1 Crônicas 9
Biblica® ní oore ọ̀fẹ́ láti lo Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde-Òní (YOR) vs NTLH
1 Gbogbo Israẹli ni a kọ lẹ́sẹẹsẹ nínú ìtàn ìdílé láti ọ̀dọ̀ àwọn baba ńlá nínú ìwé àwọn ọba Israẹli. Àwọn ènìyàn Juda ni a kó ní ìgbèkùn lọ sí Babeli nítorí àìṣòótọ́ wọn.
1 Fizeram uma lista de todo o povo de Israel de acordo com as suas famílias, e isso foi escrito no Livro dos Reis de Israel . O povo de Judá havia sido levado prisioneiro para a Babilônia como castigo pelos seus pecados.
2 Nísinsin yìí, àwọn tí ó kọ́kọ́ tún tẹ̀dó lórí ohun ìní wọn ní ìlú wọn ni díẹ̀ nínú àwọn ọmọ Israẹli, àwọn àlùfáà, àwọn ará Lefi àti àwọn ìránṣẹ́ ilé Olúwa.
2 Os primeiros que voltaram a morar nas suas propriedades e nas suas cidades foram gente do povo, sacerdotes, levitas e servidores do Templo.
3 Àwọn tí ó wá láti Juda láti Benjamini àti láti Efraimu àti Manase tí ó ń gbé ní Jerusalẹmu jẹ́:
3 Pessoas das tribos de Judá, Benjamim, Efraim e Manassés foram morar em Jerusalém. O líder dos descendentes de Peres, filho de Judá, foi Utai, filho de Amiúde e neto de Onri. Entre os seus antepassados estavam Inri e Bani. O líder dos descendentes de Selá, filho de Judá, foi Asaías, que era o chefe da sua família. O líder dos descendentes de Zera, filho de Judá, foi Jeuel. Salu, filho de Mesulã, neto de Hodavias e bisneto de Hassenuá; Ibneias, filho de Jeroão; Elá, filho de Uzi e neto de Micri; Mesulã, filho de Sefatias, neto de Reuel e bisneto de Ibnijas.
4 Uttai ọmọ Ammihudu, ọmọ Omri, ọmọ Imri, ọmọ Bani, ìran ọmọ Peresi ọmọ Juda.
4 — ausente —
5 Àti nínú ará Ṣilo:
5 — ausente —
6 Ní ti ará Sera:
6 — ausente —
7 Àti nínú àwọn ọmọ Benjamini ni:
7 — ausente —
8 Ibinaiah ọmọ Jerohamu;
8 — ausente —
9 Àwọn ènìyàn láti Benjamini gẹ́gẹ́ bí a ti ṣe kọ ọ́ nínú ìran wọn nínú ìtàn ìdílé láti ọ̀dọ̀ baba ńlá wọn, tí ó jẹ́ ẹgbẹ̀rún ó dín mẹ́rìnlélógójì (956). Gbogbo àwọn ọkùnrin yí jẹ́ àwọn olórí àwọn ìdílé.
9 Novecentas e cinquenta e seis famílias da tribo de Benjamim moravam em Jerusalém. Todos os homens cujos nomes estão escritos acima eram chefes de famílias. Jedaías, Jeoiaribe e Jaquim. Ali morava também Azarias, que era o administrador do Templo; ele era filho de Hilquias, neto de Mesulã, bisneto de Zadoque, trineto de Meraiote e tetraneto de Aitube. Adaías, filho de Jeroão, neto de Pasur e bisneto de Malquias. Masai, filho de Adiel, neto de Jazera, bisneto de Mesulã, trineto de Mesilemite e tetraneto de Imer.
10 Ní ti àwọn àlùfáà:
10 — ausente —
11 Asariah ọmọ Hilkiah, ọmọ Meṣullamu, ọmọ Sadoku, ọmọ Meraioti, ọmọ Ahitubu, olórí tí ó ń bojútó ilé Ọlọ́run;
11 — ausente —
12 Adaiah ọmọ Jerohamu, ọmọ Paṣuri, ọmọ Malkiah;
12 — ausente —
13 Àwọn àlùfáà, tí wọ́n jẹ́ àwọn olórí àwọn ìdílé, tí ó jẹ́ ẹgbẹ̀sán ó dín méjì (1,760). Wọ́n jẹ́ alágbára ọkùnrin, tí wọ́n lè dúró fún iṣẹ́ ìránṣẹ́ nínú ilé Ọlọ́run.
13 Havia mil setecentos e sessenta sacerdotes que eram chefes de famílias. Eles estavam preparados para fazer todos os trabalhos do Templo. Semaías, filho de Hassube, neto de Azricã e bisneto de Hasabias. Ele era do grupo de famílias de Merari. Baquebacar, Heres e Galal. Matanias, filho de Mica, neto de Zicri e bisneto de Asafe. Obadias, filho de Semaías, neto de Galal e bisneto de Jedutum. Berequias, filho de Asa e neto de Elcana, que morava nas terras que pertenciam à cidade de Netofa.
14 Ní ti àwọn ará Lefi:
14 — ausente —
15 Bakibakari, Hereṣi, Galali àti Mattaniah, ọmọ Mika, ọmọ Sikri, ọmọ Asafu;
15 — ausente —
16 Obadiah ọmọ Ṣemaiah, ọmọ Galali, ọmọ Jedutuni;
16 — ausente —
17 Àwọn olùtọ́jú ẹnu-ọ̀nà:
17 Moravam em Jerusalém os seguintes guardas do Templo: Salum, Acube, Talmom e Aimã. Salum era o chefe deles.
18 ti wà ní ipò ìdúró ní ẹnu-ọ̀nà ọba ní apá ìhà ìlà-oòrùn títí di àkókò yí. Wọ̀nyí ni àwọn olùtọ́jú ẹnu-ọ̀nà tí ó jẹ́ ti ìpàgọ́ àwọn ará Lefi.
18 Desde aquele tempo até hoje , membros dos seus grupos de famílias têm sido guardas do Portão do Rei , que ficava no lado leste do Templo. Antigamente eles eram os guardas dos portões dos acampamentos dos levitas .
19 Ṣallumu ọmọ Kore ọmọ Ebiasafi, ọmọ Kora, àti àwọn olùtọ́jú ẹnu-ọ̀nà ẹlẹgbẹ́ rẹ̀. Láti ìdílé rẹ̀ (àwọn ará Korati) ni ó dúró fún ṣíṣọ́ ìloro ẹnu-ọ̀nà àgọ́ gẹ́gẹ́ bí baba wọn ti ń dúró fún ṣíṣọ́ àbáwọlé ibùgbé Olúwa.
19 Salum, filho de Coré e neto de Ebiasafe, e também os seus parentes do grupo de famílias de Corá eram os encarregados de guardar a entrada da Tenda da Presença de Deus , como os seus antepassados haviam sido quando eram os encarregados do acampamento de Deus, o Senhor .
20 Ní ìgbà àkọ́kọ́ Finehasi ọmọ Eleasari jẹ́ olórí fún àwọn olùtọ́jú ẹnu-ọ̀nà, Olúwa sì wà pẹ̀lú rẹ̀.
20 Naquela época, Fineias, filho de Eleazar — que o Senhor esteja com Fineias! — era o chefe deles.
21 Sekariah, ọmọ Meṣelemiah jẹ́ olùtọ́jú ẹnu-ọ̀nà ní àbáwọlé sí àgọ́ ibi ìpàdé.
21 Zacarias, filho de Meselemias, também era guarda da entrada da Tenda da Presença de Deus.
22 Gbogbo rẹ̀ lápapọ̀, àwọn tí a yàn láti jẹ́ olùtọ́jú ẹnu-ọ̀nà ní àwọn ìloro jẹ́ igba ó lé méjìlá (212). A ka àwọn wọ̀nyí nípa ìdílé ní ìletò wọn.
22 Ao todo, duzentos e doze homens foram escolhidos para serem guardas dos portões. Os nomes deles foram escritos numa lista, de acordo com os povoados onde moravam. O rei Davi e o profeta Samuel é que haviam colocado os antepassados deles nesses cargos de confiança.
23 Àwọn àti àwọn ọmọ wọn ni ó wà fún ṣíṣọ́ ẹnu-ọ̀nà ilé Olúwa ilé tí a pè ní àgọ́.
23 Eles e os seus descendentes guardavam os portões da área do Templo.
24 Àwọn olùtọ́jú ẹnu-ọ̀nà wà ní igun mẹ́rẹ̀ẹ̀rin: ìlà-oòrùn, ìwọ̀-oòrùn àríwá àti gúúsù.
24 Havia um portão de frente para cada uma das direções: norte, sul, leste e oeste, e cada portão tinha um guarda-chefe.
25 Àwọn arákùnrin wọn ní àwọn ìletò wọn ní láti wá ní àkókò dé àkókò láti pín iṣẹ́ ìsìn wọn fún àkókò ọjọ́ méje.
25 Esses guardas eram ajudados pelos seus parentes que moravam nos povoados e que se revezavam no trabalho de sete em sete dias.
26 Ṣùgbọ́n àwọn olórí alábojútó ẹnu-ọ̀nà mẹ́rẹ̀ẹ̀rin tí wọ́n jẹ́ ará Lefi ni a yàn fún àwọn iyàrá àti àwọn àpótí ìṣúra ní ilé Ọlọ́run.
26 Os quatro guardas-chefes eram levitas e eram responsáveis por esse trabalho e também vigiavam os cômodos do Templo e as coisas guardadas ali.
27 Wọ́n á lo gbogbo òru ní dídúró yí ilé Ọlọ́run ká, nítorí wọ́n ní láti ṣọ́ ọ, wọ́n sì ní àṣẹ sí kọ́kọ́rọ́ fún ṣíṣí i ní àràárọ̀.
27 Eles moravam perto do Templo porque era seu dever guardá-lo e abrir os portões todas as manhãs.
28 Díẹ̀ wà ní ìdí ohun èlò tí à ń lò fún ìsìn ilé Ọlọ́run; wọn a máa kà á nígbà tí wọ́n gbé e wọlé àti nígbà tí a kó wọn jáde.
28 Os outros levitas eram responsáveis pelos objetos usados no culto. Todas as vezes que esses objetos eram usados, eles os contavam quando eram levados e quando eram devolvidos.
29 Àwọn mìíràn ni a yàn láti bojútó ohun èlò àti gbogbo ohun èlò ilé tí a yà sọ́tọ̀ fún Ọlọ́run, àti ìyẹ̀fun àti ọtí èso àjàrà àti òróró náà, tùràrí àti tùràrí olóòórùn dídùn.
29 Também havia levitas encarregados dos outros objetos sagrados e da farinha de trigo, do vinho, do azeite, do incenso e das especiarias .
30 Ṣùgbọ́n díẹ̀ nínú àwọn àlùfáà ni ó ń bojútó pípò tùràrí olóòórùn dídùn papọ̀.
30 Mas os sacerdotes é que tinham a responsabilidade de misturar as especiarias.
31 Ará Lefi tí a sọ ní Mattitiah àkọ́bí ọmọkùnrin Ṣallumu ará Kora ni a yàn, tí ń ṣe alábojútó ohun tí a dín.
31 Um levita chamado Matitias, que era o filho mais velho de Salum, do grupo de famílias de Corá, era o encarregado de preparar as ofertas de pães .
32 Àti nínú àwọn arákùnrin wọn, nínú àwọn ọmọ Kohati tó ń ṣe ìtọ́jú àkàrà ìfihàn, láti máa pèsè rẹ̀ ní ọjọọjọ́ ìsinmi.
32 Membros do grupo de famílias de Coate estavam encarregados de fazer todos os sábados os pães sagrados para o Templo.
33 Àwọn tí wọ́n jẹ́ ọkùnrin, olórí àwọn ìdílé Lefi dúró nínú àgọ́ ilé Olúwa, wọn kò sì ṣe lára iṣẹ́ ìsìn yòókù nítorí wọ́n ń ṣe iṣẹ́ náà lọ́sàn, lóru.
33 Algumas famílias de levitas eram responsáveis pela música no Templo. Os chefes dessas famílias moravam nos cômodos do Templo e não tinham outros deveres, pois estavam ocupados no seu serviço de dia e de noite.
34 Gbogbo wọ̀nyí jẹ́ olórí àwọn Lefi, olóyè gẹ́gẹ́ bí a ti ṣe kọ lẹ́sẹẹsẹ sínú ìtàn ìdílé láti ọ̀dọ̀ baba ńlá wọn, wọ́n sì ń gbé ní Jerusalẹmu.
34 Foram estes os chefes de famílias de levitas, de acordo com a lista dos nomes dos seus antepassados. Eles eram os líderes que moravam em Jerusalém.
35 Jeieli baba Gibeoni ń gbé ní Gibeoni.
35 Jeiel fundou a cidade de Gibeão e ficou morando ali. A sua mulher se chamava Maacá.
36 pẹ̀lú àkọ́bí ọmọkùnrin rẹ̀ jẹ́ Abdoni, tí wọ̀nyí sì ń tẹ̀lé Suri, Kiṣi, Baali, Neri, Nadabu.
36 O seu filho mais velho se chamava Abdom, e os outros eram Zur, Quis, Baal, Ner, Nadabe,
37 Gedori, Ahio, Sekariah àti Mikiloti.
37 Gedor, Aiô, Zacarias e Miclote.
38 Mikiloti jẹ́ baba Ṣimeamu, àwọn náà ń gbé ní ẹ̀bá ìbátan wọn ní Jerusalẹmu.
38 Miclote foi o pai de Simeia. Os seus descendentes moravam em Jerusalém, perto das outras famílias do seu grupo de famílias.
39 Neri jẹ́ baba Kiṣi, Kiṣi baba a Saulu, àti Saulu baba a Jonatani, àti Malikiṣua, Abinadabu àti Eṣi-Baali.
39 Ner foi pai de Quis, e Quis foi pai de Saul. Saul foi pai de quatro filhos: Jônatas, Malquisua, Abinadabe e Esbaal .
40 Ọmọ Jonatani:
40 Jônatas foi pai de Meribe-Baal , e Meribe-Baal foi pai de Mica.
41 Àwọn ọmọ Mika:
41 Mica foi pai de quatro filhos: Pitom, Meleque, Tareia e Acaz.
42 Ahasi jẹ́ baba Jada, Jada jẹ́ baba Alemeti, Asmafeti, Simri, sì Simri jẹ́ baba Mosa.
42 Acaz foi pai de Jaerá, e Jaerá foi pai de três filhos: Alemete, Azmavete e Zinri. Zinri foi pai de Mosa,
43 Mosa jẹ́ baba Binea; Refaiah jẹ́ ọmọ rẹ̀, Eleasa ọmọ rẹ̀ àti Aseli ọmọ rẹ̀.
43 Mosa foi pai de Bineá, Bineá foi pai de Refaías, Refaías foi pai de Eleasa, e Eleasa foi pai de Azel.
44 Aseli ní ọmọ mẹ́fà, pẹ̀lú wọ̀nyí ni orúkọ wọn:
44 Azel foi pai de seis filhos: Azricã, Bocru, Ismael, Searias, Obadias e Hanã.
Atalhos do teclado
- Capítulo anterior←
- Próximo capítulo→
- Versículo anteriork
- Próximo versículoj
- Limpar seleçãoEsc
- Esta ajuda?
Estude este capítulo no WhatsApp
Peça à IA da Bíblia Fala para explicar 1 Crônicas 9, comparar traduções ou montar um estudo — tudo direto pelo WhatsApp.