1 Crônicas 4
Biblica® ní oore ọ̀fẹ́ láti lo Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde-Òní (YOR) vs NTLH
1 Àwọn ọmọ Juda:
1 São estes os descendentes de Judá: Peres, Hezrom, Carmi, Hur e Sobal.
2 Reaiah ọmọ Ṣobali ni baba Jahati, àti Jahati baba Ahumai àti Lahadi. Àwọn wọ̀nyí ni ẹ̀yà ará Sorati.
2 Sobal foi pai de Reaías, Reaías foi pai de Jaate, Jaate foi pai de Aumai e Laade. Aumai e Laade foram os antepassados dos grupos de famílias que moravam em Zora.
3 Àwọn wọ̀nyí ni àwọn ọmọ Etamu:
3 — ausente —
4 Penueli sì ni baba Gedori, àti Eseri baba Huṣa.
4 — ausente —
5 Aṣihuri baba Tekoa sì ní aya méjì, Hela àti Naara.
5 Asur, que fundou a cidade de Tecoa, teve duas esposas: Helá e Naara.
6 Naara sì bí Ahussamu, Heferi Temeni àti Haaṣtari. Àwọn wọ̀nyí sì ni àwọn ọmọ Naara.
6 Ele e Naara tiveram quatro filhos: Auzã, Héfer, Temeni e Haastari.
7 Àwọn ọmọ Hela:
7 Asur e Helá tiveram três filhos: Zerete, Isar e Etnã.
8 àti Kosi ẹni tí ó jẹ́ baba Anubu àti Sobeba àti ti àwọn ẹ̀yà Aharheli ọmọ Harumu.
8 Coz foi pai de Anube e Zobeba e foi o antepassado dos grupos de famílias que descendem de Acarel, filho de Harum.
9 Jabesi sì ní ọlá ju àwọn ẹ̀gbọ́n rẹ̀ ọkùnrin lọ. Ìyá rẹ̀ sì sọ ọ́ ní Jabesi wí pé, “Mo bí i nínú ìpọ́njú.”
9 Houve um homem chamado Jabes, que foi a pessoa mais respeitada da sua família. A sua mãe pôs nele o nome de Jabes porque ela havia sofrido muito durante o parto.
10 Jabesi sì kígbe sókè sí Ọlọ́run Israẹli wí pé, “Háà, Ìwọ yóò bùkún fún mi, ìwọ yóò sì mú agbègbè mi tóbi! Jẹ́ kí ọwọ́ rẹ kí ó wà pẹ̀lú mi kí o sì pa mi mọ́ kúrò nínú ibi; kí èmi kí ó le ní ìdáǹdè kúrò nínú ìrora.” Ọlọ́run sì gbọ́ ohùn ẹ̀bẹ̀ rẹ̀.
10 Mas Jabes orou assim ao Deus de Israel: “Ó Deus, abençoa-me e dá-me muitas terras. Fica comigo e livra-me de qualquer coisa que possa me causar dor.” E Deus atendeu a sua oração.
11 Kelubu arákùnrin Ṣuha, sì jẹ́ baba Mehiri, ẹni tí ó jẹ́ baba Eṣtoni.
11 Quelube, irmão de Suá, foi pai de um filho chamado Meir. Meir foi pai de Estom,
12 Eṣtoni sì jẹ́ baba Beti-Rafa, Pasea àti Tehina ti baba ìlú Nahaṣi. Àwọn wọ̀nyí ni ọkùnrin Reka.
12 e Estom foi pai de três filhos: Bete-Rafa, Paseia e Teína. Teína foi o fundador da cidade de Naás. Os descendentes deles moravam em Reca.
13 Àwọn ọmọ Kenasi:
13 Quenaz foi pai de dois filhos: Otoniel e Seraías. Otoniel também foi pai de dois filhos: Hatate e Meonotai.
14 Meonotai sì ni baba Ofira.
14 Meonotai foi pai de Ofrá. Seraías foi pai de Joabe, o fundador do vale dos Artesãos, onde todos os homens faziam trabalhos de artesanato.
15 Àwọn ọmọ Kalebu ọmọ Jefunne:
15 Calebe, filho de Jefoné, foi pai de três filhos: Iru, Elá e Naã. E Elá foi pai de Quenaz.
16 Àwọn ọmọ Jehaleeli:
16 Jealelel foi pai de quatro filhos: Zife, Zifa, Tiria e Asareel.
17 Àwọn ọmọ Esra:
17 Esdras foi pai de quatro filhos: Jéter, Merede, Éfer e Jalom. Merede casou com Bitia, que era filha do rei do Egito, e eles tiveram uma filha chamada Míriam e dois filhos: Samai e Isba. Isba fundou a cidade de Estemoa.
18 Aya rẹ̀ láti ẹ̀yà Juda sì bí Jaredi baba Gedori, àti Heberi baba Soko àti Jekutieli baba Sanoa. Àwọn wọ̀nyí ni àwọn ọmọ ọmọbìnrin Farao Bitia, ẹni ti Meredi ti fẹ́.
18 Merede também casou com uma mulher da tribo de Judá, e eles tiveram três filhos: Jerede, que fundou a cidade de Gedor; Héber, que fundou Socó; e Jecutiel, que fundou Zanoa.
19 Àwọn ọmọ aya Hodiah arábìnrin Nahamu,
19 Hodias casou com a irmã de Naã. Os seus descendentes fundaram o grupo de famílias de Garmi, que morava na cidade de Queila, e o grupo de famílias de Maacá, que morava em Estemoa.
20 Àwọn ọmọ Ṣimoni:
20 Simão foi pai de quatro filhos: Amnom, Rina, Ben-Hanã e Tilom. Isi foi pai de dois filhos: Zoete e Ben-Zoete.
21 Àwọn ọmọ Ṣela ọmọ Juda:
21 Selá foi um dos filhos de Judá. Um dos descendentes de Selá foi Er, que fundou a cidade de Leca; outro foi Lada, que fundou Maressa. Selá foi também o antepassado dos grupos de famílias que teciam linho e que moravam na cidade de Bete-Asbeia.
22 Jokimu, ọkùnrin Koseba, àti Joaṣi àti Sarafi, olórí ní Moabu àti Jaṣubi Lehemu. (Àkọsílẹ̀ yìí sì wà láti ìgbà àtijọ́.)
22 Foi também o antepassado de Joquim e do povo que morava na cidade de Cozeba. E também de Joás e Sarafe, que casaram com mulheres moabitas e ficaram morando em Belém. (Estes registros são antigos.)
23 Àwọn sì ni amọ̀kòkò tí ń gbé ní Netaimu àti Gedera; wọ́n sì dúró níbẹ̀ wọ́n sì ń ṣiṣẹ́ fún ọba.
23 Eles eram oleiros que trabalhavam para o rei e moravam nas cidades de Netaim e Gedera.
24 Àwọn ọmọ Simeoni:
24 Simeão foi pai de cinco filhos: Nemuel, Jamim, Jaribe, Zera e Saul.
25 Ṣallumu sì jẹ́ ọmọ Saulu, Mibsamu ọmọ rẹ̀ Miṣima ọmọ rẹ̀.
25 Saul foi pai de Salum, Salum foi pai de Mibsão, e Mibsão foi pai de Misma.
26 Àwọn ọmọ Miṣima:
26 Misma foi pai de Hamuel, Hamuel foi pai de Zacur, e Zacur foi pai de Simei.
27 Ṣimei sì ní ọmọkùnrin mẹ́rìndínlógún àti ọmọbìnrin mẹ́fà, ṣùgbọ́n àwọn ẹ̀gbọ́n rẹ̀ ọkùnrin kò ní ọmọ púpọ̀; bẹ́ẹ̀ ni àwọn ìdílé wọn kò sì pọ̀ gẹ́gẹ́ bí àwọn ènìyàn Juda.
27 Simei foi pai de dezesseis filhos e seis filhas, mas os seus parentes tiveram menos filhos do que ele, e a tribo de Simeão não cresceu tanto como a tribo de Judá.
28 Wọ́n sì ń gbé ní Beerṣeba, Molada, Hasari-Ṣuali,
28 Até o tempo do rei Davi, os descendentes de Simeão moravam nas seguintes cidades: Berseba, Molada, Hazar-Sual,
29 àti ní Biliha, àti ní Esemu, àti ní Toladi,
29 Bila, Ezém, Tolade,
30 Betueli, Horma, Siklagi,
30 Betuel, Horma, Ziclague,
31 Beti-Markaboti Hormah; Hasari Susimu, Beti-Biri àti Ṣaraimi. Àwọn wọ̀nyí ni ìlú wọn títí di ìgbà ọba Dafidi,
31 Bete-Marcabote, Hazar-Susim, Bete-Biri e Saaraim.
32 agbègbè ìlú wọn ni Etamu, Aini, Rimoni, Tokeni, Aṣani àwọn ìlú márùn-ún,
32 Eles também moravam em mais cinco cidades: Etã, Aim, Rimom, Toquém e Asã,
33 àti gbogbo ìletò wọn, tí ó wà yí ìlú náà ká, dé Baali. Àwọn wọ̀nyí ni ibùgbé wọn.
33 e nos povoados que ficavam ao seu redor, até a cidade de Baal. São essas as suas famílias e os lugares onde moravam. As suas famílias continuaram a aumentar, e por isso
34 Meṣobabu àti Jamleki,
34 — ausente —
35 Joẹli,
35 — ausente —
36 àti pẹ̀lú Elioenai, Jaakoba, Jeṣohaiah,
36 — ausente —
37 àti Sisa ọmọ Ṣifi ọmọ Alloni, ọmọ Jedaiah, ọmọ Ṣimri ọmọ Ṣemaiah.
37 — ausente —
38 Àwọn ọkùnrin tí a dárúkọ lókè yìí àwọn ni ìjòyè ìdílé wọn.
38 — ausente —
39 wọ́n sì lọ sí ojú ọ̀nà Gedori. Lọ títí dé ìlà-oòrùn àfonífojì láti wá koríko fún àwọn agbo ẹran wọn.
39 eles se espalharam para o oeste quase até Gerar e levaram as suas ovelhas para pastar no lado leste do vale onde fica aquela cidade.
40 Wọ́n sì rí koríko tútù tí ó dára ilẹ̀ náà gbòòrò ó sì ní àlàáfíà ó sì gbé jẹ́. Àwọn ọmọ Hamu ni ó ti ń gbé ibẹ̀ tẹ́lẹ̀tẹ́lẹ̀.
40 Ali eles acharam muitas pastagens num pedaço de terra espaçosa, tranquila e cheia de paz. Os descendentes de Cam haviam morado ali antes.
41 Àwọn ọkùnrin tí a kọ orúkọ rẹ̀ sókè, dé ní ọjọ́ Hesekiah ọba Juda. Wọ́n sì kọlu àwọn ará Hamu ní àgọ́ wọn àti pẹ̀lú àwọn ará Mehuni tí a rí níbẹ̀ tí ó sì pa wọ́n run pátápátá títí di òní yìí. Wọ́n sì ń gbé ní ipò wọn, nítorí pé koríko ń bẹ níbẹ̀ fún agbo ẹran wọn.
41 No tempo do rei Ezequias, de Judá, os homens cujos nomes estão escritos acima foram até Gerar e destruíram as barracas e cabanas do povo que morava ali. Eles expulsaram o povo e ficaram morando em Gerar porque ali havia bastante pasto para as suas ovelhas.
42 Ẹ̀ẹ́dẹ́gbẹ̀ta (500) nínú àwọn ará Simeoni, lábẹ́ ìdarí pẹ̀lú Pelatiah, Neariah, Refaiah àti Usieli, àwọn ọmọ Iṣi, gbógun sí àwọn òkè ìlú ti Seiri.
42 Quinhentos homens da tribo de Simeão foram para Edom, na direção leste. Os seus chefes eram os filhos de Isi: Pelatias, Nearias, Refaías e Uziel.
43 Wọ́n sì pa àwọn ará Amaleki tí ó kù, àwọn tí ó ti sálà, wọ́n sì ti ń gbé ibẹ̀ títí di òní yìí.
43 Eles mataram os amalequitas que haviam escapado com vida e estão morando ali até hoje .
Atalhos do teclado
- Capítulo anterior←
- Próximo capítulo→
- Versículo anteriork
- Próximo versículoj
- Limpar seleçãoEsc
- Esta ajuda?
Estude este capítulo no WhatsApp
Peça à IA da Bíblia Fala para explicar 1 Crônicas 4, comparar traduções ou montar um estudo — tudo direto pelo WhatsApp.