2 Crônicas 2

Biblica® ní oore ọ̀fẹ́ láti lo Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde-Òní (YOR) vs BKJ

Sair da comparação
1 Solomoni pinnu láti kọ́ ilé fún orúkọ Olúwa àti ilé kan fún ìjọba rẹ̀
1 E Salomão determinou a construção de uma casa para o nome do SENHOR, e de uma casa para o seu reino.
2 Solomoni sì yan ẹgbẹ̀rún ní ọ̀nà àádọ́rin (70,000) àwọn ọkùnrin láti ru ẹrù àti ọ̀kẹ́ mẹ́rin (80,000) àwọn ọkùnrin gẹ́gẹ́ bi olùgé-òkúta ní àwọn òkè àti ẹgbẹ̀rún mẹ́rìndínlógójì (36,000) gẹ́gẹ́ bí àwọn alábojútó lórí wọn.
2 E Salomão recrutou setenta mil homens para levar cargas, e oitenta mil para talharem no monte, e três mil e seiscentos para os supervisionar.
3 Solomoni rán iṣẹ́ yìí sí Hiramu ọba Tire:
3 E Salomão mandou dizer a Hirão, o rei de Tiro: Assim como tu fizeste com Davi, meu pai, e lhe enviaste cedros para lhe construir uma casa para nela habitar, assim também faze comigo.
4 Nísinsin yìí, èmi n kọ́ ilé kan fún orúkọ Olúwa Ọlọ́run mi àti láti yà á sí mímọ́ fún un àti láti sun tùràrí olóòórùn dídùn níwájú rẹ̀, fún gbígbé àkàrà ìfihàn ìgbàkúgbà, àti fún ṣíṣe ẹbọ sísun ní gbogbo àárọ̀ àti ìrọ̀lẹ́ àti ní ọjọọjọ́ ìsinmi àti oṣù tuntun àti ní àjọ̀dún tí a yàn ti Olúwa Ọlọ́run wa. Èyí ni àṣẹ fún Israẹli láéláé.
4 Eis que edifico uma casa para o nome do SENHOR meu Deus, para lhe consagrar, para queimar perante ele incenso aromático, e para a apresentação contínua do pão da proposição, para as ofertas queimadas da manhã e da tarde, nos shabats e nas luas novas, e nas festas solenes do SENHOR nosso Deus. Esta é uma ordenança eterna para Israel.
5 “Ilé Olúwa tí èmi yóò kọ́ yóò tóbi, nítorí pé Ọlọ́run wa tóbi ju gbogbo àwọn ọlọ́run mìíràn lọ.
5 E a casa que eu edifico é grande; porque grande é o nosso Deus acima de todos os deuses.
6 Ṣùgbọ́n ta ni ó le è kọ́ ilé fún Olúwa, níwọ̀n ìgbà tí àwọn ọ̀run, àní ọ̀run àwọn ọ̀run tó ga jùlọ, kò le è gbà á? Ta ni èmi nígbà náà láti kọ́ ilé fún Olúwa, bí kò ṣe kìkì àti sun ẹbọ sun ẹbọ níwájú rẹ̀?
6 Porém, quem é capaz de edificar-lhe uma casa, vendo que o céu e até o céu dos céus não podem contê-lo? Quem sou eu, então, para que lhe edifique uma casa, salvo para somente queimar sacrifício diante dele?
7 “Nítorí náà, rán ọkùnrin kan sí mi, tí a kọ́ láti ṣiṣẹ́ pẹ̀lú wúrà àti fàdákà àti idẹ àti irin, àti ní àwọ̀ àlùkò àti àwọ̀ pupa fòò àti ní àwọ̀ ojú ọ̀run, tí ó jẹ́ onímọ̀ nínú iṣẹ́ igi gbígbẹ́ láti ṣiṣẹ́ ní Juda àti Jerusalẹmu pẹ̀lú àwọn onímọ̀ oníṣọ̀nà tí baba à mi Dafidi pèsè.
7 Envia-me, agora, portanto, um homem perito para trabalhar em ouro, e em prata, e em bronze, e em ferro, e em púrpura, e escarlate, e azul, e que possa ser hábil em entalhar com os peritos que estão comigo em Judá e em Jerusalém, aos quais Davi, o meu pai, proveu.
8 “Fi ìtì igi kedari, junifa àti algumu ránṣẹ́ sí mi, láti Lebanoni, nítorí tí mo mọ̀ pé àwọn ọkùnrin rẹ ní ìmọ̀ nínú gígé igi rírẹ́. Àwọn ọkùnrin mi yóò ṣiṣẹ́ pẹ̀lú àwọn ọkùnrin rẹ.
8 Envia-me também madeiras de cedro, cipreste e algumins, do Líbano; porque sei que os teus servos podem ser hábeis em cortar madeira no Líbano; e eis que os meus servos estarão com os teus servos,
9 Láti pèsè ọ̀pọ̀ igi rírẹ́ fún mi, nítorí ilé Olúwa tí mo kọ́ gbọdọ̀ tóbi kí o sì lógo púpọ̀.
9 só para preparar madeira para mim em abundância; porquanto a casa que estou prestes a edificar será grande e maravilhosa.
10 Èmi yóò fún àwọn ìránṣẹ́ rẹ, àwọn ọkùnrin agégi tí ó ń gé ìtì igi náà ni ogún ẹgbẹ̀rún (20,000), alikama ilẹ̀ àti ogún ẹgbẹ̀rún (20,000), ọ̀pọ̀lọpọ̀ ti barle; ogún ẹgbẹ̀rún (20,000), bati ọtí wáìnì àti ogún ẹgbẹ̀rún (20,000) bati òróró olifi.”
10 E, eis que darei aos teus servos, os talhadores que cortam madeira, vinte mil medidas de trigo batido, e vinte mil medidas de cevada, e vinte mil batos de vinho, e vinte mil batos de azeite.
11 Hiramu ọba Tire fèsì padà nípasẹ̀ ìwé sí Solomoni:
11 Então, Hirão, o rei de Tiro, respondeu por escrito, o que enviou a Salomão: Porque o SENHOR tem amado o seu povo, ele te fez rei sobre eles.
12 Hiramu fi kún un pe,
12 Além disso, Hirão também disse: Bendito seja o SENHOR Deus de Israel, que fez céu e terra, que tem dado ao rei Davi, um filho sábio, dotado de prudência e entendimento, para que pudesse edificar uma casa para o SENHOR, e uma casa para o seu reino.
13 “Èmi ń rán Huramu-Abi, ọkùnrin tí ó kún fún ìmọ̀ àti òye sí ọ.
13 E, agora eu envio um perito, dotado de entendimento, Hirão o pai,
14 Ọmọbìnrin kan nínú àwọn ọmọbìnrin Dani àti tí baba a rẹ̀ wá láti Tire tí ó gbọ́ngbọ́n àti ṣiṣẹ́ ní wúrà àti ní fàdákà, ní idẹ, ní irin, ní òkúta àti ní ìtì igi, ní èse-àlùkò, ní aláró, àti ní ọ̀gbọ̀ tí ó dára, àti òdòdó, láti gbẹ́ onírúurú ohun gbígbẹ́ pẹ̀lú, àti láti ṣe àwárí ìmọ̀ ẹ̀rọ irú ẹ̀yàkẹ́yà tí a ó fún un ṣe. Òun yóò ṣiṣẹ́ pẹ̀lú àwọn ọlọ́gbọ́n rẹ̀, àti pẹ̀lú àwọn ọlọ́gbọ́n olúwa mi, Dafidi baba a rẹ.
14 o filho de uma mulher das filhas de Dã, e o seu pai era um homem de Tiro, perito no trabalho em ouro, e em prata, em bronze, em ferro, em pedra, e em madeira, em púrpura, em azul e em linho fino, e em escarlate; também para entalhar toda sorte de entalhes, e para desvendar toda invenção que lhe for apresentada, com os teus peritos, e com os peritos do meu senhor Davi, teu pai.
15 “Nísinsin yìí, jẹ́ kí olúwa mi rán àwọn ìránṣẹ́ rẹ̀ ní alikama àti barle àti òróró Olifi náà àti ọtí tí ó ti ṣe ìlérí.
15 Agora, portanto, o trigo e a cevada, o azeite, e o vinho, dos quais o meu senhor falou, que ele os envie aos seus servos;
16 Àwa yóò sì gé gbogbo àwọn ìtí igi láti Lebanoni tí ìwọ yóò lò pẹ̀lú a ó gbé wọn fò lójú omi òkun lọ sí Joppa. Lẹ́yìn náà ìwọ lè kó wọn gòkè lọ sí Jerusalẹmu.”
16 e nós cortaremos madeira do Líbano, o tanto quanto precisares; e a levaremos a ti em jangadas pelo mar até Jope; e tu as farás subir até Jerusalém.
17 Solomoni ka iye àwọn àjèjì tí ó wà ní Israẹli lẹ́yìn kíka iye wọn tí baba a rẹ̀ Dafidi ti ṣe; a sì ka iye wọn sí ọ̀kẹ́ mẹ́jọ ó dín egbèjìlélọ́gbọ̀n (153,600).
17 E Salomão contou todos os estrangeiros que estavam na terra de Israel, segundo a contagem com a qual Davi, o seu pai, havia-lhes contado; e foram achados cento e cinquenta e três mil e seiscentos.
18 Ó sì yan ẹgbẹ̀rún ní ọ̀nà àádọ́rin (70,000) nínú wọn láti ru ẹrù, àti ọ̀kẹ́ mẹ́rin (80,000) láti ṣe àgọ́ òkúta lórí òkè, àti egbèjìdínlógún (3,600) alábojútó láti kó àwọn ènìyàn ṣiṣẹ́.
18 E ele designou setenta mil para serem carregadores de cargas, e oitenta mil para serem talhadores no monte, e três mil e seiscentos supervisores para colocar o povo ao trabalho.

Ler em outra tradução

Comparar com outra

Estude este capítulo no WhatsApp

Peça à IA da Bíblia Fala para explicar 2 Crônicas 2, comparar traduções ou montar um estudo — tudo direto pelo WhatsApp.