Jó 29

Biblica® ní oore ọ̀fẹ́ láti lo Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde-Òní (YOR)

1 Pẹ̀lúpẹ̀lú, Jobu sì tún tẹ̀síwájú nínú ọ̀rọ̀ rẹ̀, ó sì wí pé,

2 “Háà! ìbá ṣe pé èmi wà bí ìgbà oṣù tí ó kọjá,

3 nígbà tí fìtílà rẹ tàn sí mi ní orí,

4 Bí mo ti rí nígbà ọ̀dọ́ mi,

5 nígbà tí Olódùmarè wà pẹ̀lú mi,

6 nígbà tí èmi fi òrí-àmọ́ n wẹ ìṣísẹ̀ mi,

7 “Nígbà tí mo jáde la àárín ìlú lọ sí ẹnu ibodè,

8 nígbà náà ni àwọn ọmọkùnrin rí mi,

9 àwọn ọmọ-aládé dákẹ́ ọ̀rọ̀ sísọ,

10 Àwọn ọlọ́lá dákẹ́,

11 Nígbà tí etí gbọ́, ó sì súre fún mi,

12 nítorí mo gbà tálákà tí n fẹ́ ìrànlọ́wọ́,

13 Ẹni tí ó ń kìlọ̀ súre fún mi,

14 Èmi sì mú òdodo wọ̀ bí aṣọ,

15 Mo ṣe ojú fún afọ́jú mo sì ṣe ẹsẹ̀

16 Mo ṣe baba fún tálákà;

17 Mo sì ká eyín ẹ̀rẹ̀kẹ́ ènìyàn búburú,

18 “Nígbà náà ni mo rò pé, ‘Èmi yóò kú nínú ilé mi,

19 Gbòǹgbò mi yóò ta kan omi,

20 Ògo mi yóò wà ní ọ̀tún ní ọ̀dọ̀ mi,

21 “Èmi ni ènìyàn ń dẹtí sílẹ̀ sí,

22 Lẹ́yìn ọ̀rọ̀ mi, wọn kò tún sọ̀rọ̀ mọ́;

23 Wọn a sì dúró dè mí bí ẹni wí pé wọ́n dúró fún ọ̀wọ́ òjò;

24 Èmi sì rẹ́rìn-ín sí wọn nígbà tí wọn kò bá gbà á gbọ́;

25 Mo la ọ̀nà sílẹ̀ fún wọn, mo sì jókòó bí olóyè wọn.

Ler em outra tradução

Comparar lado a lado

Estude este capítulo no WhatsApp

Peça à IA da Bíblia Fala para explicar Jó 29, comparar traduções ou montar um estudo — tudo direto pelo WhatsApp.