Ezequiel 29
Biblica® ní oore ọ̀fẹ́ láti lo Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde-Òní (YOR) vs NTLH
1 Ní ọjọ́ kejìlá, oṣù kẹwàá, ọdún kẹwàá, ọ̀rọ̀ Olúwa tọ̀ mí wá wí pé:
1 No décimo ano do nosso cativeiro , no dia doze do décimo mês , o Senhor me disse o seguinte:
2 “Ọmọ ènìyàn, kọjú sí Farao ọba Ejibiti kí ó sì sọ àsọtẹ́lẹ̀ sí i àti sí gbogbo Ejibiti.
2 — Homem mortal , fale contra o rei do Egito . Diga-lhe como ele e toda a terra do Egito serão castigados.
3 Sọ̀rọ̀, kí ó sì wí pé, ‘Báyìí ní Olúwa Olódùmarè wí:
3 Diga que o Senhor Deus está dizendo isto ao rei do Egito: “Eu estou contra você, crocodilo monstruoso deitado no rio. Você diz que o rio Nilo é seu, que você mesmo o fez.
4 Ṣùgbọ́n èmi yóò fi ìwọ̀ mú ẹnu rẹ
4 Mas eu porei um gancho no seu focinho e farei com que os peixes do seu rio fiquem agarrados em você. Então eu o puxarei para fora do rio Nilo, com todos os peixes agarrados em você.
5 Èmi yóò sọ ọ́ nù sí aginjù
5 Eu o jogarei no deserto e todos aqueles peixes também. O seu corpo ficará largado no chão e não será sepultado. Eu o darei às aves e aos animais selvagens como alimento.
6 Nígbà náà gbogbo àwọn olùgbé ni Ejibiti yóò mọ pé, Èmi ni Olúwa.
6 Assim todo o povo do Egito ficará sabendo que eu sou o Senhor .” O — Os israelitas se apoiaram em você, mas você foi um bastão fraco.
7 Nígbà tí wọn fi ọwọ́ agbára wọn dì ọ́ mú. Ìwọ fọ́, ìwọ sì ya gbogbo èjìká wọn; nígbà tí wọn fi ara tì ọ́, ìwọ sẹ́, ìwọ sì mú gbogbo ẹ̀gbẹ́ wọn gbọ̀n.
7 Quando eles se apoiaram, você quebrou, machucou o ombro deles e fez com que torcessem as costas.
8 “ ‘Nítorí náà, èyí ní Olúwa Olódùmarè wí: Kíyèsi, Èmi yóò mú idà kan wá sórí rẹ tí yóò sì gé ènìyàn àti ẹran kúrò nínú rẹ.
8 Por isso, eu, o Senhor Deus, estou lhe dizendo que farei com que homens o ataquem com espadas, e eles matarão a sua gente e os seus animais.
9 Ilẹ̀ Ejibiti yóò di aginjù àti ahoro, nígbà náà ní wọn yóò sì mọ̀ wí pé èmi ní Olúwa.
9 O Egito vai virar um deserto vazio. Aí você ficará sabendo que eu sou o Senhor . — Você disse que o rio Nilo é seu e que foi você que o fez,
10 nítorí náà, mo lòdì sí ọ àti sí àwọn odò rẹ, èmi yóò sì mú kí ilẹ̀ Ejibiti di píparun àti ahoro, pátápátá, láti Migdoli lọ dé Siene, dé ààlà ilẹ̀ Kuṣi.
10 e por isso eu estou contra você e contra o seu rio Nilo. Farei com que todo o Egito vire um deserto vazio, desde a cidade de Migdol, no Norte, até a cidade de Assuã, no Sul, e até a fronteira da Etiópia.
11 Kò sí ẹsẹ̀ ènìyàn tàbí tí ẹranko tí yóò gba ibẹ̀ kọjá; ẹni kankan kò ní gbé ibẹ̀ fún ogójì ọdún.
11 Nenhuma pessoa ou animal passará pelas suas terras. Durante quarenta anos, o Egito ficará sem moradores.
12 Èmi yóò sọ ilẹ̀ Ejibiti di ọ̀kan ní àárín àwọn ìlú tí ó di ahoro, fún ogójì ọdún, Èmi yóò sì fọ́n àwọn ara Ejibiti ká sáàárín àwọn orílẹ̀-èdè, èmi yóò sì tú wọn ká sáàárín gbogbo ilẹ̀.
12 Farei do Egito o país mais deserto do mundo. Durante quarenta anos, as cidades do Egito ficarão arrasadas, mais arrasadas do que quaisquer outras cidades. Farei com que os egípcios se tornem refugiados. Fugirão para todos os países e viverão no meio de outros povos.
13 “ ‘Ṣùgbọ́n báyìí ní Olúwa Olódùmarè wí: Ní òpin ogójì ọdún, èmi yóò ṣa àwọn ará Ejibiti jọ láti ọ̀dọ̀ àwọn ènìyàn níbi tí a fọ́n wọn ká sí.
13 O Senhor Deus diz: — Depois desses quarenta anos, trarei os egípcios de volta das nações por onde os espalhei.
14 Èmi yóò sì tún mú ìgbèkùn Ejibiti padà bọ̀, èmi yóò sì dá wọn padà sí ilẹ̀ Paturosi, ilẹ̀ àwọn baba ńlá wọn. Wọn yóò wà níbẹ̀ bí ìjọba tí a rẹ̀ sílẹ̀.
14 Eu os deixarei viver no Sul do Egito, a região de onde vieram. Ali eles serão um reino pequeno,
15 Ibẹ̀ yóò jẹ́ ìjọba tí ó rẹlẹ̀ jùlọ nínú àwọn ìjọba, kì yóò sì gbé ara rẹ̀ ga mọ́ sórí àwọn orílẹ̀-èdè: nítorí èmi ni ó dín wọn kù, tiwọn kì yóò fi ṣe olórí àwọn orílẹ̀-èdè yòókù mọ́.
15 o mais fraco de todos, e nunca mais dominarão outras nações. Eu os diminuirei tanto, que não serão capazes de dominá-las.
16 Ejibiti kí yóò sì jẹ orísun ìgbẹ́kẹ̀lé fún ilé Israẹli mọ́ ṣùgbọ́n, yóò jẹ́ ìrántí fún àìṣedéédéé wọn, nígbà tí yóò bá wò wọ́n fún ìrànlọ́wọ́. Nígbà náà, wọn yóò mọ̀ pé èmi ni Olúwa Olódùmarè.’ ”
16 Israel nunca mais dependerá da ajuda deles. O que aconteceu com o Egito fará com que o povo de Israel lembre como estava errado em confiar nos egípcios. Então Israel ficará sabendo que eu sou o Senhor Deus.
17 Ó sì ṣe ní ọjọ́ kìn-ín-ní, oṣù kìn-ín-ní, ọdún kẹtàdínlọ́gbọ̀n, ọ̀rọ̀ Olúwa tọ̀ mí wá wí pé:
17 No ano vigésimo sétimo do nosso cativeiro , no primeiro dia do primeiro mês , o Senhor falou comigo. Ele disse:
18 “Ọmọ ènìyàn, Nebukadnessari ọba Babeli mú kí ogun rẹ sin ìrú ńlá fún Tire. Gbogbo orí pá, àti gbogbo èjìká bó, síbẹ̀, òun àti àwọn ogun rẹ̀, kò rí owó ọ̀yà gbà láti Tire fún wa, fún ìrú ti a ti sìn.
18 — Homem mortal , escute. Nabucodonosor, rei da Babilônia, atacou a cidade de Tiro . Ele obrigou os seus soldados a carregarem tanto peso, que os cabelos deles caíram, e os seus ombros ficaram esfolados. Mas nem o rei nem o seu exército conseguiram nada como pagamento pelos seus esforços.
19 Nítorí náà, báyìí ni Olúwa Olódùmarè wí: Kíyèsi i, Èmi yóò fi Ejibiti fún Nebukadnessari ọba Babeli, òun yóò sì kó ọrọ̀ rẹ̀ lọ. Òun yóò bo ilé, yóò sì ṣe ìkógun ilẹ̀ náà gẹ́gẹ́ bí owó iṣẹ́ tí a san fún ológun rẹ̀.
19 — Agora, eu, o Senhor Deus, digo isto: “Darei a terra do Egito ao rei Nabucodonosor. Ele vai pegar toda a riqueza do Egito e vai levá-la como pagamento para o seu exército.
20 Èmi ti fi Ejibiti fún un gẹ́gẹ́ bí èrè wàhálà rẹ̀ nítorí òun àti àwọn ológun rẹ ṣe é fún mi, ni Olúwa Olódùmarè wí.
20 Eu darei a Nabucodonosor o Egito como pagamento pelos seus serviços, pois o seu exército está trabalhando para mim. Sou eu, o Senhor Deus, quem está falando.”
21 “Ní ọjọ́ náà, èmi yóò mú kí ìwo Israẹli ru jáde, èmi yóò sì fún ọ ní ẹnu ọ̀rọ̀ ní àárín wọn. Nígbà náà ni wọn yóò mọ̀ pé èmi ni Olúwa.”
21 — Quando isso acontecer, farei com que o povo de Israel fique forte. E a você, Ezequiel, vou dar licença para falar onde todos possam ouvi-lo, e assim eles ficarão sabendo que eu sou o Senhor .
Atalhos do teclado
- Capítulo anterior←
- Próximo capítulo→
- Versículo anteriork
- Próximo versículoj
- Limpar seleçãoEsc
- Esta ajuda?
Estude este capítulo no WhatsApp
Peça à IA da Bíblia Fala para explicar Ezequiel 29, comparar traduções ou montar um estudo — tudo direto pelo WhatsApp.