Jeremias 23

Biblica® ní oore ọ̀fẹ́ láti lo Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde-Òní (YOR) vs BKJ

Sair da comparação
1 “Ègbé ni fún àwọn olùṣọ́-àgùntàn tí ń tú agbo ẹran mi ká tí ó sì ń pa wọ́n run!” ni Olúwa wí.
1 Ai dos pastores que destroem e espalham as ovelhas do meu pasto, diz o SENHOR.
2 Nítorí náà, èyí ni ohun tí Olúwa Ọlọ́run Israẹli sọ ní ti àwọn olùṣọ́-àgùntàn tí ń darí àwọn ènìyàn mi: “Nítorí tí ẹ̀yin tú agbo ẹran mi ká, tí ẹ lé wọn dànù tí ẹ̀yin kò sì bẹ̀ wọ́n wò. Èmi yóò jẹ yín ní yà nítorí nǹkan búburú tí ẹ ti ṣe,” ni Olúwa wí.
2 Portanto assim diz o SENHOR Deus de Israel contra os pastores que apascentam o meu povo: Vós espalhastes o meu rebanho, e os afugentastes, e não os visitastes. Eis que eu visitarei sobre vós o mal de vossos feitos, diz o SENHOR.
3 “Èmi Olúwa tìkára mi yóò kó ìyókù agbo ẹran mi jọ láti inú gbogbo orílẹ̀-èdè tí mo ti lé wọn, Èmi yóò mú wọn padà sínú pápá oko wọn, níbẹ̀ ni wọn ó ti bí sí i, tí wọn ó sì pọ̀ sí i.
3 E eu recolherei o remanescente do meu rebanho de todas as regiões para onde eu os levei, e os trarei novamente para os seus apriscos, e eles serão frutíferos e aumentados.
4 Èmi ó wá olùṣọ́-àgùntàn fún wọn, tí yóò darí wọn, wọn kì yóò bẹ̀rù tàbí dààmú, bẹ́ẹ̀ ni ọ̀kan kì yóò sọnù,” ni Olúwa wí.
4 E eu levantarei pastores sobre elas, os quais as apascentarão e elas não mais temerão, nem estarão consternadas, e nenhum deles faltará, diz o SENHOR.
5 “Ọjọ́ ń bọ̀,” ni Olúwa wí,
5 Eis que os dias vêm, diz o SENHOR, em que eu levantarei para Davi um Renovo justo, e um Rei reinará e prosperará, e executará juízo e justiça na terra.
6 Ní ọjọ́ rẹ̀ ni a ó gba Juda là,
6 Nos seus dias Judá será salvo e Israel habitará a salvo. E este é seu nome, pelo qual ele será chamado: o Senhor Nossa Justiça.
7 Nítorí náà, ọjọ́ ń bọ̀,” ni Olúwa wí, “tí ènìyàn kì yóò tún wí pé, ‘Dájúdájú Olúwa wà láààyè tí ó mú àwọn ọmọ Israẹli jáde kúrò ní ilẹ̀ Ejibiti.’
7 Portanto, eis que os dias vêm, diz o SENHOR, em que eles não mais dirão: O SENHOR vive, que tirou os filhos de Israel da terra do Egito,
8 Ṣùgbọ́n wọn yóò máa wí pé, ‘Dájúdájú Olúwa ń bẹ tí ó mú irú-ọmọ ilé Israẹli wá láti ilẹ̀ àríwá àti láti àwọn ilẹ̀ ibi tí mo tí lé wọn lọ,’ wọn ó sì gbé inú ilẹ̀ wọn.”
8 porém dirão: O SENHOR vive, aquele que conduziu a semente da casa de Israel desde a região do norte, e desde todas as regiões para onde eu os levei; e eles habitarão em sua própria terra.
9 Nípa ti àwọn wòlíì èké.
9 Por causa dos profetas, o meu coração está quebrantado dentro de mim. Todos os meus ossos estremecem. Eu sou como um homem bêbado, e como um homem a quem o vinho domina, por causa do SENHOR, e por causa das palavras da sua santidade.
10 Ilẹ̀ náà kún fún panṣágà ènìyàn;
10 Porque a terra está repleta de adúlteros; pois por causa de juramentos a terra geme; os lugares agradáveis do deserto estão secos, e o seu percurso é o mal, e a sua força não é correta.
11 “Wòlíì àti àlùfáà kò gbé ìgbé ayé ìwà-bí-Ọlọ́run;
11 Pois tanto o profeta quanto o sacerdote são profanos. Sim, em minha casa encontrei a sua perversidade, diz o SENHOR.
12 “Nítorí náà, ọ̀nà wọn yóò di yíyọ́,
12 Portanto, o seu caminho lhes será como caminhos escorregadios na escuridão. Eles serão empurrados, e cairão nele, porque eu trarei o mal sobre eles, no ano da sua visitação, diz o SENHOR.
13 “Láàrín àwọn wòlíì Samaria,
13 E eu vi a loucura nos profetas de Samaria; eles profetizaram da parte de Baal, e fizeram o meu povo Israel errar.
14 Àti láàrín àwọn wòlíì Jerusalẹmu,
14 Eu também vi nos profetas de Jerusalém uma coisa horrível: Eles cometem adultério, e andam em mentiras; eles também fortalecem as mãos dos malfeitores, para que ninguém se arrependa de sua perversidade. Todos eles são para mim como Sodoma, e os seus habitantes como Gomorra.
15 Nítorí náà, báyìí ni Olúwa Ọlọ́run Alágbára wí ní ti àwọn wòlíì:
15 Portanto assim diz o SENHOR dos Exércitos a respeito dos profetas: Eis que eu os alimentarei com absinto, e os farei beber água de fel, pois dos profetas de Jerusalém saiu uma profanação para toda a terra.
16 Èyí ni ohun tí Olúwa àwọn ọmọ-ogun wí:
16 Assim diz o SENHOR dos Exércitos: Não escuteis as palavras dos profetas que profetizam para vós; eles vos farão vãos. Eles falam da visão do seu próprio coração, e não proveniente da boca do SENHOR.
17 Wọ́n ń sọ fún àwọn tí ó ń gàn mí pé,
17 Eles ainda dizem para aqueles que me desprezam: O SENHOR disse: Vós tereis paz; e eles dizem para cada um que anda após a imaginação de seu próprio coração: Nenhum mal virá sobre vós.
18 Ṣùgbọ́n èwo nínú wọn ni ó dúró
18 Porquanto, quem esteve no conselho do SENHOR, percebeu e ouviu a sua palavra? Quem deu atenção a sua palavra e a ouviu?
19 Wò ó, afẹ́fẹ́ Olúwa yóò tú jáde
19 Eis que um furacão do SENHOR surgiu em fúria, um furacão desolador, que cairá dolorosamente sobre a cabeça do perverso.
20 Ìbínú Olúwa kì yóò yẹ̀
20 A ira do SENHOR não retornará até que ele tenha executado, e realizado os pensamentos do seu coração. Nos últimos dias vós ponderareis a respeito disto perfeitamente.
21 Èmi kò rán àwọn wòlíì wọ̀nyí
21 Eu não enviei estes profetas, contudo eles foram correndo; eu não lhes falei, contudo, eles profetizaram.
22 Ṣùgbọ́n ì bà ṣe pé wọn dúró nínú ìgbìmọ̀ mi,
22 Porém se eles estivessem em meu conselho, e tivessem feito o meu povo ouvir as minhas palavras, então eles os desviariam do seu mau caminho, e do mal de seus feitos.
23 “Ǹjẹ́ Ọlọ́run tòsí nìkan ni Èmi bí?”
23 Sou um Deus só de perto e não de longe? Diz o SENHOR.
24 Ǹjẹ́ ẹnikẹ́ni lè sá pamọ́ sí ibi kọ́lọ́fín kan,
24 Pode alguém esconder-se em lugares secretos para que eu não seja capaz de vê-lo? diz o SENHOR. Não preencho eu céu e terra? diz o SENHOR.
25 “Mo ti gbọ́ gbogbo ohun tí àwọn wòlíì èké tí ń sọ àsọtẹ́lẹ̀ ní orúkọ mi ń sọ. Wọ́n sọ wí pé, ‘Mo lá àlá! Mo lá àlá!’
25 Eu ouvi o que os profetas disseram, que profetizam mentiras em meu nome, dizendo: Eu sonhei, eu sonhei.
26 Títí di ìgbà wo ni èyí yóò fi máa tẹ̀síwájú ni ọkàn àwọn wòlíì èké wọ̀nyí tí wọ́n ń sọ àsọtẹ́lẹ̀ ìtànjẹ ọkàn wọn?
26 Até quando isto estará no coração dos profetas, que profetizam mentiras? Sim, eles são profetas do engano do seu próprio coração.
27 Wọ́n rò wí pé àlá tí wọ́n ń sọ fún ara wọn yóò mú kí àwọn ènìyàn mi gbàgbé orúkọ mi, gẹ́gẹ́ bí àwọn baba wọn ṣe gbàgbé orúkọ mi nípa sí sin òrìṣà Baali.
27 Os quais pensam fazer meu povo esquecer o meu nome, por meio dos seus sonhos, que cada homem conta ao seu próximo, do mesmo modo que os seus pais esqueceram o meu nome por Baal.
28 Jẹ́ kí wòlíì tí ó bá lá àlá sọ àlá rẹ̀, ṣùgbọ́n jẹ́ kí ẹni tí ó ní ọ̀rọ̀ mí sọ ọ́ ní òtítọ́. Kí ni koríko gbígbẹ ní í ṣe nínú ọkà?” ni Olúwa wí.
28 Ao profeta que tem um sonho, conte o sonho, e aquele que tem a minha palavra, deixe-o falar a minha palavra fielmente. O que tem a palha com o trigo? diz o SENHOR.
29 “Ọ̀rọ̀ mi kò ha a dàbí iná?” ni Olúwa wí, “àti bí òòlù irin tí ń fọ́ àpáta túútúú?
29 Não é minha palavra como um fogo, diz o SENHOR, e como um martelo que quebra a rocha em pedaços?
30 “Nítorí náà, èmi lòdì sí àwọn wòlíì ni,” Olúwa wí, “Tí ń jí ọ̀rọ̀ tí ó yẹ kí ó ti ọ̀dọ̀ mi wá lò lọ́dọ̀ ara wọn.
30 Portanto, eis que eu sou contra os profetas, diz o SENHOR, que roubam as minhas palavras, cada um ao seu próximo.
31 Bẹ́ẹ̀,” ni Olúwa wí, “Èmi lòdì sí àwọn wòlíì tí wọ́n lo ahọ́n wọn káàkiri, síbẹ̀ tí wọ́n ń sọ wí pé, ‘Olúwa wí.’
31 Eis que eu sou contra os profetas, diz o SENHOR, que usam suas línguas e dizem: Ele diz.
32 Nítòótọ́, mo lòdì sí àwọn tí ń sọ àsọtẹ́lẹ̀ nípa àlá èké,” ni Olúwa wí. “Wọ́n ń sọ bẹ́ẹ̀ ni wọ́n sì ń mú àwọn ènìyàn mi ṣìnà nípa onírúurú èké wọn, síbẹ̀ èmi kò rán wọn tàbí yàn wọ́n. Wọn kò sì ran àwọn ènìyàn wọ̀nyí lọ́wọ́ bí ó ti wù kí ó kéré mọ,” ni Olúwa wí.
32 Eis que eu sou contra aqueles que profetizam falsos sonhos, diz o SENHOR, e os contam, e fazem meu povo errar por meio das suas mentiras, e por meio de suas leviandades. Contudo, eu não os enviei nem os ordenei. Portanto eles não beneficiarão este povo de modo algum, diz o SENHOR.
33 “Nígbà tí àwọn ènìyàn wọ̀nyí, tàbí wòlíì tàbí àlùfáà bá bi ọ́ léèrè wí pé, ‘Kí ni ọ̀rọ̀-ìjìnlẹ̀ Olúwa?’ Sọ fún wọn wí pé, ‘Ọ̀rọ̀-ìjìnlẹ̀ wo? Èmi yóò pa yín tì ni Olúwa wí.’
33 E quando este povo, ou o profeta, ou um sacerdote, vier a te perguntar, dizendo: Qual é o fardo do SENHOR? Tu então lhes dirás: Que fardo? Que eu vos abandonarei, diz o SENHOR.
34 Bí wòlíì tàbí àlùfáà tàbí ẹnikẹ́ni bá sì gbà wí pé, ‘Èyí ni ọ̀rọ̀-ìjìnlẹ̀ Olúwa.’ Èmi yóò fi ìyà jẹ ọkùnrin náà àti gbogbo agbo ilé rẹ̀.
34 E quanto ao profeta, e ao sacerdote, e ao povo, que dirão: O fardo do SENHOR. Eu punirei esse homem e a sua casa.
35 Èyí ni ohun tí ẹnìkọ̀ọ̀kan yín ń sọ fún ọ̀rẹ́ àti ará ilé rẹ̀: ‘Kí ni ìdáhùn Olúwa?’ Tàbí ‘Kí ni ohun tí Olúwa sọ?’
35 Desta forma direis vós cada um a seu próximo, e cada um a seu irmão: O que o SENHOR respondeu? E: O que o SENHOR falou?
36 Ṣùgbọ́n ẹ̀yin kò gbọdọ̀ dárúkọ ọ̀rọ̀ ‘ìjìnlẹ̀ Olúwa’ mọ́, nítorí pé ọ̀rọ̀ oníkálùkù ènìyàn di ọ̀rọ̀-ìjìnlẹ̀ rẹ̀. Nítorí náà, ẹ̀yin ń yí ọ̀rọ̀ Ọlọ́run alààyè, Olúwa àwọn ọmọ-ogun, Ọlọ́run wa padà.
36 E o fardo do SENHOR não mencionareis mais, porque a palavra de cada homem será o seu fardo, pois vós pervertestes as palavras do Deus vivo, do SENHOR dos Exércitos, nosso Deus.
37 Èyí ni ohun tí ẹ̀yin ń sọ fún wòlíì: ‘Kí ni ìdáhùn Olúwa sí ọ́?’ Tàbí ‘Kí ni ohun tí Olúwa bá ọ sọ?’
37 Assim dirás ao profeta: O que o SENHOR te respondeu? E: O que falou o SENHOR?
38 Bí ó tilẹ̀ jẹ́ pé ẹ̀yin ń sọ wí pé, ‘Èyí ni ọ̀rọ̀-ìjìnlẹ̀ Olúwa,’ èyí ni ohun tí Olúwa sọ, Ẹ̀yin ń lo ọ̀rọ̀ yìí, ‘Èyí ni ọ̀rọ̀-ìjìnlẹ̀ Olúwa,’ bí ó tilẹ̀ jẹ́ pé mo sọ fún un yín láti má ṣe lò ó mọ́, ‘Èyí ni ọ̀rọ̀-ìjìnlẹ̀ Olúwa.’
38 Porém visto que vós dizeis: O fardo do SENHOR, portanto assim diz o SENHOR: Porque vós dizeis esta palavra: O fardo do SENHOR, e eu vos enviei, dizendo, não ireis dizer: O fardo do SENHOR.
39 Nítorí náà, Èmi yóò gbàgbé yín, bẹ́ẹ̀ ni n ó lé e yín kúrò níwájú mi pẹ̀lú àwọn ìlú tí mo fi fún un yín àti àwọn baba yín.
39 Portanto, eis que, esquecer-me-ei completamente de vós, e eu vos abandonarei, e a cidade que eu vos dei, e a vossos pais, e retirar-vos-ei da minha presença.
40 Èmi yóò sì mú ìtìjú ayérayé wá sí orí yín, ìtìjú tí kò ní ní ìgbàgbé.”
40 E eu vos trarei uma eterna desonra e uma perpétua vergonha, que não será esquecida.

Ler em outra tradução

Comparar com outra

Estude este capítulo no WhatsApp

Peça à IA da Bíblia Fala para explicar Jeremias 23, comparar traduções ou montar um estudo — tudo direto pelo WhatsApp.