Isaías 8
Biblica® ní oore ọ̀fẹ́ láti lo Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde-Òní (YOR) vs NAA
1 Olúwa sọ fún mi pé, mú ìwé ńlá kan, kí o sì fi kálàmù ìkọ̀wé lásán kọ Maha-Ṣalali-Haṣi-Basi.
1 O Senhor me disse: — Pegue uma tabuleta grande e escreva nela de maneira inteligível: Maer-Salal-Hás-Baz.
2 Èmi yóò sì mú Uriah àlùfáà àti Sekariah ọmọ Jeberekiah gẹ́gẹ́ bí ẹlẹ́rìí òtítọ́ wá sí ọ̀dọ̀ mi.
2 Como testemunhas fidedignas, chamei o sacerdote Urias e Zacarias, filho de Jeberequias.
3 Lẹ́yìn náà, mo lọ sí ọ̀dọ̀ wòlíì obìnrin náà, ó sì lóyún, ó sì bí ọmọkùnrin kan. Olúwa sì wí fún mi pé, “Pe orúkọ rẹ̀ ní Maha-Ṣalali-Haṣi-Basi.
3 Então tive relações com a profetisa, ela ficou grávida e deu à luz um filho. E o Senhor me disse: — Ponha nele o nome de Maer-Salal-Hás-Baz.
4 Kí ọmọkùnrin náà tó mọ bí a ti ń sọ pé, ‘Baba mi’ tàbí ‘Ìyá mi,’ gbogbo ọrọ̀ Damasku àti ìkógun ti Samaria ni ọba àwọn Asiria yóò ti kó lọ.”
4 Porque, antes que o menino saiba dizer “papai” ou “mamãe”, as riquezas de Damasco e os despojos de Samaria serão levados ao rei da Assíria.
5 Olúwa sì tún sọ fún mi pé,
5 O Senhor falou comigo de novo, dizendo:
6 “Nítorí pé àwọn ènìyàn yìí ti kọ
6 — Visto que este povo desprezou as águas de Siloé, que correm brandamente, e está se derretendo de medo diante de Rezim e do filho de Remalias,
7 ǹjẹ́ nítorí náà kíyèsi i, Olúwa ń fa omi odò tí ó le,
7 eis que o Senhor fará vir sobre eles as águas do Eufrates, fortes e impetuosas, isto é, o rei da Assíria com toda a sua glória. Essas águas encherão o leito dos rios e transbordarão por todas as suas ribanceiras.
8 yóò sì gbá àárín Juda kọjá,
8 Penetrarão em Judá, inundando-o, e, passando por ele, chegarão até o pescoço. As suas asas estendidas cobrirão a largura de toda a sua terra, ó Emanuel.
9 Ké ariwo ogun, ẹ̀yin orílẹ̀-èdè, kí a sì fọ́ ọ yín túútúú,
9 Fiquem furiosos, ó povos, e serão despedaçados! Deem ouvidos, todos os países distantes! Preparem-se para a batalha e vocês serão despedaçados! Sim, preparem-se para a batalha e vocês serão despedaçados!
10 Ẹ gbìmọ̀ pọ̀, yóò sì di asán,
10 Elaborem projetos, mas eles serão frustrados; deem ordens, mas elas não serão cumpridas, porque Deus está conosco.
11 Olúwa bá mi sọ̀rọ̀ pẹ̀lú ọwọ́ agbára rẹ̀ o ìkìlọ̀ fún mi pé, èmi kò gbọdọ̀ tẹ̀lé ọ̀nà àwọn ènìyàn wọ̀nyí. Ó wí pé,
11 Porque assim o Senhor me disse, tendo forte a mão sobre mim, e me advertiu que eu não andasse pelo caminho deste povo. Ele disse:
12 “Má ṣe pe èyí ní ọ̀tẹ̀
12 — Não chamem conspiração a tudo o que este povo chama conspiração. Não temam aquilo que o povo teme, nem fiquem apavorados.
13 Olúwa àwọn ọmọ-ogun ni Ẹni tí ìwọ yóò kà sí mímọ́,
13 Ao Senhor dos Exércitos, a ele vocês devem santificar. É a ele que devem temer; é dele que devem ter pavor.
14 Òun yóò sì jẹ́ ibi mímọ́
14 Ele será um santuário para vocês, mas será pedra de tropeço e rocha de ofensa às duas casas de Israel; será laço e armadilha aos moradores de Jerusalém.
15 Ọ̀pọ̀lọpọ̀ wọn ni yóò kọsẹ̀,
15 Muitos deles tropeçarão, cairão e serão despedaçados; serão enlaçados e presos.
16 Di májẹ̀mú náà
16 — Guarde bem o testemunho e sele a lei entre os meus discípulos.
17 Èmi yóò dúró de Olúwa,
17 Esperarei no Senhor , que esconde o seu rosto da casa de Jacó; a ele aguardarei.
18 Èmi nìyí, àti àwọn ọmọ tí Olúwa fi fún mi. Àwa jẹ́ àmì àti àpẹẹrẹ ní Israẹli láti ọ̀dọ̀ Olúwa àwọn ọmọ-ogun, ẹni tí ó ń gbé ní òkè Sioni.
18 — Eis-me aqui, com os filhos que o Senhor me deu, como sinais e maravilhas em Israel da parte do Senhor dos Exércitos, que habita no monte Sião.
19 Nígbà tí àwọn ènìyàn bá sọ fún un yín pé kí ẹ lọ sí ọ̀dọ̀ àwọn abókùúsọ̀rọ̀ àti àwọn oṣó, ti máa ń kún tí wọ́n sì ń sọ̀rọ̀ kẹ́lẹ́kẹ́lẹ́, ǹjẹ́ kò ha yẹ kí àwọn ènìyàn béèrè lọ́wọ́ Ọlọ́run wọn bí? Èéṣe tí ẹ fi ń bá òkú sọ̀rọ̀ ní orúkọ alààyè?
19 — Quando disserem a vocês: “Consultem os médiuns e os adivinhos, que sussurram e murmuram”, será que um povo não deveria consultar o seu Deus? A favor dos vivos se consultarão os mortos?
20 Sí òfin àti májẹ̀mú! Bí wọn kò bá sọ̀rọ̀ gẹ́gẹ́ bí ọ̀rọ̀ yìí, wọn kò rí ìmọ́lẹ̀ ọjọ́.
20 À lei e ao testemunho! Se eles não falarem segundo esta palavra, jamais verão a luz do alvorecer.
21 Nínú ìnilára àti ebi, ni wọn yóò máa kọjá lọ láàrín ilẹ̀ náà, nígbà tí ebi bá pa wọ́n, nígbà yìí ni wọn yóò máa kanra, wọn yóò wòkè, wọn yóò sì fi ọba àti Ọlọ́run wọn ré.
21 Passarão pela terra duramente oprimidos e famintos. E, quando tiverem fome, enfurecendo-se, amaldiçoarão o seu rei e o seu Deus, olhando para cima.
22 Nígbà náà ni wọn yóò sì wolẹ̀, wọn yóò sì rí ìpọ́njú, òkùnkùn àti ìpòrúru tí ó ba ni lẹ́rù, a ó sì sọ wọ́n sínú òkùnkùn biribiri.
22 Olharão para a terra, e eis aí angústia, escuridão e sombras de ansiedade; e serão lançados em densas trevas.
Atalhos do teclado
- Capítulo anterior←
- Próximo capítulo→
- Versículo anteriork
- Próximo versículoj
- Limpar seleçãoEsc
- Esta ajuda?
Estude este capítulo no WhatsApp
Peça à IA da Bíblia Fala para explicar Isaías 8, comparar traduções ou montar um estudo — tudo direto pelo WhatsApp.