Números 26

Biblica® ní oore ọ̀fẹ́ láti lo Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde-Òní (YOR) vs BKJ

Sair da comparação
1 Lẹ́yìn àjàkálẹ̀-ààrùn Olúwa sọ fún Mose àti Eleasari ọmọ Aaroni, àlùfáà pé,
1 E depois daquela praga, o SENHOR falou a Moisés e a Eleazar, filho de Arão, o sacerdote, dizendo:
2 “Ka iye gbogbo àwọn ọmọ Israẹli gẹ́gẹ́ bí ìdílé wọ́n; láti ẹni ogun ọdún àti jù bẹ́ẹ̀ lọ tí ó lè jà lójú ogun ní Israẹli.”
2 Tomai a soma de toda a congregação dos filhos de Israel, com idade igual ou superior a vinte anos, segundo as casas de seus pais; todos os que são capacitados para irem à guerra.
3 Lórí pẹ̀tẹ́lẹ̀ ti Moabu pẹ̀lú Jordani tí ó kọjá Jeriko, Mose àti Eleasari àlùfáà sọ̀rọ̀ pẹ̀lú wọn ó wí pé,
3 E Moisés e Eleazar, o sacerdote, falaram com eles, nas planícies de Moabe, junto ao Jordão, perto de Jericó, e disseram:
4 “Ka iye àwọn ọkùnrin tí ó jẹ́ ọmọ-ogun ọdún tàbí jù bẹ́ẹ̀ lọ, gẹ́gẹ́ bí Olúwa ti pàṣẹ fún Mose.”
4 Tomai a soma do povo com idade igual ou superior a vinte anos, como o SENHOR ordenara a Moisés e aos filhos de Israel, que saíram da terra do Egito.
5 Àwọn ọmọ Reubeni, àkọ́bí ọmọkùnrin Israẹli,
5 Rúben, o primogênito de Israel; os filhos de Rúben: Enoque, do qual veio a família dos enoquitas; de Palu, a família dos paluítas;
6 ti Hesroni, ìdílé àwọn ọmọ Hesroni;
6 de Hezrom, a família dos hezronitas; de Carmi, a família dos carmitas.
7 Wọ̀nyí ni ìdílé àwọn ọmọ Reubeni; àwọn tí a sì kà nínú wọn jẹ́ ẹgbàá mọ́kànlélógún ó lé lẹ́gbẹ̀sán ó dín àádọ́rin (43,730).
7 Estas são as famílias dos rubenitas; e os que foram contados deles foram quarenta e três mil e setecentos e trinta.
8 Àwọn ọmọkùnrin Pallu ni Eliabu,
8 E o filho de Palu: Eliabe.
9 àwọn ọmọkùnrin Elifelehu ni Nemueli àti Eliabu, Datani àti Abiramu. Èyí ni Datani àti Abiramu náà tí wọ́n ní òkìkí nínú ìjọ tí ó jẹ́ ọlọ̀tẹ̀ sí Mose àti Aaroni tí ó sì wà lára àwọn ẹgbẹ́ Kora nígbà tí wọ́n bá Olúwa jà.
9 E os filhos de Eliabe: Nemuel, e Datã, e Abirão; Datã e Abirão, foram os famosos da congregação que contenderam contra Moisés e contra Arão na companhia de Corá, quando contenderam contra o SENHOR.
10 Ilẹ̀ sì la ẹnu rẹ̀, ó sì gbé wọn mì pọ̀ pẹ̀lú Kora, nígbà tí ẹgbẹ́ rẹ̀ kú níbi tí iná ti run àwọn àádọ́ta lé nígba (250) ọkùnrin. Tí wọ́n sì di àmì ìkìlọ̀.
10 E a terra abriu a sua boca, e os engoliu juntamente com Corá, quando aquela companhia morreu, quando o fogo consumiu duzentos e cinquenta homens, e eles se tornaram um sinal.
11 Àwọn ọmọ Kora, bí ó ti wù kí ó rí, wọn kò kú.
11 Porém, os filhos de Corá não morreram.
12 Àwọn ọmọ ìran Simeoni bí ìdílé wọn:
12 Os filhos de Simeão, segundo as suas famílias: de Nemuel, a família dos nemuelitas; de Jamim, a família dos jaminitas; de Jaquim, a família dos jaquinitas;
13 ti Sera, ìdílé Sera;
13 de Zerá, a família dos zeraítas; de Saul, a família dos saulitas.
14 Wọ̀nyí ni ìdílé àwọn ọmọ Simeoni, ẹgbẹ̀rún méjìlélógún ó lé igba (22,200) ọkùnrin.
14 Estas são as famílias dos simeonitas, vinte e dois mil e duzentos.
15 Àwọn ọmọ Gadi bí ìdílé wọn:
15 Os filhos de Gade, segundo as suas famílias: de Zefom, a família dos zefonitas; de Hagi, a família dos hagitas; de Suni, a família dos sunitas;
16 ti Osni, ìdílé Osni;
16 de Ozni, a família dos oznitas; de Eri, a família dos eritas;
17 ti Arodi, ìdílé Arodi;
17 de Arodi, a família dos aroditas; de Areli, a família dos arelitas.
18 Wọ̀nyí ni àwọn ọmọ Gadi tí iye wọn sì jẹ́ ọ̀kẹ́ méjì ó lé lẹ̀ẹ́dẹ́gbẹ̀ta (40,500).
18 Estas são as famílias dos filhos de Gade, segundo os que foram contados, quarenta mil e quinhentos.
19 Àwọn ọmọ Juda ni Eri àti Onani, ṣùgbọ́n Eri àti Onani kú ní ilẹ̀ Kenaani.
19 Os filhos de Judá: Er e Onã; e Er e Onã morreram na terra de Canaã.
20 Àti àwọn ọmọ Juda gẹ́gẹ́ bí ìdílé wọn:
20 E os filhos de Judá foram, segundo as suas famílias: de Selá, a família dos selaítas; de Perez, a família dos perezitas; de Zerá, a família dos zeraítas.
21 Àwọn ọmọ Peresi:
21 E os filhos de Perez foram: de Hezrom, a família dos hezronitas; de Hamul, a família dos hamulitas.
22 Wọ̀nyí ni ìdílé Juda; gẹ́gẹ́ bí àwọn tí a kà nínú wọn tí iye wọn sì jẹ́ ẹgbàá méjìdínlógójì ó lé lẹ̀ẹ́dẹ́gbẹ̀ta (76,500).
22 Estas são as famílias de Judá, segundo os que foram deles contados, setenta e seis mil e quinhentos.
23 Àwọn ọmọ Isakari gẹ́gẹ́ bí ìdílé wọn:
23 Os filhos de Issacar, segundo as suas famílias, foram: de Tola, a família dos tolaítas; de Puva, a família dos puvitas;
24 ti Jaṣubu, ìdílé Jaṣubu;
24 de Jasube, a família dos jasubitas; de Sinrom, a família dos sinronitas.
25 Wọ̀nyí ni ìdílé Isakari gẹ́gẹ́ bí àwọn tí a kà nínú wọn tí iye wọn sì jẹ́ ẹgbàá méjìlélọ́gbọ̀n ó lé ọ̀ọ́dúnrún (64,300).
25 Estas são as famílias de Issacar, segundo os que foram contados, sessenta e quatro mil e trezentos.
26 Àwọn ọmọ Sebuluni gẹ́gẹ́ bí ìdílé wọn:
26 Os filhos de Zebulom, segundo as suas famílias, foram: de Serede, a família dos sereditas; de Elom, a família dos elonitas; de Jaleel, a família dos jaleelitas.
27 Wọ̀nyí ni ìdílé àwọn ọmọ Sebuluni gẹ́gẹ́ bí àwọn tí a kà nínú wọn tí iye wọn sì jẹ́ ọ̀kẹ́ mẹ́ta ó lé lẹ̀ẹ́dẹ́gbẹ̀ta (60,500).
27 Estas são as famílias dos zebulonitas, segundo os que foram contados, sessenta mil e quinhentos.
28 Àwọn ọmọ Josẹfu gẹ́gẹ́ bí ìdílé wọn; Manase àti Efraimu.
28 Os filhos de José, segundo as suas famílias, foram Manassés e Efraim.
29 Àwọn ọmọ Manase:
29 Os filhos de Manassés foram: de Maquir, a família dos maquiritas; e Maquir gerou a Gileade; de Gileade, a família dos gileaditas.
30 Wọ̀nyí ni àwọn ọmọ Gileadi:
30 Estes são os filhos de Gileade: de Jezer, a família dos jezeritas; de Heleque, a família dos helequitas;
31 àti ti Asrieli, ìdílé Asrieli;
31 e de Asriel, a família dos asrielitas; e de Siquém, a família dos siquemitas;
32 àti Ṣemida, ìdílé àwọn ọmọ Ṣemida;
32 e de Semida, a família dos semidaítas; e de Héfer, a família dos heferitas.
33 (Selofehadi ọmọ Heferi kò sì ni ọmọkùnrin, bí kò ṣe ọmọbìnrin; orúkọ àwọn ọmọbìnrin ni Mahila, Noa, àti Hogla, Milka àti Tirsa).
33 E Zelofeade, filho de Héfer, não tinha filhos, mas filhas; e os nomes das filhas de Zelofeade foram: Macla, Noa, Hogla, Milca e Tirza.
34 Wọ̀nyí ni ìdílé Manase tí iye wọn sì jẹ́ ẹgbàá mẹ́rìndínlọ́gbọ̀n ó lé lẹ̀ẹ́dẹ́gbẹ̀rin (52,700).
34 Estas são as famílias de Manassés; e os que foram contados, eram cinquenta e dois mil e setecentos.
35 Wọ̀nyí ni àwọn ọmọ Efraimu gẹ́gẹ́ bí ìdílé wọn:
35 Estes são os filhos de Efraim, segundo as suas famílias: de Sutela, a família dos sutelaítas; de Bequer, a família dos bequeritas; de Taã, a família dos taanitas.
36 Wọ̀nyí ni àwọn ọmọ Ṣutelahi:
36 E estes são os filhos de Sutela: de Erã, a família dos eranitas.
37 Wọ̀nyí ni ìdílé àwọn ọmọ Efraimu, àwọn tí a kà nínú wọn sì jẹ́ ẹgbàá mẹ́rìndínlógún ó lé lẹ̀ẹ́dẹ́gbẹ̀ta (32,500).
37 Estas são as famílias dos filhos de Efraim, segundo os que foram contados, trinta e dois mil e quinhentos; estes são os filhos de José, segundo as suas famílias.
38 Àwọn ọmọ Benjamini gẹ́gẹ́ bí ìdílé wọn nìyìí:
38 Os filhos de Benjamim, segundo as suas famílias: de Belá, a família dos belaítas; de Asbel, a família dos asbelitas; de Airão, a família dos airamitas;
39 ti Ṣufamu, ìdílé àwọn ọmọ Ṣufamu;
39 de Sufã, a família dos sufamitas; de Hufã, a família dos hufamitas.
40 Àwọn ọmọ Bela ní ipasẹ̀ Ardi àti Naamani nìyìí:
40 E os filhos de Belá foram Arde e Naamã; de Arde, a família dos arditas; de Naamã, a família dos naamanitas.
41 Wọ̀nyí ni àwọn ọmọ Benjamini; gẹ́gẹ́ bí ìdílé wọn; àti àwọn tí a kà nínú wọn jẹ́ ẹgbàá méjìlélógún ó lé ẹgbẹ̀jọ (45,600).
41 Estes são os filhos de Benjamim, segundo as suas famílias; e os que foram contados, eram quarenta e cinco mil e seiscentos.
42 Wọ̀nyí ni àwọn ọmọ Dani gẹ́gẹ́ bí ìdílé wọn:
42 Estes são os filhos de Dã, segundo as suas famílias: de Suão, a família dos suamitas; estas são as famílias de Dã, segundo as suas famílias.
43 Gbogbo ìdílé àwọn ọmọ Ṣuhamu, gẹ́gẹ́ bí àwọn tí a kà nínú wọn jẹ́ ẹgbàá méjìlélọ́gbọ̀n ó lé irinwó (64,400).
43 Todas as famílias dos suamitas, segundo os que foram contados, eram sessenta e quatro mil e quatrocentos.
44 Ti àwọn ọmọ Aṣeri gẹ́gẹ́ bí ìdílé wọn:
44 Os filhos de Aser, segundo as suas famílias, foram: de Imna, a família dos imnaítas; de Isvi, a família dos isvitas; de Berias, a família dos beriaítas.
45 Ti àwọn ọmọ Beriah:
45 Os filhos de Berias foram: de Héber, a família dos heberitas; de Malquiel, a família dos malquielitas.
46 (Orúkọ ọmọ Aṣeri obìnrin nì jẹ́ Sera.)
46 E o nome da filha de Aser foi Sera.
47 Wọ̀nyí ni ìdílé àwọn ọmọ Aṣeri gẹ́gẹ́ bí àwọn tí a kà nínú wọn jẹ́ ẹgbàá mẹ́rìndínlọ́gbọ̀n ó lé egbèje (53,400).
47 Estas são as famílias dos filhos de Aser, segundo os que foram contados, cinquenta e três mil e quatrocentos.
48 Ti àwọn ọmọ Naftali gẹ́gẹ́ bí ìdílé wọn:
48 Os filhos de Naftali, segundo as suas famílias; de Jazeel, a família dos jazeelitas; de Guni, a família dos gunitas;
49 ti Jeseri, ìdílé àwọn ọmọ Jeṣeri;
49 de Jezer, a família dos jezeritas; de Silém, a família dos silemitas.
50 Wọ̀nyí ni ìdílé ti Naftali gẹ́gẹ́ bí ìdílé wọn, àwọn tí a kà nínú wọn jẹ́ ẹgbàá méjìlélógún ó lé egbèje (45,400).
50 Estas são as famílias de Naftali, segundo as suas famílias; e os que foram contados, eram quarenta e cinco mil e quatrocentos.
51 Àpapọ̀ iye tí a kà nínú àwọn ọmọ Israẹli jẹ́ ọgbọ̀n ọ̀kẹ́ ó lé ẹgbẹ̀sán dín làádọ́rin (601,730).
51 Estes são os contados dos filhos de Israel, seiscentos e um mil e setecentos e trinta.
52 Olúwa sọ fún Mose pé,
52 E o SENHOR falou a Moisés, dizendo:
53 “Ilẹ̀ náà gbọdọ̀ jẹ́ pínpín fún wọn gẹ́gẹ́ bí ogún wọn gẹ́gẹ́ bí iye orúkọ wọn.
53 Entre estes a terra será dividida em herança, segundo o número dos nomes.
54 Fún àwọn ọ̀pọ̀ ni kí ìwọ ó fún ní ogún ìlú púpọ̀ àti fún àwọn tí ó kéré ni kí ìwọ ó fi kékeré fún, ẹnìkọ̀ọ̀kan gbọdọ̀ gba ogún ìbí tirẹ̀ gẹ́gẹ́ bí ènìyàn tí a kọ.
54 Para muitos darás uma herança maior; e para poucos darás uma herança menor; a cada um se dará a sua herança, segundo os que foram contados.
55 Rí dájú pé ilẹ̀ yìí gbọdọ̀ jẹ́ fífi ìbò pín gẹ́gẹ́ bí wọn sì ti pọ̀ tó. Gẹ́gẹ́ bí orúkọ ẹ̀yà àwọn baba wọn ni kí wọn kí ó ni í.
55 Porém, a terra será dividida por sorte; segundo os nomes das tribos de seus pais, assim a herdarão.
56 Olúkúlùkù ogún ìní ni a gbọdọ̀ fi ìbò pín gẹ́gẹ́ bí wọ́n ti pọ̀ tó láàrín ńlá àti kékeré.”
56 Segundo a sorte, a herança será dividida entre muitos e poucos.
57 Wọ̀nyí ni àwọn ọmọ Lefi tí a kà nínú wọn gẹ́gẹ́ bí ìdílé wọn:
57 E estes são os que foram contados de Levi, segundo as suas famílias: de Gérson, a família dos gersonitas; de Coate, a família dos coatitas; de Merari, a família dos meraritas.
58 Wọ̀nyí ni ìdílé àwọn ọmọ Lefi;
58 Estas são as famílias de Levi: a família dos libnitas, a família dos hebronitas, a família dos malitas, a família dos musitas, a família dos coraítas; e Coate gerou a Anrão.
59 orúkọ aya Amramu sì ń jẹ́ Jokebedi, ọmọbìnrin Lefi, tí ìyá rẹ̀ bí fún Lefi ní Ejibiti. Òun sì bí Aaroni, Mose, àti Miriamu arábìnrin wọn fún Amramu.
59 E o nome da esposa de Anrão era Joquebede, filha de Levi, a quem sua mãe gerou de Levi no Egito; e de Anrão ela gerou Arão, e Moisés, e Miriã, sua irmã.
60 Aaroni ni baba Nadabu àti Abihu, Eleasari àti Itamari.
60 E de Arão nasceram Nadabe, Abiú, Eleazar e Itamar.
61 Ṣùgbọ́n Nadabu àti Abihu kú, nígbà tí wọ́n rú ẹbọ níwájú Olúwa nígbà tí wọ́n mú iná àjèjì wá.)
61 E Nadabe e Abiú morreram quando ofereceram fogo estranho perante o SENHOR.
62 Gbogbo àwọn ọmọkùnrin Lefi láti oṣù kan àti ju bẹ́ẹ̀ lọ ẹgbẹ̀rún méjìlélógún ó lé lẹ́gbẹ̀rún (23,000). Wọn kò ka wọ́n mọ́ àwọn ọmọ Israẹli tókù nítorí tí wọ́n kò gba ogún ìní lára wọn.
62 E os que foram contados somaram vinte e três mil, todos os homens com idade superior a um mês, porque não foram contados entre os filhos de Israel, porque não lhes foi dada herança entre os filhos de Israel.
63 Àwọn wọ̀nyí ni Mose àti Eleasari àlùfáà kà nígbà tí wọ́n ka àwọn ọmọ Israẹli ní pẹ̀tẹ́lẹ̀ Moabu lẹ́bàá odò Jordani létí Jeriko.
63 Estes são os que foram contados por Moisés e Eleazar, o sacerdote, que contaram os filhos de Israel nas planícies de Moabe, junto ao Jordão, perto de Jericó.
64 Kò sí ẹnìkan nínú àwọn tí Mose àti Aaroni àlùfáà kà nígbà tí wọ́n ka àwọn ọmọ Israẹli ní aginjù Sinai.
64 Mas entre estes não havia nenhum dos que foram contados por Moisés e Arão, o sacerdote, quando contaram aos filhos de Israel no deserto do Sinai.
65 Nítorí Olúwa ti sọ fún àwọn ọmọ Israẹli pé kíkú ni wọn yóò kú sí aginjù, kò sì sí ẹnìkankan nínú wọn tí kò kú àfi Kalebu ọmọ Jefunne, àti Joṣua ọmọ Nuni.
65 Porque o SENHOR dissera deles: Eles certamente morrerão no deserto. E não restou nenhum homem daqueles, exceto Calebe, filho de Jefoné, e Josué, filho de Num.

Ler em outra tradução

Comparar com outra

Estude este capítulo no WhatsApp

Peça à IA da Bíblia Fala para explicar Números 26, comparar traduções ou montar um estudo — tudo direto pelo WhatsApp.