1 Crônicas 9

Biblica® ní oore ọ̀fẹ́ láti lo Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde-Òní (YOR) vs BKJ

Sair da comparação
1 Gbogbo Israẹli ni a kọ lẹ́sẹẹsẹ nínú ìtàn ìdílé láti ọ̀dọ̀ àwọn baba ńlá nínú ìwé àwọn ọba Israẹli. Àwọn ènìyàn Juda ni a kó ní ìgbèkùn lọ sí Babeli nítorí àìṣòótọ́ wọn.
1 Assim, todo o Israel foi contado pelas genealogias; e, eis que, eles estão escritos no livro dos Reis de Israel e Judá, que foram levados para Babilônia por causa das suas transgressões.
2 Nísinsin yìí, àwọn tí ó kọ́kọ́ tún tẹ̀dó lórí ohun ìní wọn ní ìlú wọn ni díẹ̀ nínú àwọn ọmọ Israẹli, àwọn àlùfáà, àwọn ará Lefi àti àwọn ìránṣẹ́ ilé Olúwa.
2 Ora, os primeiros habitantes que moraram nas suas possessões, e nas suas cidades foram: Os israelitas, os sacerdotes, os levitas, e os netineus.
3 Àwọn tí ó wá láti Juda láti Benjamini àti láti Efraimu àti Manase tí ó ń gbé ní Jerusalẹmu jẹ́:
3 E em Jerusalém habitaram, dos filhos de Judá, e dos filhos de Benjamim, e dos filhos de Efraim, e Manassés:
4 Uttai ọmọ Ammihudu, ọmọ Omri, ọmọ Imri, ọmọ Bani, ìran ọmọ Peresi ọmọ Juda.
4 Utai, o filho de Amiúde; o filho de Onri, o filho de Inri, o filho de Bani; dos filhos de Perez, o filho de Judá.
5 Àti nínú ará Ṣilo:
5 E dos silonitas: Asaías, o primogênito; e os seus filhos.
6 Ní ti ará Sera:
6 E dos filhos de Zerá: Jeuel, e os seus irmãos; seiscentos e noventa.
7 Àti nínú àwọn ọmọ Benjamini ni:
7 E dos filhos de Benjamim: Salu, o filho de Mesulão, o filho de Hodavias, o filho de Hassenuá,
8 Ibinaiah ọmọ Jerohamu;
8 e Ibneias, o filho de Jeroão; e Elá, o filho de Uzi, o filho de Micri; e Mesulão, o filho de Sefatias, o filho de Reuel, filho de Ibnijas;
9 Àwọn ènìyàn láti Benjamini gẹ́gẹ́ bí a ti ṣe kọ ọ́ nínú ìran wọn nínú ìtàn ìdílé láti ọ̀dọ̀ baba ńlá wọn, tí ó jẹ́ ẹgbẹ̀rún ó dín mẹ́rìnlélógójì (956). Gbogbo àwọn ọkùnrin yí jẹ́ àwọn olórí àwọn ìdílé.
9 e os seus irmãos, segundo as suas gerações; novecentos e cinquenta e seis. Todos estes homens foram chefes dos pais na casa dos seus pais.
10 Ní ti àwọn àlùfáà:
10 E dos sacerdotes: Jedaías, e Jeoiaribe, e Jaquim;
11 Asariah ọmọ Hilkiah, ọmọ Meṣullamu, ọmọ Sadoku, ọmọ Meraioti, ọmọ Ahitubu, olórí tí ó ń bojútó ilé Ọlọ́run;
11 e Azarias, o filho de Hilquias, o filho de Mesulão, o filho de Zadoque, o filho de Meraiote, o filho de Aitube, o regente da casa de Deus;
12 Adaiah ọmọ Jerohamu, ọmọ Paṣuri, ọmọ Malkiah;
12 e Adaías, o filho de Jeroão, o filho de Pasur, o filho de Malquias; e Masai, o filho de Adiel, o filho de Jazera, o filho de Mesulão, o filho de Mesilemite, o filho de Imer;
13 Àwọn àlùfáà, tí wọ́n jẹ́ àwọn olórí àwọn ìdílé, tí ó jẹ́ ẹgbẹ̀sán ó dín méjì (1,760). Wọ́n jẹ́ alágbára ọkùnrin, tí wọ́n lè dúró fún iṣẹ́ ìránṣẹ́ nínú ilé Ọlọ́run.
13 e os seus irmãos, cabeças da casa dos seus pais, mil setecentos e sessenta; homens capacitados para a obra do serviço da casa de Deus.
14 Ní ti àwọn ará Lefi:
14 E dos levitas: Semaías, o filho de Hassube, o filho de Azricão, o filho de Hasabias, dos filhos de Merari;
15 Bakibakari, Hereṣi, Galali àti Mattaniah, ọmọ Mika, ọmọ Sikri, ọmọ Asafu;
15 e Baquebacar, Heres, e Galal, e Matanias, o filho de Mica, o filho de Zicri, o filho de Asafe;
16 Obadiah ọmọ Ṣemaiah, ọmọ Galali, ọmọ Jedutuni;
16 e Obadias, o filho de Semaías, o filho de Galal, o filho de Jedutum; e Berequias, o filho de Asa, o filho de Elcana, que habitou nas aldeias dos netofatitas.
17 Àwọn olùtọ́jú ẹnu-ọ̀nà:
17 E os porteiros foram: Salum, e Acube, e Talmom, e Aimã, e os seus irmãos. Salum foi o chefe;
18 ti wà ní ipò ìdúró ní ẹnu-ọ̀nà ọba ní apá ìhà ìlà-oòrùn títí di àkókò yí. Wọ̀nyí ni àwọn olùtọ́jú ẹnu-ọ̀nà tí ó jẹ́ ti ìpàgọ́ àwọn ará Lefi.
18 que até agora servia no portão do rei, em direção leste; eles foram porteiros nos acampamentos dos filhos de Levi.
19 Ṣallumu ọmọ Kore ọmọ Ebiasafi, ọmọ Kora, àti àwọn olùtọ́jú ẹnu-ọ̀nà ẹlẹgbẹ́ rẹ̀. Láti ìdílé rẹ̀ (àwọn ará Korati) ni ó dúró fún ṣíṣọ́ ìloro ẹnu-ọ̀nà àgọ́ gẹ́gẹ́ bí baba wọn ti ń dúró fún ṣíṣọ́ àbáwọlé ibùgbé Olúwa.
19 E Salum, o filho de Coré, o filho de Ebiasafe, o filho de Corá, e os seus irmãos, da casa do seu pai, os coraítas, estavam sobre a obra do serviço, guardadores dos portões do tabernáculo; e os seus pais, estando sobre o exército do SENHOR, foram os guardadores da entrada.
20 Ní ìgbà àkọ́kọ́ Finehasi ọmọ Eleasari jẹ́ olórí fún àwọn olùtọ́jú ẹnu-ọ̀nà, Olúwa sì wà pẹ̀lú rẹ̀.
20 E Fineias, o filho de Eleazar, foi o regente sobre eles em tempos passados, e o SENHOR esteve com ele.
21 Sekariah, ọmọ Meṣelemiah jẹ́ olùtọ́jú ẹnu-ọ̀nà ní àbáwọlé sí àgọ́ ibi ìpàdé.
21 E Zacarias, o filho de Meselemias, era o porteiro da porta do tabernáculo da congregação.
22 Gbogbo rẹ̀ lápapọ̀, àwọn tí a yàn láti jẹ́ olùtọ́jú ẹnu-ọ̀nà ní àwọn ìloro jẹ́ igba ó lé méjìlá (212). A ka àwọn wọ̀nyí nípa ìdílé ní ìletò wọn.
22 Todos estes que foram escolhidos para serem porteiros nos portões foram duzentos e doze. Estes foram considerados pelas suas genealogias, nas suas aldeias, aos quais Davi e Samuel, o vidente, ordenaram ao seu ofício.
23 Àwọn àti àwọn ọmọ wọn ni ó wà fún ṣíṣọ́ ẹnu-ọ̀nà ilé Olúwa ilé tí a pè ní àgọ́.
23 Eles e os seus filhos tinham a supervisão dos portões da casa do SENHOR, guardavam a casa do tabernáculo.
24 Àwọn olùtọ́jú ẹnu-ọ̀nà wà ní igun mẹ́rẹ̀ẹ̀rin: ìlà-oòrùn, ìwọ̀-oòrùn àríwá àti gúúsù.
24 Nos quatro lados estavam os porteiros, em direção leste, oeste, norte e sul.
25 Àwọn arákùnrin wọn ní àwọn ìletò wọn ní láti wá ní àkókò dé àkókò láti pín iṣẹ́ ìsìn wọn fún àkókò ọjọ́ méje.
25 E os seus irmãos, os quais estavam nas suas aldeias, deveriam vir com eles depois de sete dias, de tempos em tempos.
26 Ṣùgbọ́n àwọn olórí alábojútó ẹnu-ọ̀nà mẹ́rẹ̀ẹ̀rin tí wọ́n jẹ́ ará Lefi ni a yàn fún àwọn iyàrá àti àwọn àpótí ìṣúra ní ilé Ọlọ́run.
26 Porque estes levitas, os quatro porteiros chefes, estavam no seu ofício designado, e encarregados das câmaras e tesouros da casa de Deus.
27 Wọ́n á lo gbogbo òru ní dídúró yí ilé Ọlọ́run ká, nítorí wọ́n ní láti ṣọ́ ọ, wọ́n sì ní àṣẹ sí kọ́kọ́rọ́ fún ṣíṣí i ní àràárọ̀.
27 E eles se alojavam ao redor da casa de Deus, porque a guarda estava sobre eles, e lhes cabia, a cada manhã, a sua abertura.
28 Díẹ̀ wà ní ìdí ohun èlò tí à ń lò fún ìsìn ilé Ọlọ́run; wọn a máa kà á nígbà tí wọ́n gbé e wọlé àti nígbà tí a kó wọn jáde.
28 E alguns deles tinham por incumbência os vasos da ministração, de modo que deveriam trazê-los para dentro e para fora, para contagem.
29 Àwọn mìíràn ni a yàn láti bojútó ohun èlò àti gbogbo ohun èlò ilé tí a yà sọ́tọ̀ fún Ọlọ́run, àti ìyẹ̀fun àti ọtí èso àjàrà àti òróró náà, tùràrí àti tùràrí olóòórùn dídùn.
29 Alguns deles também foram indicados para a supervisão dos vasos, e de todos os instrumentos do santuário, e de farinha fina, e do vinho, e do óleo, e do incenso, e das especiarias.
30 Ṣùgbọ́n díẹ̀ nínú àwọn àlùfáà ni ó ń bojútó pípò tùràrí olóòórùn dídùn papọ̀.
30 E alguns dos filhos dos sacerdotes fizeram um unguento das especiarias.
31 Ará Lefi tí a sọ ní Mattitiah àkọ́bí ọmọkùnrin Ṣallumu ará Kora ni a yàn, tí ń ṣe alábojútó ohun tí a dín.
31 E Matitias, um dos levitas, que foi o primogênito de Salum, o coraíta, tinha por ofício as coisas que eram feitas nas panelas.
32 Àti nínú àwọn arákùnrin wọn, nínú àwọn ọmọ Kohati tó ń ṣe ìtọ́jú àkàrà ìfihàn, láti máa pèsè rẹ̀ ní ọjọọjọ́ ìsinmi.
32 E outros dos seus irmãos, dos filhos dos coatitas, estavam a cargo do pão da proposição, de prepará-lo a cada shabat.
33 Àwọn tí wọ́n jẹ́ ọkùnrin, olórí àwọn ìdílé Lefi dúró nínú àgọ́ ilé Olúwa, wọn kò sì ṣe lára iṣẹ́ ìsìn yòókù nítorí wọ́n ń ṣe iṣẹ́ náà lọ́sàn, lóru.
33 E estes são os cantores, chefes dos pais dos levitas, que permanecendo nas câmaras, estavam livres; pois eles eram empregados naquela obra dia e noite.
34 Gbogbo wọ̀nyí jẹ́ olórí àwọn Lefi, olóyè gẹ́gẹ́ bí a ti ṣe kọ lẹ́sẹẹsẹ sínú ìtàn ìdílé láti ọ̀dọ̀ baba ńlá wọn, wọ́n sì ń gbé ní Jerusalẹmu.
34 Estes pais dos levitas foram chefes ao longo das suas gerações; estes habitaram em Jerusalém.
35 Jeieli baba Gibeoni ń gbé ní Gibeoni.
35 E em Gibeão habitou Jeiel, o pai de Gibeão; e o nome de sua esposa era Maaca.
36 pẹ̀lú àkọ́bí ọmọkùnrin rẹ̀ jẹ́ Abdoni, tí wọ̀nyí sì ń tẹ̀lé Suri, Kiṣi, Baali, Neri, Nadabu.
36 E o seu filho primogênito Abdom, depois Zur, e Quis, e Baal, e Ner, e Nadabe,
37 Gedori, Ahio, Sekariah àti Mikiloti.
37 e Gedor, e Aiô, e Zacarias, e Miclote.
38 Mikiloti jẹ́ baba Ṣimeamu, àwọn náà ń gbé ní ẹ̀bá ìbátan wọn ní Jerusalẹmu.
38 E Miclote gerou Simeia. E estes também habitaram com os seus irmãos em Jerusalém, defronte aos seus irmãos.
39 Neri jẹ́ baba Kiṣi, Kiṣi baba a Saulu, àti Saulu baba a Jonatani, àti Malikiṣua, Abinadabu àti Eṣi-Baali.
39 E Ner gerou Quis, e Quis gerou Saul; e Saul gerou Jônatas, e Malquisua, e Abinadabe, e Esbaal.
40 Ọmọ Jonatani:
40 E o filho de Jônatas foi Meribe-Baal; e Meribe-Baal gerou Mica.
41 Àwọn ọmọ Mika:
41 E os filhos de Mica foram: Pitom, e Meleque, e Tareia, e Acaz.
42 Ahasi jẹ́ baba Jada, Jada jẹ́ baba Alemeti, Asmafeti, Simri, sì Simri jẹ́ baba Mosa.
42 E Acaz gerou Jaerá; e Jaerá gerou Alemete, e Azmavete, e a Zinri; e Zinri gerou Mosa;
43 Mosa jẹ́ baba Binea; Refaiah jẹ́ ọmọ rẹ̀, Eleasa ọmọ rẹ̀ àti Aseli ọmọ rẹ̀.
43 e Mosa gerou Bineá; e Refaías, seu filho, Eleasa seu filho, Azel seu filho.
44 Aseli ní ọmọ mẹ́fà, pẹ̀lú wọ̀nyí ni orúkọ wọn:
44 E Azel teve seis filhos, cujos nomes são estes: Azricão, e Bocru, e Ismael, e Searias, e Obadias, e Hanã. Estes foram os filhos de Azel.

Ler em outra tradução

Comparar com outra

Estude este capítulo no WhatsApp

Peça à IA da Bíblia Fala para explicar 1 Crônicas 9, comparar traduções ou montar um estudo — tudo direto pelo WhatsApp.