Isaías 8

Biblica® ní oore ọ̀fẹ́ láti lo Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde-Òní (YOR) vs BKJ

Sair da comparação
1 Olúwa sọ fún mi pé, mú ìwé ńlá kan, kí o sì fi kálàmù ìkọ̀wé lásán kọ Maha-Ṣalali-Haṣi-Basi.
1 Além disso, o SENHOR me disse: Pega um grande rolo, e escreve nele com a pena de homem, a respeito de Maher-shalal-hash-baz.
2 Èmi yóò sì mú Uriah àlùfáà àti Sekariah ọmọ Jeberekiah gẹ́gẹ́ bí ẹlẹ́rìí òtítọ́ wá sí ọ̀dọ̀ mi.
2 E eu trouxe até mim fiéis testemunhas para registrar: Urias, o sacerdote, e Zacarias, o filho de Jeberequias.
3 Lẹ́yìn náà, mo lọ sí ọ̀dọ̀ wòlíì obìnrin náà, ó sì lóyún, ó sì bí ọmọkùnrin kan. Olúwa sì wí fún mi pé, “Pe orúkọ rẹ̀ ní Maha-Ṣalali-Haṣi-Basi.
3 E eu me cheguei à profetisa, e ela concebeu, e deu à luz um filho. Então disse o SENHOR a mim: Dá-lhe o nome de Maher-shalal-hash-baz.
4 Kí ọmọkùnrin náà tó mọ bí a ti ń sọ pé, ‘Baba mi’ tàbí ‘Ìyá mi,’ gbogbo ọrọ̀ Damasku àti ìkógun ti Samaria ni ọba àwọn Asiria yóò ti kó lọ.”
4 Porque, antes da criança ter conhecimento para clamar: Meu pai, e minha mãe, os ricos de Damasco e o despojo de Samaria serão tomados perante o rei da Assíria.
5 Olúwa sì tún sọ fún mi pé,
5 O SENHOR também me falou novamente, dizendo:
6 “Nítorí pé àwọn ènìyàn yìí ti kọ
6 Visto que este povo rejeita as águas de Siloé, que correm suavemente, e se alegram em Rezim e no filho de Remalias.
7 ǹjẹ́ nítorí náà kíyèsi i, Olúwa ń fa omi odò tí ó le,
7 Agora, portanto, observai, o Senhor traz sobre eles as águas do rio, fortes e muitas, precisamente, o rei da Assíria e toda a sua glória. E ele surgirá sobre todos os seus leitos de rio e examinará todas as suas margens.
8 yóò sì gbá àárín Juda kọjá,
8 E ele se estenderá por toda Judá. Ele transbordará e será bem-sucedido. Ele alcançará até o pescoço. E o distender das asas dele preencherá a largura de tua terra, ó Emanuel.
9 Ké ariwo ogun, ẹ̀yin orílẹ̀-èdè, kí a sì fọ́ ọ yín túútúú,
9 Associai-vos, ó vós, povo, e vós sereis feitos em pedaços; e dai ouvidos, todos vós de países distantes; cingi-vos, e vós sereis feitos em pedaços; cingi-vos e vós sereis feitos em pedaços.
10 Ẹ gbìmọ̀ pọ̀, yóò sì di asán,
10 Tomai conselho juntos e isto tornar-se-á em nada. Falai a palavra, e ela não prevalecerá, porque Deus está conosco.
11 Olúwa bá mi sọ̀rọ̀ pẹ̀lú ọwọ́ agbára rẹ̀ o ìkìlọ̀ fún mi pé, èmi kò gbọdọ̀ tẹ̀lé ọ̀nà àwọn ènìyàn wọ̀nyí. Ó wí pé,
11 Porque o SENHOR falou desta forma a mim, com uma forte mão, e instruiu-me que eu não devo andar no caminho deste povo, dizendo:
12 “Má ṣe pe èyí ní ọ̀tẹ̀
12 Não digais vós, uma conspiração, a todos aqueles para quem este povo dirá, uma conspiração. Nem temais vós o que eles temem, nem tenhais medo.
13 Olúwa àwọn ọmọ-ogun ni Ẹni tí ìwọ yóò kà sí mímọ́,
13 Santificai ao SENHOR dos Exércitos, a ele mesmo, e permiti que Ele seja o vosso temor, e permiti que Ele seja a vossa reverência.
14 Òun yóò sì jẹ́ ibi mímọ́
14 E Ele vos será por santuário; porém será por uma pedra de tropeço e por uma rocha de ofensa para ambas as casas de Israel; por laço e por armadilha para os habitantes de Jerusalém.
15 Ọ̀pọ̀lọpọ̀ wọn ni yóò kọsẹ̀,
15 E muitos dentre eles irão tropeçar e cair; e serão quebrados, e serão capturados, e serão tomados.
16 Di májẹ̀mú náà
16 Atai o testemunho, selai a lei entre meus discípulos.
17 Èmi yóò dúró de Olúwa,
17 E eu esperarei no SENHOR, que esconde a sua face da casa de Jacó, e eu o buscarei.
18 Èmi nìyí, àti àwọn ọmọ tí Olúwa fi fún mi. Àwa jẹ́ àmì àti àpẹẹrẹ ní Israẹli láti ọ̀dọ̀ Olúwa àwọn ọmọ-ogun, ẹni tí ó ń gbé ní òkè Sioni.
18 Eis que eu, e os filhos que o SENHOR tem me dado somos para sinais e maravilhas em Israel, provenientes do SENHOR dos Exércitos, que habita no monte Sião.
19 Nígbà tí àwọn ènìyàn bá sọ fún un yín pé kí ẹ lọ sí ọ̀dọ̀ àwọn abókùúsọ̀rọ̀ àti àwọn oṣó, ti máa ń kún tí wọ́n sì ń sọ̀rọ̀ kẹ́lẹ́kẹ́lẹ́, ǹjẹ́ kò ha yẹ kí àwọn ènìyàn béèrè lọ́wọ́ Ọlọ́run wọn bí? Èéṣe tí ẹ fi ń bá òkú sọ̀rọ̀ ní orúkọ alààyè?
19 E quando eles vos disserem: Buscai aqueles que possuem espíritos familiares, e por magos que piam e que murmuram. Não deveria um povo buscar o seu Deus? A favor do vivo consultará ao morto?
20 Sí òfin àti májẹ̀mú! Bí wọn kò bá sọ̀rọ̀ gẹ́gẹ́ bí ọ̀rọ̀ yìí, wọn kò rí ìmọ́lẹ̀ ọjọ́.
20 À lei e ao testemunho: se eles não falarem de acordo com esta palavra, é porque nenhuma luz existe neles.
21 Nínú ìnilára àti ebi, ni wọn yóò máa kọjá lọ láàrín ilẹ̀ náà, nígbà tí ebi bá pa wọ́n, nígbà yìí ni wọn yóò máa kanra, wọn yóò wòkè, wọn yóò sì fi ọba àti Ọlọ́run wọn ré.
21 E eles irão atravessá-la, praticamente sem ajuda e famintos. E acontecerá que, quando eles estiverem famintos, eles irão se inquietar e amaldiçoar seu rei e seu Deus, e olharão para cima.
22 Nígbà náà ni wọn yóò sì wolẹ̀, wọn yóò sì rí ìpọ́njú, òkùnkùn àti ìpòrúru tí ó ba ni lẹ́rù, a ó sì sọ wọ́n sínú òkùnkùn biribiri.
22 E eles olharão para a terra e observarão dificuldade e escuridão, desesperança de angústia e eles serão lançados à escuridão.

Ler em outra tradução

Comparar com outra

Estude este capítulo no WhatsApp

Peça à IA da Bíblia Fala para explicar Isaías 8, comparar traduções ou montar um estudo — tudo direto pelo WhatsApp.