Jeremias 23

Biblica® ní oore ọ̀fẹ́ láti lo Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde-Òní (YOR) vs NAA

Sair da comparação
NAA Nova Almeida Atualizada 2017
1 “Ègbé ni fún àwọn olùṣọ́-àgùntàn tí ń tú agbo ẹran mi ká tí ó sì ń pa wọ́n run!” ni Olúwa wí.
1 — Ai dos pastores que destroem e dispersam as ovelhas do meu pasto! — diz o Senhor .
2 Nítorí náà, èyí ni ohun tí Olúwa Ọlọ́run Israẹli sọ ní ti àwọn olùṣọ́-àgùntàn tí ń darí àwọn ènìyàn mi: “Nítorí tí ẹ̀yin tú agbo ẹran mi ká, tí ẹ lé wọn dànù tí ẹ̀yin kò sì bẹ̀ wọ́n wò. Èmi yóò jẹ yín ní yà nítorí nǹkan búburú tí ẹ ti ṣe,” ni Olúwa wí.
2 Portanto, assim diz o Senhor , o Deus de Israel, a respeito dos pastores que apascentam o meu povo: “Vocês dispersaram as minhas ovelhas e as afugentaram, e não cuidaram delas. Mas eu tratarei de castigar vocês por causa das maldades que praticaram, diz o Senhor .
3 “Èmi Olúwa tìkára mi yóò kó ìyókù agbo ẹran mi jọ láti inú gbogbo orílẹ̀-èdè tí mo ti lé wọn, Èmi yóò mú wọn padà sínú pápá oko wọn, níbẹ̀ ni wọn ó ti bí sí i, tí wọn ó sì pọ̀ sí i.
3 Eu mesmo recolherei o remanescente das minhas ovelhas, de todas as terras para onde as tiver dispersado, e as farei voltar aos seus apriscos; serão fecundas e se multiplicarão.
4 Èmi ó wá olùṣọ́-àgùntàn fún wọn, tí yóò darí wọn, wọn kì yóò bẹ̀rù tàbí dààmú, bẹ́ẹ̀ ni ọ̀kan kì yóò sọnù,” ni Olúwa wí.
4 Porei sobre elas pastores que as apascentem, e elas jamais terão medo, nem ficarão assustadas; nem uma delas faltará, diz o Senhor .”
5 “Ọjọ́ ń bọ̀,” ni Olúwa wí,
5 — Eis que vêm dias, diz o Senhor , em que levantarei a Davi um Renovo justo; e, como rei que é, reinará, agirá com sabedoria e executará o juízo e a justiça na terra.
6 Ní ọjọ́ rẹ̀ ni a ó gba Juda là,
6 Nos seus dias, Judá será salvo, e Israel habitará seguro. E este será o nome pelo qual será chamado: “ Senhor , Justiça Nossa”.
7 Nítorí náà, ọjọ́ ń bọ̀,” ni Olúwa wí, “tí ènìyàn kì yóò tún wí pé, ‘Dájúdájú Olúwa wà láààyè tí ó mú àwọn ọmọ Israẹli jáde kúrò ní ilẹ̀ Ejibiti.’
7 — Portanto, eis que vêm dias, diz o Senhor , em que nunca mais dirão: “Tão certo como vive o Senhor , que tirou os filhos de Israel da terra do Egito”,
8 Ṣùgbọ́n wọn yóò máa wí pé, ‘Dájúdájú Olúwa ń bẹ tí ó mú irú-ọmọ ilé Israẹli wá láti ilẹ̀ àríwá àti láti àwọn ilẹ̀ ibi tí mo tí lé wọn lọ,’ wọn ó sì gbé inú ilẹ̀ wọn.”
8 mas: “Tão certo como vive o Senhor , que tirou e trouxe a descendência da casa de Israel da terra do Norte e de todas as terras para onde os tinha dispersado”. E habitarão na sua própria terra.
9 Nípa ti àwọn wòlíì èké.
9 A respeito dos profetas: “O meu coração está partido dentro de mim. Todos os meus ossos estremecem. Sou como um homem embriagado e como um homem vencido pelo vinho, por causa do e por causa das suas santas palavras.
10 Ilẹ̀ náà kún fún panṣágà ènìyàn;
10 Porque a terra está cheia de adúlteros e chora por causa da maldição divina; os pastos do deserto estão secos. Porque o modo de vida deles é mau, e seu uso da força não é reto.”
11 “Wòlíì àti àlùfáà kò gbé ìgbé ayé ìwà-bí-Ọlọ́run;
11 “Pois tanto o profeta como o sacerdote estão contaminados; até na minha casa achei a sua maldade”, diz o
12 “Nítorí náà, ọ̀nà wọn yóò di yíyọ́,
12 “Portanto, o caminho deles será como lugares escorregadios na escuridão, para a qual serão empurrados e na qual cairão. Porque trarei sobre eles a calamidade, o ano da sua punição”, diz o
13 “Láàrín àwọn wòlíì Samaria,
13 “Nos profetas de Samaria vi algo que causa desgosto: profetizaram por Baal e fizeram o meu povo de Israel andar errante.
14 Àti láàrín àwọn wòlíì Jerusalẹmu,
14 Mas nos profetas de Jerusalém vejo coisa horrenda: cometem adultério, andam com falsidade e fortalecem as mãos dos malfeitores, para que não se convertam da sua maldade. Para mim, todos eles se tornaram como Sodoma, e os moradores de Jerusalém, como Gomorra.
15 Nítorí náà, báyìí ni Olúwa Ọlọ́run Alágbára wí ní ti àwọn wòlíì:
15 Portanto, assim diz o a respeito dos profetas: Eis que os alimentarei com absinto e lhes darei de beber água envenenada; porque dos profetas de Jerusalém se derramou a impiedade sobre toda a terra.”
16 Èyí ni ohun tí Olúwa àwọn ọmọ-ogun wí:
16 Assim diz o Senhor dos Exércitos: — Não deem ouvidos às palavras dos profetas que profetizam entre vocês e que os enchem de falsas esperanças; falam as visões do seu coração, não o que vem da boca do
17 Wọ́n ń sọ fún àwọn tí ó ń gàn mí pé,
17 Dizem continuamente aos que me desprezam: “O Senhor disse: Vocês terão paz”; e a todos os que andam segundo a dureza do seu coração dizem: “Nenhum mal lhes sobrevirá.”
18 Ṣùgbọ́n èwo nínú wọn ni ó dúró
18 Porque quem esteve no conselho do e viu, e ouviu a sua palavra? Quem esteve atento à sua palavra e a ouviu?
19 Wò ó, afẹ́fẹ́ Olúwa yóò tú jáde
19 Eis a tempestade do Senhor ! O furor saiu, e um vendaval passou sobre a cabeça dos ímpios.
20 Ìbínú Olúwa kì yóò yẹ̀
20 A ira do Senhor não se desviará até que ele execute e cumpra os desígnios do seu coração. Nos últimos dias, vocês entenderão isso claramente.
21 Èmi kò rán àwọn wòlíì wọ̀nyí
21 “Não mandei esses profetas, mas eles foram correndo; não lhes falei, mas eles profetizaram.
22 Ṣùgbọ́n ì bà ṣe pé wọn dúró nínú ìgbìmọ̀ mi,
22 Mas, se tivessem estado no meu conselho, teriam anunciado as minhas palavras ao meu povo e o teriam feito voltar do seu mau caminho e da maldade das suas ações.”
23 “Ǹjẹ́ Ọlọ́run tòsí nìkan ni Èmi bí?”
23 — Sou eu Deus apenas de perto, diz o Senhor , e não também Deus de longe?
24 Ǹjẹ́ ẹnikẹ́ni lè sá pamọ́ sí ibi kọ́lọ́fín kan,
24 Pode alguém se ocultar em esconderijos, de modo que eu não o veja? — diz o Senhor . Não encho eu os céus e a terra? — diz o Senhor .
25 “Mo ti gbọ́ gbogbo ohun tí àwọn wòlíì èké tí ń sọ àsọtẹ́lẹ̀ ní orúkọ mi ń sọ. Wọ́n sọ wí pé, ‘Mo lá àlá! Mo lá àlá!’
25 Tenho ouvido o que dizem aqueles profetas, proclamando mentiras em meu nome, dizendo: “Sonhei, sonhei.”
26 Títí di ìgbà wo ni èyí yóò fi máa tẹ̀síwájú ni ọkàn àwọn wòlíì èké wọ̀nyí tí wọ́n ń sọ àsọtẹ́lẹ̀ ìtànjẹ ọkàn wọn?
26 Até quando acontecerá isso no coração dos profetas que proclamam mentiras, que proclamam só o engano do próprio coração?
27 Wọ́n rò wí pé àlá tí wọ́n ń sọ fún ara wọn yóò mú kí àwọn ènìyàn mi gbàgbé orúkọ mi, gẹ́gẹ́ bí àwọn baba wọn ṣe gbàgbé orúkọ mi nípa sí sin òrìṣà Baali.
27 Até quando tentarão fazer com que o meu povo se esqueça do meu nome por meio dos sonhos que contam uns aos outros, assim como os pais deles se esqueceram do meu nome, por causa de Baal?
28 Jẹ́ kí wòlíì tí ó bá lá àlá sọ àlá rẹ̀, ṣùgbọ́n jẹ́ kí ẹni tí ó ní ọ̀rọ̀ mí sọ ọ́ ní òtítọ́. Kí ni koríko gbígbẹ ní í ṣe nínú ọkà?” ni Olúwa wí.
28 O profeta que tem um sonho conte-o como um simples sonho. Mas aquele em quem está a minha palavra fale a minha palavra com verdade. O que é que a palha tem a ver com o trigo? — diz o Senhor .
29 “Ọ̀rọ̀ mi kò ha a dàbí iná?” ni Olúwa wí, “àti bí òòlù irin tí ń fọ́ àpáta túútúú?
29 Não é a minha palavra como fogo, diz o Senhor , e como um martelo que despedaça a rocha?
30 “Nítorí náà, èmi lòdì sí àwọn wòlíì ni,” Olúwa wí, “Tí ń jí ọ̀rọ̀ tí ó yẹ kí ó ti ọ̀dọ̀ mi wá lò lọ́dọ̀ ara wọn.
30 Portanto, eis que eu sou contra esses profetas, diz o Senhor , que roubam as minhas palavras uns dos outros.
31 Bẹ́ẹ̀,” ni Olúwa wí, “Èmi lòdì sí àwọn wòlíì tí wọ́n lo ahọ́n wọn káàkiri, síbẹ̀ tí wọ́n ń sọ wí pé, ‘Olúwa wí.’
31 Eis que eu sou contra esses profetas, diz o Senhor , que pregam a sua própria palavra e afirmam: “Ele disse.”
32 Nítòótọ́, mo lòdì sí àwọn tí ń sọ àsọtẹ́lẹ̀ nípa àlá èké,” ni Olúwa wí. “Wọ́n ń sọ bẹ́ẹ̀ ni wọ́n sì ń mú àwọn ènìyàn mi ṣìnà nípa onírúurú èké wọn, síbẹ̀ èmi kò rán wọn tàbí yàn wọ́n. Wọn kò sì ran àwọn ènìyàn wọ̀nyí lọ́wọ́ bí ó ti wù kí ó kéré mọ,” ni Olúwa wí.
32 Eis que eu sou contra os que profetizam sonhos mentirosos, diz o Senhor , e os contam, e com as suas mentiras e leviandades fazem o meu povo andar errante. Eu não os enviei, nem lhes dei ordem alguma; e eles não trazem nenhum proveito a este povo, diz o Senhor .
33 “Nígbà tí àwọn ènìyàn wọ̀nyí, tàbí wòlíì tàbí àlùfáà bá bi ọ́ léèrè wí pé, ‘Kí ni ọ̀rọ̀-ìjìnlẹ̀ Olúwa?’ Sọ fún wọn wí pé, ‘Ọ̀rọ̀-ìjìnlẹ̀ wo? Èmi yóò pa yín tì ni Olúwa wí.’
33 — Quando, pois, este povo ou um profeta ou um sacerdote perguntar a você, Jeremias: “Qual é a sentença pesada do Senhor ?”, responda: “Vocês são o peso, e eu os lançarei fora”, diz o Senhor .
34 Bí wòlíì tàbí àlùfáà tàbí ẹnikẹ́ni bá sì gbà wí pé, ‘Èyí ni ọ̀rọ̀-ìjìnlẹ̀ Olúwa.’ Èmi yóò fi ìyà jẹ ọkùnrin náà àti gbogbo agbo ilé rẹ̀.
34 E, se um profeta, um sacerdote, ou alguém do povo disser: “Sentença pesada do Senhor ”, castigarei esse homem e a sua casa.
35 Èyí ni ohun tí ẹnìkọ̀ọ̀kan yín ń sọ fún ọ̀rẹ́ àti ará ilé rẹ̀: ‘Kí ni ìdáhùn Olúwa?’ Tàbí ‘Kí ni ohun tí Olúwa sọ?’
35 Em vez disso, cada um deveria perguntar ao seu companheiro e ao seu irmão: “O que o Senhor respondeu? O que foi que o Senhor falou?”
36 Ṣùgbọ́n ẹ̀yin kò gbọdọ̀ dárúkọ ọ̀rọ̀ ‘ìjìnlẹ̀ Olúwa’ mọ́, nítorí pé ọ̀rọ̀ oníkálùkù ènìyàn di ọ̀rọ̀-ìjìnlẹ̀ rẹ̀. Nítorí náà, ẹ̀yin ń yí ọ̀rọ̀ Ọlọ́run alààyè, Olúwa àwọn ọmọ-ogun, Ọlọ́run wa padà.
36 Mas nunca mais vocês devem fazer menção das palavras “sentença pesada do Senhor ”, pois o que se tornará um peso para alguém é a própria palavra que ele falou. Porque vocês torcem as palavras do Deus vivo, do Senhor dos Exércitos, o nosso Deus.
37 Èyí ni ohun tí ẹ̀yin ń sọ fún wòlíì: ‘Kí ni ìdáhùn Olúwa sí ọ́?’ Tàbí ‘Kí ni ohun tí Olúwa bá ọ sọ?’
37 O que você deve perguntar a um profeta é: “O que foi que o Senhor lhe respondeu? O que foi que o Senhor falou?”
38 Bí ó tilẹ̀ jẹ́ pé ẹ̀yin ń sọ wí pé, ‘Èyí ni ọ̀rọ̀-ìjìnlẹ̀ Olúwa,’ èyí ni ohun tí Olúwa sọ, Ẹ̀yin ń lo ọ̀rọ̀ yìí, ‘Èyí ni ọ̀rọ̀-ìjìnlẹ̀ Olúwa,’ bí ó tilẹ̀ jẹ́ pé mo sọ fún un yín láti má ṣe lò ó mọ́, ‘Èyí ni ọ̀rọ̀-ìjìnlẹ̀ Olúwa.’
38 Mas, porque vocês dizem: “Sentença pesada do Senhor ”, assim diz o Senhor : Porque vocês continuam a usar as palavras “sentença pesada do Senhor ”, quando eu lhes havia proibido de fazer isso,
39 Nítorí náà, Èmi yóò gbàgbé yín, bẹ́ẹ̀ ni n ó lé e yín kúrò níwájú mi pẹ̀lú àwọn ìlú tí mo fi fún un yín àti àwọn baba yín.
39 eu os levantarei e os lançarei fora da minha presença, tanto vocês como a cidade que dei a vocês e aos seus pais.
40 Èmi yóò sì mú ìtìjú ayérayé wá sí orí yín, ìtìjú tí kò ní ní ìgbàgbé.”
40 Porei sobre vocês perpétuo desprezo e eterna vergonha, que jamais serão esquecidos.

Ler em outra tradução

Comparar com outra

Estude este capítulo no WhatsApp

Peça à IA da Bíblia Fala para explicar Jeremias 23, comparar traduções ou montar um estudo — tudo direto pelo WhatsApp.