Salmos 4

Biblica® ní oore ọ̀fẹ́ láti lo Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde-Òní (YOR)

1 Dá mi lóhùn nígbà tí mo bá pè ọ́,

2 Báwo ni yóò ṣe pẹ́ tó, ẹ̀yin ọmọ ènìyàn, tí ẹ ó ṣe sọ ògo mi di ìtìjú?

3 Ṣùgbọ́n kí ẹ mọ̀ pé, Olúwa ti ya ẹni olódodo sọ́tọ̀ fún ara rẹ̀;

4 Ẹ bínú ẹ má ṣe ṣẹ̀,

5 Ẹ rú ẹbọ òdodo

6 Ọ̀pọ̀lọpọ̀ ló ń béèrè pé, “Ta ni yóò ṣe rere fún wa?”

7 Ìwọ ti fi ayọ̀ púpọ̀ kún ọkàn mi

8 Èmi yóò dùbúlẹ̀, èmi ó sì sùn ní àlàáfíà,

Ler em outra tradução

Comparar lado a lado

Estude este capítulo no WhatsApp

Peça à IA da Bíblia Fala para explicar Salmos 4, comparar traduções ou montar um estudo — tudo direto pelo WhatsApp.