Jó 11

Biblica® ní oore ọ̀fẹ́ láti lo Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde-Òní (YOR)

1 Ìgbà náà ni Sofari, ará Naama, dáhùn, ó sì wí pé,

2 “A ha lè ṣe kí a máa dáhùn sí ọ̀pọ̀lọpọ̀ ọ̀rọ̀?

3 Ṣé àmọ̀tán rẹ le mú ènìyàn pa ẹnu wọn mọ́ bí?

4 Ìwọ sá à ti wí fún Ọlọ́run pé, ‘Ìṣe mi jẹ́ aláìléérí,

5 Ṣùgbọ́n Ọlọ́run ìbá jẹ́ sọ̀rọ̀,

6 kí ó sì fi àṣírí ọgbọ́n hàn ọ́ pé, ó pọ̀ ju òye ènìyàn lọ,

7 “Ìwọ ha le ṣe àwárí ohun ìjìnlẹ̀ Ọlọ́run bí?

8 Ó ga ju àwọn ọ̀run lọ; kí ni ìwọ le è ṣe?

9 Ìwọ̀n rẹ̀ gùn ju ayé lọ,

10 “Bí òun bá rékọjá, tí ó sì sé ọnà

11 Òun sá à mọ ẹlẹ́tàn ènìyàn;

12 Ṣùgbọ́n òmùgọ̀ ènìyàn ki yóò di ọlọ́gbọ́n

13 “Bí ìwọ bá fi ọkàn rẹ fún un,

14 bí ìwọ bá gbé ẹ̀ṣẹ̀ tí ń bẹ ní ọwọ́ rẹ jù sọnù

15 nígbà náà ni ìwọ ó gbé ojú rẹ sókè láìní àbàwọ́n,

16 Nítorí pé ìwọ ó gbàgbé ìṣòro rẹ;

17 Ọjọ́ ayé rẹ yóò sì mọ́lẹ̀ ju ọ̀sán gangan lọ,

18 Ìwọ ó sì wà láìléwu, nítorí pé ìrètí wà;

19 Ìwọ ó sì dùbúlẹ̀ pẹ̀lú, kì yóò sì sí ẹni tí yóò dẹ́rùbà ọ́,

20 Ṣùgbọ́n ojú ìkà ènìyàn yóò mófo;

Ler em outra tradução

Comparar lado a lado

Estude este capítulo no WhatsApp

Peça à IA da Bíblia Fala para explicar Jó 11, comparar traduções ou montar um estudo — tudo direto pelo WhatsApp.