2 Samuel 10
Biblica® ní oore ọ̀fẹ́ láti lo Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde-Òní (YOR) vs BKJ
1 Ó sì ṣe lẹ́yìn èyí, ọba àwọn ará Ammoni sì kú, Hanuni ọmọ rẹ̀ sì jẹ ọba ní ipò rẹ̀.
1 E ocorreu, depois disso, que o rei dos filhos de Amom morreu, e Hanum, seu filho, reinou em seu lugar.
2 Dafidi sì wí pé, “Èmi yóò ṣe oore fún Hanuni ọmọ Nahaṣi gẹ́gẹ́ bí baba rẹ̀ sì ti ṣe oore fún mi.” Dafidi sì ránṣẹ́ láti tù Hanuni nínú láti ọwọ́ àwọn ìránṣẹ́ rẹ̀ wá, nítorí ti baba rẹ̀.
2 Então, Davi disse: Mostrarei bondade para com Hanum, filho de Naás, como o seu pai mostrou bondade para comigo. E Davi enviou consolo a ele pela mão dos seus servos por causa do seu pai. E os servos de Davi adentraram a terra dos filhos de Amom.
3 Àwọn olórí àwọn ọmọ Ammoni sì wí fún Hanuni olúwa wọn pé, “Ǹjẹ́ o rò pé Dafidi ń bu ọlá fún baba rẹ nígbà tí ó rán ènìyàn wá láti bá ọ kẹ́dùn? Kò ha ṣe pé Dafidi rán àwọn ìránṣẹ́ sí ọ láti wo ìlú àti láti yọ́ ọ wò àti láti gbà ọ́.”
3 E os príncipes dos filhos de Amom disseram a Hanum, o seu senhor: Tu pensas que Davi presta honra ao teu pai, por isso ele enviou consoladores até ti? Porventura não enviou Davi os seus servos a ti para investigar a cidade, e para espioná-la, e para derrubá-la?
4 Hanuni sì mú àwọn ìránṣẹ́ Dafidi ó fá apá kan irùngbọ̀n wọn, ó sì gé ààbọ̀ kúrò ní agbádá wọn, títí ó fi dé ìdí wọn, ó sì rán wọn lọ.
4 Pelo que Hanum tomou os servos de Davi, e raspou metade das suas barbas, e cortou fora metade das suas vestes, até as suas nádegas, e os despediu.
5 Wọ́n sì sọ fún Dafidi, ó sì ránṣẹ́ lọ pàdé wọn, nítorí tí ojú ti àwọn ọkùnrin náà púpọ̀: ọba sì wí pé, “Ẹ dúró ní Jeriko títí irùngbọ̀n yín yóò fi hù, nígbà náà ni kí ẹ tó máa bọ̀.”
5 Quando disseram isto a Davi, ele enviou para encontrá-los, porque os homens estavam sobremaneira envergonhados; e o rei disse: Aguardai em Jericó até que as vossas barbas estejam crescidas e, depois, retornai.
6 Àwọn ará Ammoni sì ri pé, wọ́n di ẹni ìríra níwájú Dafidi, àwọn ọmọ Ammoni sì ránṣẹ́, wọ́n sì fi owó bẹ́ ogún àwọn ará Siria ti Beti-Rehobu; àti Siria-Soba, ogún ẹgbẹ̀rún (20,000) ẹlẹ́ṣẹ̀ àti ti ọba Maaka, ẹgbẹ̀rún (1,000) ọkùnrin àti ti Tobu ẹgbàá mẹ́fà (12,000) ọkùnrin lọ́wẹ̀.
6 E quando os filhos de Amom viram que eles fediam diante de Davi, os filhos de Amom enviaram e contrataram os sírios de Bete-Reobe, e os sírios de Zobá, vinte mil homens de pé, e do rei Maaca mil homens, e de Istobe doze mil homens.
7 Dafidi sì gbọ́, ó sì rán Joabu, àti gbogbo ogún àwọn ọkùnrin alágbára.
7 E quando Davi ouviu isto, ele enviou Joabe, e todo o exército dos homens poderosos.
8 Àwọn ọmọ Ammoni sì jáde wá, wọ́n sì tẹ́ ogun ní ẹnu odi; ará Siria-Soba, àti ti Rehobu, àti Tobu, àti Maaka, wọ́n sì tẹ ogun ni pápá fún ara wọn.
8 E os filhos de Amom saíram, e ordenaram a batalha à entrada do portão; e os sírios de Zobá, de Reobe, de Istobe e de Maaca estavam sozinhos no campo.
9 Nígbà tí Joabu sì rí i pé ogun náà dojúkọ òun níwájú àti lẹ́yìn, ó sì yàn nínú gbogbo àwọn akíkanjú ọkùnrin ní Israẹli, ó sì tẹ́ ogun kọjú sí àwọn ará Siria.
9 Quando Joabe viu que a frente da batalha estava contra ele pela dianteira e retaguarda, ele escolheu de todos os homens escolhidos de Israel, e os pôs em formação contra os sírios;
10 Ó sì fi àwọn ènìyàn tí ó kù lé Abiṣai àbúrò rẹ̀ lọ́wọ́, kí ó lè tẹ ogun kọjú sí àwọn ọmọ Ammoni.
10 e o restante do povo ele entregou na mão de Abisai, seu irmão, para que ele pudesse colocá-los em formação contra os filhos de Amom.
11 Ó sì wí pé, “Bí agbára àwọn ará Siria bá pọ̀ ju èmi lọ, ìwọ yóò sì wá ràn mí lọ́wọ́, ṣùgbọ́n bí ọwọ́ àwọn ọmọ Ammoni bá sì pọ̀jù ọ́ lọ, èmi ó sì wá ràn ọ́ lọ́wọ́.
11 E ele disse: Se os sírios me forem demasiadamente fortes, então tu me ajudarás; mas se os filhos de Amom te forem demasiadamente fortes, então eu virei e te ajudarei.
12 Mú ọkàn lè, jẹ́ kí a ṣe onígboyà nítorí àwọn ènìyàn wa, àti nítorí àwọn ìlú Ọlọ́run wa; Olúwa yóò sì ṣe èyí tí ó dára lójú rẹ̀.”
12 Seja de boa coragem, e vamos jogar com os homens em favor do nosso povo, e das cidades do nosso Deus; e faça o SENHOR aquilo que lhe parecer bom.
13 Joabu àti àwọn ènìyàn tí ń bẹ lọ́dọ̀ rẹ̀ sì bá àwọn ará Siria pàdé ìjà, wọ́n sì sá níwájú rẹ̀.
13 E Joabe se aproximou, e o povo que estava com ele, para a batalha contra os sírios; e eles fugiram diante dele.
14 Nígbà tí àwọn ọmọ Ammoni sì rí i pé àwọn ará Siria sá, àwọn pẹ̀lú sì sá níwájú Abiṣai, wọ́n sì wọ inú ìlú lọ. Joabu sì padà kúrò lẹ́yìn àwọn ọmọ Ammoni, ó sì wá sí Jerusalẹmu.
14 E quando os filhos de Amom viram que os sírios haviam fugido, então fugiram também eles diante de Abisai, e entraram na cidade. Assim, Joabe retornou dos filhos de Amom e chegou a Jerusalém.
15 Nígbà tí àwọn ará Siria sì rí i pé àwọn ṣubú níwájú Israẹli, wọ́n sì kó ara wọn jọ
15 E quando os sírios viram que eles foram feridos diante de Israel, eles se reuniram todos.
16 Hadadeseri sì ránṣẹ́, ó sì mú àwọn Siria tí ó wà ní òkè odò Eufurate jáde wá, wọ́n sì wá sí Helami; Sobaki olórí ogun Hadadeseri sì ṣe olórí wọn.
16 E Hadadezer enviou, e retirou os sírios que estavam além do rio; e eles vieram até Helã; e Sobaque, o capitão do exército de Hadadezer, foi adiante deles.
17 Nígbà tí a sọ fún Dafidi, ó sì kó gbogbo Israẹli jọ, wọ́n sì kọjá Jordani, wọ́n sì wá sí Helami, àwọn ará Siria sì tẹ́ ogun kọjú sí Dafidi, wọ́n sì bá a jà.
17 E quando contaram a Davi, ele reuniu todo o Israel, e atravessou o Jordão, e chegou a Helã. E os sírios se puseram em formação contra Davi, e lutaram contra ele.
18 Àwọn ará Siria sì sá níwájú Israẹli, Dafidi sì pa nínú àwọn ará Siria ẹ̀ẹ́dẹ́gbẹ̀rin (700) àwọn oníkẹ̀kẹ́, àti ọ̀kẹ́ méjì (40,000) ẹlẹ́ṣin, wọ́n sì kọlu Sobaki olórí ogun wọn, ó sì kú níbẹ̀.
18 E os sírios fugiram diante de Israel; e Davi matou os homens de setecentas carruagens dos sírios, e quarenta mil cavaleiros, e feriu Sobaque, o capitão do exército deles, que morreu ali.
19 Nígbà tí gbogbo àwọn ọba tí ó wà lábẹ́ Hadadeseri sì rí i pé wọ́n di bíbì ṣubú níwájú Israẹli, wọ́n sì bá Israẹli làjà, wọ́n sì ń sìn wọ́n.
19 E quando todos os reis que eram servos de Hadadezer viram que eles foram feridos diante de Israel, fizeram paz com Israel, e os serviram. Assim, os sírios temeram ajudar os filhos de Amom futuramente.
Atalhos do teclado
- Capítulo anterior←
- Próximo capítulo→
- Versículo anteriork
- Próximo versículoj
- Limpar seleçãoEsc
- Esta ajuda?
Estude este capítulo no WhatsApp
Peça à IA da Bíblia Fala para explicar 2 Samuel 10, comparar traduções ou montar um estudo — tudo direto pelo WhatsApp.