Jeremias 23
Biblica® ní oore ọ̀fẹ́ láti lo Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde-Òní (YOR) vs NVT
1 “Ègbé ni fún àwọn olùṣọ́-àgùntàn tí ń tú agbo ẹran mi ká tí ó sì ń pa wọ́n run!” ni Olúwa wí.
1 “Que aflição espera os pastores de minhas ovelhas, pois destruíram e dispersaram aqueles de quem deviam cuidar”, diz o S enhor .
2 Nítorí náà, èyí ni ohun tí Olúwa Ọlọ́run Israẹli sọ ní ti àwọn olùṣọ́-àgùntàn tí ń darí àwọn ènìyàn mi: “Nítorí tí ẹ̀yin tú agbo ẹran mi ká, tí ẹ lé wọn dànù tí ẹ̀yin kò sì bẹ̀ wọ́n wò. Èmi yóò jẹ yín ní yà nítorí nǹkan búburú tí ẹ ti ṣe,” ni Olúwa wí.
2 Portanto, assim diz o S enhor , o Deus de Israel, a esses líderes do povo: “Em vez de cuidarem do meu rebanho e o conduzirem em segurança, vocês o abandonaram e o levaram à destruição. Agora, eu os castigarei pelo mal que fizeram.
3 “Èmi Olúwa tìkára mi yóò kó ìyókù agbo ẹran mi jọ láti inú gbogbo orílẹ̀-èdè tí mo ti lé wọn, Èmi yóò mú wọn padà sínú pápá oko wọn, níbẹ̀ ni wọn ó ti bí sí i, tí wọn ó sì pọ̀ sí i.
3 Contudo, reunirei o remanescente do meu rebanho das terras para onde os expulsei. Eu os trarei de volta para seu curral, e eles serão férteis e se multiplicarão.
4 Èmi ó wá olùṣọ́-àgùntàn fún wọn, tí yóò darí wọn, wọn kì yóò bẹ̀rù tàbí dààmú, bẹ́ẹ̀ ni ọ̀kan kì yóò sọnù,” ni Olúwa wí.
4 Em seguida, nomearei bons pastores que cuidarão dessas ovelhas. Elas nunca mais terão medo, e nenhuma delas se perderá. Eu, o S enhor , falei!
5 “Ọjọ́ ń bọ̀,” ni Olúwa wí,
5 “Pois está chegando o dia”, diz o S “em que levantarei um Renovo, um descendente justo, da linhagem do rei Davi. Ele reinará com sabedoria e fará o que é justo e certo em toda a terra.
6 Ní ọjọ́ rẹ̀ ni a ó gba Juda là,
6 E este será seu nome: ‘O S Nesse dia, Judá será salvo, e Israel viverá em segurança.
7 Nítorí náà, ọjọ́ ń bọ̀,” ni Olúwa wí, “tí ènìyàn kì yóò tún wí pé, ‘Dájúdájú Olúwa wà láààyè tí ó mú àwọn ọmọ Israẹli jáde kúrò ní ilẹ̀ Ejibiti.’
7 “Está chegando o dia”, diz o S enhor , “em que as pessoas que fizerem um juramento não dirão: ‘Tão certo como vive o S enhor , que tirou o povo de Israel da terra do Egito’.
8 Ṣùgbọ́n wọn yóò máa wí pé, ‘Dájúdájú Olúwa ń bẹ tí ó mú irú-ọmọ ilé Israẹli wá láti ilẹ̀ àríwá àti láti àwọn ilẹ̀ ibi tí mo tí lé wọn lọ,’ wọn ó sì gbé inú ilẹ̀ wọn.”
8 Em vez disso, dirão: ‘Tão certo como vive o S enhor , que trouxe o povo de Israel de volta da terra do norte e de todas as nações onde os havia exilado’. Então viverão em sua própria terra.”
9 Nípa ti àwọn wòlíì èké.
9 Meu coração está quebrantado por causa dos falsos profetas, e todos os meus ossos tremem. Cambaleio como um bêbado, como alguém vencido pelo vinho, por causa das santas palavras que o S
10 Ilẹ̀ náà kún fún panṣágà ènìyàn;
10 Pois a terra está cheia de adultério e debaixo de maldição. A terra está de luto; os pastos do deserto secaram. Pois todos praticam o mal e abusam do poder.
11 “Wòlíì àti àlùfáà kò gbé ìgbé ayé ìwà-bí-Ọlọ́run;
11 “Até os sacerdotes e profetas são homens corrompidos. Vi seus atos desprezíveis aqui mesmo, em meu templo”, diz o S
12 “Nítorí náà, ọ̀nà wọn yóò di yíyọ́,
12 “Portanto, os caminhos deles se tornarão escorregadios. Serão perseguidos na escuridão, e ali cairão. Pois trarei calamidade sobre eles no tempo determinado para seu castigo. Eu, o S
13 “Láàrín àwọn wòlíì Samaria,
13 “Vi que os profetas de Samaria eram terríveis, pois profetizavam em nome de Baal e faziam Israel, meu povo, pecar.
14 Àti láàrín àwọn wòlíì Jerusalẹmu,
14 Agora, porém, vejo que os profetas de Jerusalém são ainda piores; cometem adultério, gostam da desonestidade e incentivam quem pratica o mal, para que ninguém se arrependa de sua maldade. Esses profetas são tão perversos quanto os habitantes de Sodoma e Gomorra.”
15 Nítorí náà, báyìí ni Olúwa Ọlọ́run Alágbára wí ní ti àwọn wòlíì:
15 Portanto, assim diz o S enhor dos Exércitos acerca dos profetas: “Eu os alimentarei com amargura e lhes darei veneno para beber, pois foi por causa dos profetas de Jerusalém que a perversidade encheu esta terra”.
16 Èyí ni ohun tí Olúwa àwọn ọmọ-ogun wí:
16 Assim diz o S enhor dos Exércitos a seu povo: “Não deem ouvidos a esses profetas quando profetizam para vocês e os enchem de falsas esperanças. Eles inventam tudo que dizem; não falam da parte do S
17 Wọ́n ń sọ fún àwọn tí ó ń gàn mí pé,
17 Vivem repetindo aos que desprezam minha palavra: ‘O S E aos que seguem os desejos teimosos de seu coração, dizem: ‘Nada de mal lhes acontecerá!’.
18 Ṣùgbọ́n èwo nínú wọn ni ó dúró
18 “Acaso algum desses profetas esteve na presença do S enhor para ouvir suas palavras? Algum deles prestou atenção e obedeceu?
19 Wò ó, afẹ́fẹ́ Olúwa yóò tú jáde
19 Vejam, a ira do S enhor irrompe como uma tempestade, um vendaval sobre a cabeça dos perversos!
20 Ìbínú Olúwa kì yóò yẹ̀
20 A ira do S enhor não passará até que ele cumpra tudo que planejou. Em dias futuros, vocês entenderão tudo isso claramente.
21 Èmi kò rán àwọn wòlíì wọ̀nyí
21 “Não enviei esses profetas, mas eles correm de um lado para o outro. Não lhes dei mensagem alguma, e ainda assim continuam a profetizar.
22 Ṣùgbọ́n ì bà ṣe pé wọn dúró nínú ìgbìmọ̀ mi,
22 Se houvessem estado diante de mim e me ouvido, teriam anunciado minhas palavras e levado meu povo a se arrepender de seus maus caminhos e suas más ações.
23 “Ǹjẹ́ Ọlọ́run tòsí nìkan ni Èmi bí?”
23 Acaso sou Deus apenas de perto?”, diz o S enhor . “Não sou Deus também de longe?
24 Ǹjẹ́ ẹnikẹ́ni lè sá pamọ́ sí ibi kọ́lọ́fín kan,
24 Pode alguém se esconder de mim onde eu não veja? Não estou em toda parte, nos céus e na terra?”, diz o S
25 “Mo ti gbọ́ gbogbo ohun tí àwọn wòlíì èké tí ń sọ àsọtẹ́lẹ̀ ní orúkọ mi ń sọ. Wọ́n sọ wí pé, ‘Mo lá àlá! Mo lá àlá!’
25 “Ouvi esses profetas dizerem: ‘Tive um sonho! Tive um sonho!’ e depois contarem mentiras em meu nome.
26 Títí di ìgbà wo ni èyí yóò fi máa tẹ̀síwájú ni ọkàn àwọn wòlíì èké wọ̀nyí tí wọ́n ń sọ àsọtẹ́lẹ̀ ìtànjẹ ọkàn wọn?
26 Até quando isso continuará? Se são profetas, são profetas do engano e inventam tudo que dizem.
27 Wọ́n rò wí pé àlá tí wọ́n ń sọ fún ara wọn yóò mú kí àwọn ènìyàn mi gbàgbé orúkọ mi, gẹ́gẹ́ bí àwọn baba wọn ṣe gbàgbé orúkọ mi nípa sí sin òrìṣà Baali.
27 Relatando esses sonhos falsos, procuram fazer meu povo se esquecer de mim, como seus antepassados se esqueceram de mim ao adorar os ídolos de Baal.
28 Jẹ́ kí wòlíì tí ó bá lá àlá sọ àlá rẹ̀, ṣùgbọ́n jẹ́ kí ẹni tí ó ní ọ̀rọ̀ mí sọ ọ́ ní òtítọ́. Kí ni koríko gbígbẹ ní í ṣe nínú ọkà?” ni Olúwa wí.
28 “Que esses falsos profetas relatem seus sonhos, mas que meus verdadeiros mensageiros proclamem fielmente todas as minhas palavras; há diferença entre palha e trigo!
29 “Ọ̀rọ̀ mi kò ha a dàbí iná?” ni Olúwa wí, “àti bí òòlù irin tí ń fọ́ àpáta túútúú?
29 Acaso minha palavra não arde como fogo?”, diz o S “Não é como martelo que despedaça a rocha?
30 “Nítorí náà, èmi lòdì sí àwọn wòlíì ni,” Olúwa wí, “Tí ń jí ọ̀rọ̀ tí ó yẹ kí ó ti ọ̀dọ̀ mi wá lò lọ́dọ̀ ara wọn.
30 “Portanto”, diz o S enhor , “sou contra esses profetas que roubam palavras uns dos outros e afirmam que as receberam de mim.
31 Bẹ́ẹ̀,” ni Olúwa wí, “Èmi lòdì sí àwọn wòlíì tí wọ́n lo ahọ́n wọn káàkiri, síbẹ̀ tí wọ́n ń sọ wí pé, ‘Olúwa wí.’
31 Sou contra esses profetas cheios de lábia que dizem: ‘Esta profecia é do S enhor !’.
32 Nítòótọ́, mo lòdì sí àwọn tí ń sọ àsọtẹ́lẹ̀ nípa àlá èké,” ni Olúwa wí. “Wọ́n ń sọ bẹ́ẹ̀ ni wọ́n sì ń mú àwọn ènìyàn mi ṣìnà nípa onírúurú èké wọn, síbẹ̀ èmi kò rán wọn tàbí yàn wọ́n. Wọn kò sì ran àwọn ènìyàn wọ̀nyí lọ́wọ́ bí ó ti wù kí ó kéré mọ,” ni Olúwa wí.
32 Sou contra esses falsos profetas. Seus sonhos imaginários são mentiras descaradas que fazem meu povo pecar. Não os enviei nem os nomeei, e eles não têm nada a dizer a este povo. Eu, o S enhor , falei!”
33 “Nígbà tí àwọn ènìyàn wọ̀nyí, tàbí wòlíì tàbí àlùfáà bá bi ọ́ léèrè wí pé, ‘Kí ni ọ̀rọ̀-ìjìnlẹ̀ Olúwa?’ Sọ fún wọn wí pé, ‘Ọ̀rọ̀-ìjìnlẹ̀ wo? Èmi yóò pa yín tì ni Olúwa wí.’
33 “Se alguém do povo, ou algum dos profetas ou dos sacerdotes lhe perguntar: ‘Que palavras pesadas o S enhor lhe deu para anunciar hoje?’, responda: ‘Vocês são o peso! O S enhor diz que os abandonará!’.
34 Bí wòlíì tàbí àlùfáà tàbí ẹnikẹ́ni bá sì gbà wí pé, ‘Èyí ni ọ̀rọ̀-ìjìnlẹ̀ Olúwa.’ Èmi yóò fi ìyà jẹ ọkùnrin náà àti gbogbo agbo ilé rẹ̀.
34 “Se algum profeta, sacerdote ou qualquer outra pessoa disser: ‘Tenho uma profecia do S enhor ’, castigarei essa pessoa e toda a sua família.
35 Èyí ni ohun tí ẹnìkọ̀ọ̀kan yín ń sọ fún ọ̀rẹ́ àti ará ilé rẹ̀: ‘Kí ni ìdáhùn Olúwa?’ Tàbí ‘Kí ni ohun tí Olúwa sọ?’
35 Perguntem uns aos outros: ‘Qual é a resposta do S enhor ?’, ou ‘O que o S enhor diz?’.
36 Ṣùgbọ́n ẹ̀yin kò gbọdọ̀ dárúkọ ọ̀rọ̀ ‘ìjìnlẹ̀ Olúwa’ mọ́, nítorí pé ọ̀rọ̀ oníkálùkù ènìyàn di ọ̀rọ̀-ìjìnlẹ̀ rẹ̀. Nítorí náà, ẹ̀yin ń yí ọ̀rọ̀ Ọlọ́run alààyè, Olúwa àwọn ọmọ-ogun, Ọlọ́run wa padà.
36 Mas parem de usar a expressão ‘profecia do S enhor ’. Pois alguns a usam para conferir autoridade às próprias ideias e distorcem as palavras de nosso Deus, o Deus vivo, o S enhor dos Exércitos.
37 Èyí ni ohun tí ẹ̀yin ń sọ fún wòlíì: ‘Kí ni ìdáhùn Olúwa sí ọ́?’ Tàbí ‘Kí ni ohun tí Olúwa bá ọ sọ?’
37 “Isto é o que você dirá aos profetas: ‘Qual é a resposta do S enhor ?’, ou ‘O que o S enhor diz?’.
38 Bí ó tilẹ̀ jẹ́ pé ẹ̀yin ń sọ wí pé, ‘Èyí ni ọ̀rọ̀-ìjìnlẹ̀ Olúwa,’ èyí ni ohun tí Olúwa sọ, Ẹ̀yin ń lo ọ̀rọ̀ yìí, ‘Èyí ni ọ̀rọ̀-ìjìnlẹ̀ Olúwa,’ bí ó tilẹ̀ jẹ́ pé mo sọ fún un yín láti má ṣe lò ó mọ́, ‘Èyí ni ọ̀rọ̀-ìjìnlẹ̀ Olúwa.’
38 Mas, se responderem: ‘Esta é uma profecia do S enhor !’, você deve dizer: ‘Assim diz o S enhor : Porque usaram a expressão ‘profecia do S enhor ’, embora eu os tenha advertido de que não a usassem,
39 Nítorí náà, Èmi yóò gbàgbé yín, bẹ́ẹ̀ ni n ó lé e yín kúrò níwájú mi pẹ̀lú àwọn ìlú tí mo fi fún un yín àti àwọn baba yín.
39 eu me esquecerei completamente de vocês. Sim, os expulsarei de minha presença, junto com esta cidade que dei a vocês e a seus antepassados.
40 Èmi yóò sì mú ìtìjú ayérayé wá sí orí yín, ìtìjú tí kò ní ní ìgbàgbé.”
40 Farei de vocês objeto de ridículo, e seu nome será infame para sempre’.”
Atalhos do teclado
- Capítulo anterior←
- Próximo capítulo→
- Versículo anteriork
- Próximo versículoj
- Limpar seleçãoEsc
- Esta ajuda?
Estude este capítulo no WhatsApp
Peça à IA da Bíblia Fala para explicar Jeremias 23, comparar traduções ou montar um estudo — tudo direto pelo WhatsApp.