Salmos 5

Biblica® ní oore ọ̀fẹ́ láti lo Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde-Òní (YOR)

1 Fi etí sí ọ̀rọ̀ mi, Olúwa,

2 Fi etí sílẹ̀ sí igbe mi fún ìrànlọ́wọ́,

3 Ní òwúrọ̀, Olúwa, ìwọ yóò gbọ́ ohùn mi;

4 Nítorí ìwọ kì í ṣe Ọlọ́run tí ó ní inú dídùn sí búburú;

5 Àwọn agbéraga kò le è dúró

6 ìwọ yóò pa àwọn tí ń ṣe èké run.

7 Ṣùgbọ́n èmi, nípa títóbi àánú rẹ̀,

8 Tọ́ mi, Olúwa, nínú òdodo rẹ,

9 Kò sí ọ̀rọ̀ kan ní ẹnu wọn tí a lè gbàgbọ́;

10 Dá wọn lẹ́bi Ọlọ́run!

11 Ṣùgbọ́n, jẹ́ kí gbogbo àwọn tí ó sádi ọ́ kí ó yọ̀;

12 Dájúdájú, Olúwa, ìwọ bùkún olódodo;

Ler em outra tradução

Comparar lado a lado

Estude este capítulo no WhatsApp

Peça à IA da Bíblia Fala para explicar Salmos 5, comparar traduções ou montar um estudo — tudo direto pelo WhatsApp.