Ezequiel 29
Biblica® ní oore ọ̀fẹ́ láti lo Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde-Òní (YOR) vs BKJ
1 Ní ọjọ́ kejìlá, oṣù kẹwàá, ọdún kẹwàá, ọ̀rọ̀ Olúwa tọ̀ mí wá wí pé:
1 No décimo ano, no décimo mês, no décimo dia do mês, a palavra do SENHOR veio a mim, dizendo:
2 “Ọmọ ènìyàn, kọjú sí Farao ọba Ejibiti kí ó sì sọ àsọtẹ́lẹ̀ sí i àti sí gbogbo Ejibiti.
2 Filho do homem, põe a tua face contra Faraó, rei do Egito, e profetiza contra ele, e contra todo o Egito;
3 Sọ̀rọ̀, kí ó sì wí pé, ‘Báyìí ní Olúwa Olódùmarè wí:
3 fala, e dize: Assim diz o Senhor DEUS: Eis que eu estou contra ti, Faraó, rei do Egito, o grande dragão que está no meio dos teus rios, e que disse: O meu rio é meu, e eu o fiz para mim.
4 Ṣùgbọ́n èmi yóò fi ìwọ̀ mú ẹnu rẹ
4 Mas eu porei anzóis em tuas mandíbulas, e farei com que os peixes dos teus rios grudem nas tuas escamas; e tirar-te-ei do meio dos teus rios, e todos os peixes dos teus rios grudarão nas tuas escamas.
5 Èmi yóò sọ ọ́ nù sí aginjù
5 E te deixarei lançado no deserto, a ti e a todos os peixes dos teus rios; tu cairás sobre os campos abertos; não serás recolhido nem ajuntado; eu te dei por alimento aos animais do campo e às aves do céu.
6 Nígbà náà gbogbo àwọn olùgbé ni Ejibiti yóò mọ pé, Èmi ni Olúwa.
6 E todos os habitantes do Egito saberão que eu sou o SENHOR, porque eles se tornaram um cajado de cana para a casa de Israel.
7 Nígbà tí wọn fi ọwọ́ agbára wọn dì ọ́ mú. Ìwọ fọ́, ìwọ sì ya gbogbo èjìká wọn; nígbà tí wọn fi ara tì ọ́, ìwọ sẹ́, ìwọ sì mú gbogbo ẹ̀gbẹ́ wọn gbọ̀n.
7 Quando eles se apoderaram de ti pela tua mão, tu te quebraste, e lhes rasgaste todo o ombro; e quando se debruçaram sobre ti, te quebraste, e fizeste todos os seus lombos ficar numa posição.
8 “ ‘Nítorí náà, èyí ní Olúwa Olódùmarè wí: Kíyèsi, Èmi yóò mú idà kan wá sórí rẹ tí yóò sì gé ènìyàn àti ẹran kúrò nínú rẹ.
8 Portanto, assim diz o Senhor DEUS: Eis que eu trarei uma espada sobre ti, e cortarei fora de ti homem e animal.
9 Ilẹ̀ Ejibiti yóò di aginjù àti ahoro, nígbà náà ní wọn yóò sì mọ̀ wí pé èmi ní Olúwa.
9 E a terra do Egito será assolada e devastada; e eles saberão que eu sou o SENHOR, porquanto ele disse: O rio é meu, e eu o fiz.
10 nítorí náà, mo lòdì sí ọ àti sí àwọn odò rẹ, èmi yóò sì mú kí ilẹ̀ Ejibiti di píparun àti ahoro, pátápátá, láti Migdoli lọ dé Siene, dé ààlà ilẹ̀ Kuṣi.
10 Eis que, portanto, eu estou contra ti, e contra os teus rios; e tornarei a terra do Egito totalmente devastada e assolada, desde a torre de Sevene até a fronteira da Etiópia.
11 Kò sí ẹsẹ̀ ènìyàn tàbí tí ẹranko tí yóò gba ibẹ̀ kọjá; ẹni kankan kò ní gbé ibẹ̀ fún ogójì ọdún.
11 Nenhum pé de homem passará por ela, nem pé de animal passará por ela, nem será habitada por quarenta anos.
12 Èmi yóò sọ ilẹ̀ Ejibiti di ọ̀kan ní àárín àwọn ìlú tí ó di ahoro, fún ogójì ọdún, Èmi yóò sì fọ́n àwọn ara Ejibiti ká sáàárín àwọn orílẹ̀-èdè, èmi yóò sì tú wọn ká sáàárín gbogbo ilẹ̀.
12 E tornarei a terra do Egito assolada no meio dos países que estão assolados; e as suas cidades entre as cidades que estão devastadas, serão assoladas por quarenta anos; e espalharei os egípcios entre as nações, e os dispersarei pelas nações.
13 “ ‘Ṣùgbọ́n báyìí ní Olúwa Olódùmarè wí: Ní òpin ogójì ọdún, èmi yóò ṣa àwọn ará Ejibiti jọ láti ọ̀dọ̀ àwọn ènìyàn níbi tí a fọ́n wọn ká sí.
13 Porém, assim diz o Senhor DEUS: Ao fim de quarenta anos eu ajuntarei os egípcios dentre as pessoas aonde eles foram espalhados;
14 Èmi yóò sì tún mú ìgbèkùn Ejibiti padà bọ̀, èmi yóò sì dá wọn padà sí ilẹ̀ Paturosi, ilẹ̀ àwọn baba ńlá wọn. Wọn yóò wà níbẹ̀ bí ìjọba tí a rẹ̀ sílẹ̀.
14 e eu trarei novamente o cativeiro do Egito, e os farei voltar à terra de Patros, à terra de sua habitação; e eles serão ali um reino baixo.
15 Ibẹ̀ yóò jẹ́ ìjọba tí ó rẹlẹ̀ jùlọ nínú àwọn ìjọba, kì yóò sì gbé ara rẹ̀ ga mọ́ sórí àwọn orílẹ̀-èdè: nítorí èmi ni ó dín wọn kù, tiwọn kì yóò fi ṣe olórí àwọn orílẹ̀-èdè yòókù mọ́.
15 Será o mais baixo dos reinos, nem mais se exaltará sobre as nações; porque eu os diminuirei, para que eles não governem sobre as nações.
16 Ejibiti kí yóò sì jẹ orísun ìgbẹ́kẹ̀lé fún ilé Israẹli mọ́ ṣùgbọ́n, yóò jẹ́ ìrántí fún àìṣedéédéé wọn, nígbà tí yóò bá wò wọ́n fún ìrànlọ́wọ́. Nígbà náà, wọn yóò mọ̀ pé èmi ni Olúwa Olódùmarè.’ ”
16 E não será mais a confiança da casa de Israel, que lhes traz sua iniquidade à lembrança, quando olharem após eles; mas saberão que eu sou o Senhor DEUS.
17 Ó sì ṣe ní ọjọ́ kìn-ín-ní, oṣù kìn-ín-ní, ọdún kẹtàdínlọ́gbọ̀n, ọ̀rọ̀ Olúwa tọ̀ mí wá wí pé:
17 E aconteceu que, no vigésimo sétimo ano, no primeiro mês, no primeiro dia do mês, a palavra do SENHOR veio a mim, dizendo:
18 “Ọmọ ènìyàn, Nebukadnessari ọba Babeli mú kí ogun rẹ sin ìrú ńlá fún Tire. Gbogbo orí pá, àti gbogbo èjìká bó, síbẹ̀, òun àti àwọn ogun rẹ̀, kò rí owó ọ̀yà gbà láti Tire fún wa, fún ìrú ti a ti sìn.
18 Filho do homem, Nabucodonosor, rei de babilônia, fez com que o seu exército prestasse um grande serviço contra Tiro; toda a cabeça se tornou calva, e todo o ombro foi descascado; ainda assim, não houve paga a ele nem a seu exército por Tiro, pelo serviço que havia prestado contra ela;
19 Nítorí náà, báyìí ni Olúwa Olódùmarè wí: Kíyèsi i, Èmi yóò fi Ejibiti fún Nebukadnessari ọba Babeli, òun yóò sì kó ọrọ̀ rẹ̀ lọ. Òun yóò bo ilé, yóò sì ṣe ìkógun ilẹ̀ náà gẹ́gẹ́ bí owó iṣẹ́ tí a san fún ológun rẹ̀.
19 portanto, assim diz o Senhor DEUS: Eis que eu darei a terra do Egito a Nabucodonosor, rei de babilônia; e ele levará a sua multidão, e tomará o seu despojo, e tomará a sua presa, e esta será a paga por seu exército.
20 Èmi ti fi Ejibiti fún un gẹ́gẹ́ bí èrè wàhálà rẹ̀ nítorí òun àti àwọn ológun rẹ ṣe é fún mi, ni Olúwa Olódùmarè wí.
20 Eu lhe dei a terra do Egito pelo seu trabalho com o qual serviu contra ela, porquanto forjaram por mim, diz o Senhor DEUS.
21 “Ní ọjọ́ náà, èmi yóò mú kí ìwo Israẹli ru jáde, èmi yóò sì fún ọ ní ẹnu ọ̀rọ̀ ní àárín wọn. Nígbà náà ni wọn yóò mọ̀ pé èmi ni Olúwa.”
21 Naquele dia eu farei com que o chifre da casa de Israel brote, e eu te darei a abertura da tua boca no meio deles; e eles saberão que eu sou o SENHOR.
Atalhos do teclado
- Capítulo anterior←
- Próximo capítulo→
- Versículo anteriork
- Próximo versículoj
- Limpar seleçãoEsc
- Esta ajuda?
Estude este capítulo no WhatsApp
Peça à IA da Bíblia Fala para explicar Ezequiel 29, comparar traduções ou montar um estudo — tudo direto pelo WhatsApp.