2 Crônicas 2

Biblica® ní oore ọ̀fẹ́ láti lo Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde-Òní (YOR) vs NTLH

Sair da comparação
NTLH Nova Tradução na Linguagem de Hoje 2000
1 Solomoni pinnu láti kọ́ ilé fún orúkọ Olúwa àti ilé kan fún ìjọba rẹ̀
1 O rei Salomão resolveu construir um templo para a adoração de Deus, o Senhor , e também um palácio para si mesmo.
2 Solomoni sì yan ẹgbẹ̀rún ní ọ̀nà àádọ́rin (70,000) àwọn ọkùnrin láti ru ẹrù àti ọ̀kẹ́ mẹ́rin (80,000) àwọn ọkùnrin gẹ́gẹ́ bi olùgé-òkúta ní àwọn òkè àti ẹgbẹ̀rún mẹ́rìndínlógójì (36,000) gẹ́gẹ́ bí àwọn alábojútó lórí wọn.
2 Alistou setenta mil homens para carregarem o material e oitenta mil para cortarem pedras nas montanhas. E colocou três mil e seiscentos chefes para dirigirem o trabalho.
3 Solomoni rán iṣẹ́ yìí sí Hiramu ọba Tire:
3 Depois mandou a Hirão, rei de Tiro, a seguinte mensagem: “Você vendeu ao meu pai, o rei Davi, cedros para que ele construísse o seu palácio. Agora faça o mesmo comigo.
4 Nísinsin yìí, èmi n kọ́ ilé kan fún orúkọ Olúwa Ọlọ́run mi àti láti yà á sí mímọ́ fún un àti láti sun tùràrí olóòórùn dídùn níwájú rẹ̀, fún gbígbé àkàrà ìfihàn ìgbàkúgbà, àti fún ṣíṣe ẹbọ sísun ní gbogbo àárọ̀ àti ìrọ̀lẹ́ àti ní ọjọọjọ́ ìsinmi àti oṣù tuntun àti ní àjọ̀dún tí a yàn ti Olúwa Ọlọ́run wa. Èyí ni àṣẹ fún Israẹli láéláé.
4 Estou pronto para construir um templo onde o Senhor , meu Deus, será adorado. Será um lugar santo, onde queimaremos incenso cheiroso em adoração a Deus e lhe apresentaremos sempre os pães sagrados. Todas as manhãs e todas as tardes, ofereceremos em sacrifício animais que serão completamente queimados; faremos a mesma coisa nos sábados, nas Festas da Lua Nova e nas outras festas em honra do Senhor , nosso Deus. É nossa obrigação fazer isso para sempre.
5 “Ilé Olúwa tí èmi yóò kọ́ yóò tóbi, nítorí pé Ọlọ́run wa tóbi ju gbogbo àwọn ọlọ́run mìíràn lọ.
5 Vou construir um Templo enorme, pois o nosso Deus é maior do que todos os outros deuses.
6 Ṣùgbọ́n ta ni ó le è kọ́ ilé fún Olúwa, níwọ̀n ìgbà tí àwọn ọ̀run, àní ọ̀run àwọn ọ̀run tó ga jùlọ, kò le è gbà á? Ta ni èmi nígbà náà láti kọ́ ilé fún Olúwa, bí kò ṣe kìkì àti sun ẹbọ sun ẹbọ níwájú rẹ̀?
6 Mas, se Deus não cabe nem mesmo no céu, que é tão grande, quem pode construir um templo para ele? E quem sou eu para levantar um templo digno de Deus, a não ser que seja um lugar onde se queime incenso em honra dele?
7 “Nítorí náà, rán ọkùnrin kan sí mi, tí a kọ́ láti ṣiṣẹ́ pẹ̀lú wúrà àti fàdákà àti idẹ àti irin, àti ní àwọ̀ àlùkò àti àwọ̀ pupa fòò àti ní àwọ̀ ojú ọ̀run, tí ó jẹ́ onímọ̀ nínú iṣẹ́ igi gbígbẹ́ láti ṣiṣẹ́ ní Juda àti Jerusalẹmu pẹ̀lú àwọn onímọ̀ oníṣọ̀nà tí baba à mi Dafidi pèsè.
7 Portanto, mande-me um homem que saiba trabalhar em ouro, prata, bronze e ferro; que saiba fazer tecidos de fios de lã púrpura , vermelha e azul e que saiba entalhar madeira. Ele trabalhará em Judá e em Jerusalém com os meus artesãos que foram contratados por Davi, o meu pai.
8 “Fi ìtì igi kedari, junifa àti algumu ránṣẹ́ sí mi, láti Lebanoni, nítorí tí mo mọ̀ pé àwọn ọkùnrin rẹ ní ìmọ̀ nínú gígé igi rírẹ́. Àwọn ọkùnrin mi yóò ṣiṣẹ́ pẹ̀lú àwọn ọkùnrin rẹ.
8 Sei que os seus trabalhadores sabem cortar árvores; portanto, mande-me do Líbano madeira de cedro, de pinho e de sândalo. Os meus homens trabalharão junto com os seus,
9 Láti pèsè ọ̀pọ̀ igi rírẹ́ fún mi, nítorí ilé Olúwa tí mo kọ́ gbọdọ̀ tóbi kí o sì lógo púpọ̀.
9 a fim de preparar muita madeira, pois o templo que vou construir será grande e maravilhoso.
10 Èmi yóò fún àwọn ìránṣẹ́ rẹ, àwọn ọkùnrin agégi tí ó ń gé ìtì igi náà ni ogún ẹgbẹ̀rún (20,000), alikama ilẹ̀ àti ogún ẹgbẹ̀rún (20,000), ọ̀pọ̀lọpọ̀ ti barle; ogún ẹgbẹ̀rún (20,000), bati ọtí wáìnì àti ogún ẹgbẹ̀rún (20,000) bati òróró olifi.”
10 Para os seus trabalhadores que vão cortar as árvores eu fornecerei duas mil toneladas de trigo, duas mil toneladas de cevada , quatrocentos mil litros de vinho e quatrocentos mil litros de azeite.”
11 Hiramu ọba Tire fèsì padà nípasẹ̀ ìwé sí Solomoni:
11 Em resposta, o rei Hirão mandou a Salomão a seguinte carta: “O
12 Hiramu fi kún un pe,
12 Louvado seja o Senhor , o Deus de Israel, o Criador do céu e da terra! Louvado seja Deus, que deu ao rei Davi um filho tão cheio de sabedoria, tão inteligente e prudente, que vai construir um templo para Deus e um palácio para si mesmo!
13 “Èmi ń rán Huramu-Abi, ọkùnrin tí ó kún fún ìmọ̀ àti òye sí ọ.
13 E agora eu vou lhe mandar Hurã, um mestre artesão inteligente e capaz.
14 Ọmọbìnrin kan nínú àwọn ọmọbìnrin Dani àti tí baba a rẹ̀ wá láti Tire tí ó gbọ́ngbọ́n àti ṣiṣẹ́ ní wúrà àti ní fàdákà, ní idẹ, ní irin, ní òkúta àti ní ìtì igi, ní èse-àlùkò, ní aláró, àti ní ọ̀gbọ̀ tí ó dára, àti òdòdó, láti gbẹ́ onírúurú ohun gbígbẹ́ pẹ̀lú, àti láti ṣe àwárí ìmọ̀ ẹ̀rọ irú ẹ̀yàkẹ́yà tí a ó fún un ṣe. Òun yóò ṣiṣẹ́ pẹ̀lú àwọn ọlọ́gbọ́n rẹ̀, àti pẹ̀lú àwọn ọlọ́gbọ́n olúwa mi, Dafidi baba a rẹ.
14 A sua mãe pertencia à tribo de Dã, e o seu pai era da cidade de Tiro. Ele trabalha em ouro, prata, bronze, ferro, pedra e madeira; sabe fazer tecidos de linho fino e de fios de lã púrpura, azul e vermelha. É perito também em obras de entalhe e sabe executar qualquer desenho que lhe seja apresentado. Ele trabalhará com os seus artesãos e com os artesãos do rei Davi, o seu ilustre pai.
15 “Nísinsin yìí, jẹ́ kí olúwa mi rán àwọn ìránṣẹ́ rẹ̀ ní alikama àti barle àti òróró Olifi náà àti ọtí tí ó ti ṣe ìlérí.
15 Eu peço que você nos mande o trigo, a cevada, o vinho e o azeite que prometeu.
16 Àwa yóò sì gé gbogbo àwọn ìtí igi láti Lebanoni tí ìwọ yóò lò pẹ̀lú a ó gbé wọn fò lójú omi òkun lọ sí Joppa. Lẹ́yìn náà ìwọ lè kó wọn gòkè lọ sí Jerusalẹmu.”
16 Nós cortaremos nos montes Líbanos todas as árvores que você precisar. Levaremos as toras até o mar, faremos jangadas com elas e as levaremos por mar até o porto de Jope. Dali você as levará para Jerusalém.”
17 Solomoni ka iye àwọn àjèjì tí ó wà ní Israẹli lẹ́yìn kíka iye wọn tí baba a rẹ̀ Dafidi ti ṣe; a sì ka iye wọn sí ọ̀kẹ́ mẹ́jọ ó dín egbèjìlélọ́gbọ̀n (153,600).
17 O rei Salomão fez uma contagem de todos os estrangeiros que moravam em Israel, como Davi, o seu pai, tinha feito. Havia no país cento e cinquenta e três mil e seiscentos estrangeiros.
18 Ó sì yan ẹgbẹ̀rún ní ọ̀nà àádọ́rin (70,000) nínú wọn láti ru ẹrù, àti ọ̀kẹ́ mẹ́rin (80,000) láti ṣe àgọ́ òkúta lórí òkè, àti egbèjìdínlógún (3,600) alábojútó láti kó àwọn ènìyàn ṣiṣẹ́.
18 Salomão separou setenta mil deles para carregarem o material, oitenta mil para cortarem pedras nas montanhas e três mil e seiscentos como chefes para dirigirem o trabalho.

Ler em outra tradução

Comparar com outra

Estude este capítulo no WhatsApp

Peça à IA da Bíblia Fala para explicar 2 Crônicas 2, comparar traduções ou montar um estudo — tudo direto pelo WhatsApp.