1 Crônicas 4

Biblica® ní oore ọ̀fẹ́ láti lo Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde-Òní (YOR) vs BKJ

Sair da comparação
1 Àwọn ọmọ Juda:
1 Os filhos de Judá: Perez, Hezrom, e Carmi, e Hur, e Sobal.
2 Reaiah ọmọ Ṣobali ni baba Jahati, àti Jahati baba Ahumai àti Lahadi. Àwọn wọ̀nyí ni ẹ̀yà ará Sorati.
2 E Reaías, o filho de Sobal, gerou Jaate; e Jaate gerou Aumai e Laade. Estas são as famílias dos zoratitas.
3 Àwọn wọ̀nyí ni àwọn ọmọ Etamu:
3 E estes foram do pai de Etã: Jezreel, e Isma, e Idbas; e o nome da sua irmã era Hazelelponi;
4 Penueli sì ni baba Gedori, àti Eseri baba Huṣa.
4 e Penuel, pai de Gedor; e Eser, pai de Husá. Estes foram os filhos de Hur, o primogênito de Efrata, o pai de Belém.
5 Aṣihuri baba Tekoa sì ní aya méjì, Hela àti Naara.
5 E Asur, o pai de Tecoa, tinha duas esposas: Hela e Naara.
6 Naara sì bí Ahussamu, Heferi Temeni àti Haaṣtari. Àwọn wọ̀nyí sì ni àwọn ọmọ Naara.
6 E Naara deu à luz Auzão, e Héfer, e Temeni, e Haastari. Estes foram os filhos de Naara.
7 Àwọn ọmọ Hela:
7 E os filhos de Hela foram: Zerete, e Isar e Etnã.
8 àti Kosi ẹni tí ó jẹ́ baba Anubu àti Sobeba àti ti àwọn ẹ̀yà Aharheli ọmọ Harumu.
8 E Coz gerou Anube, e Zobeba, e as famílias de Aarel, o filho de Harum.
9 Jabesi sì ní ọlá ju àwọn ẹ̀gbọ́n rẹ̀ ọkùnrin lọ. Ìyá rẹ̀ sì sọ ọ́ ní Jabesi wí pé, “Mo bí i nínú ìpọ́njú.”
9 E Jabez foi mais honrado do que os seus irmãos; e sua mãe chamou o seu nome Jabez, dizendo: Porque eu dei à luz com dores.
10 Jabesi sì kígbe sókè sí Ọlọ́run Israẹli wí pé, “Háà, Ìwọ yóò bùkún fún mi, ìwọ yóò sì mú agbègbè mi tóbi! Jẹ́ kí ọwọ́ rẹ kí ó wà pẹ̀lú mi kí o sì pa mi mọ́ kúrò nínú ibi; kí èmi kí ó le ní ìdáǹdè kúrò nínú ìrora.” Ọlọ́run sì gbọ́ ohùn ẹ̀bẹ̀ rẹ̀.
10 E Jabez invocou o Deus de Israel, dizendo: Se com a bênção me abençoares, e alargares minhas fronteiras, seja tua mão comigo e me guardes do mal, de modo que ele não me aflija! E Deus lhe concedeu aquilo que ele solicitou.
11 Kelubu arákùnrin Ṣuha, sì jẹ́ baba Mehiri, ẹni tí ó jẹ́ baba Eṣtoni.
11 E Quelube, o irmão de Suá, gerou Meir, o qual foi o pai de Estom.
12 Eṣtoni sì jẹ́ baba Beti-Rafa, Pasea àti Tehina ti baba ìlú Nahaṣi. Àwọn wọ̀nyí ni ọkùnrin Reka.
12 E Estom gerou Bete-Rafa, e Pasea, e Teína, o pai de Ir-Naás. Estes são os homens de Reca.
13 Àwọn ọmọ Kenasi:
13 E os filhos de Quenaz: Otniel e Seraías; e o filho de Otniel: Hatate.
14 Meonotai sì ni baba Ofira.
14 E Meonotai gerou Ofra, e Seraías gerou Joabe, pai do vale dos Carasins; porque eles eram artesãos.
15 Àwọn ọmọ Kalebu ọmọ Jefunne:
15 E os filhos de Calebe, o filho de Jefoné; Iru, Elá e Naã; e o filho de Elá: foi Quenaz.
16 Àwọn ọmọ Jehaleeli:
16 E os filhos de Jealelel: Zife, e Zifa, e Tiria, e Asareel.
17 Àwọn ọmọ Esra:
17 E os filhos de Ezra foram: Jéter, e Merede, e Efer, e Jalom; e ela deu à luz Miriã, e Samai, e Isbá, o pai de Estemoa.
18 Aya rẹ̀ láti ẹ̀yà Juda sì bí Jaredi baba Gedori, àti Heberi baba Soko àti Jekutieli baba Sanoa. Àwọn wọ̀nyí ni àwọn ọmọ ọmọbìnrin Farao Bitia, ẹni ti Meredi ti fẹ́.
18 E a sua esposa Judia deu à luz Jerede, o pai de Gedor, e Héber, o pai de Socó, e Jecutiel, o pai de Zanoa. E estes são os filhos de Bitia, a filha de Faraó, a qual Merede tomou.
19 Àwọn ọmọ aya Hodiah arábìnrin Nahamu,
19 E os filhos da sua esposa Hodias, a irmã de Naã; o pai de Queila, o garmita, e Estemoa, o maacatita.
20 Àwọn ọmọ Ṣimoni:
20 E os filhos de Simeão foram: Amnom, e Rina, e Ben-Hanã, e Tilom. E os filhos de Isi foram: Zoete e Ben-Zoete.
21 Àwọn ọmọ Ṣela ọmọ Juda:
21 Os filhos de Selá, o filho de Judá foram: Er, o pai de Leca, e Lada, o pai de Maressa, e as famílias da casa daqueles que trabalhavam com linho fino, da casa de Asbeia,
22 Jokimu, ọkùnrin Koseba, àti Joaṣi àti Sarafi, olórí ní Moabu àti Jaṣubi Lehemu. (Àkọsílẹ̀ yìí sì wà láti ìgbà àtijọ́.)
22 e Joquim, e os homens de Cozeba, e de Joás, e Sarafe, que tinham o domínio em Moabe, e Jasubi-Leém. E estas são coisas antigas.
23 Àwọn sì ni amọ̀kòkò tí ń gbé ní Netaimu àti Gedera; wọ́n sì dúró níbẹ̀ wọ́n sì ń ṣiṣẹ́ fún ọba.
23 Estes foram os oleiros, e aqueles que habitaram entre plantas e cercados; ali habitaram com o rei para a sua obra.
24 Àwọn ọmọ Simeoni:
24 Os filhos de Simeão foram: Nemuel, Jamim, Jaribe, Zerá, e Saul;
25 Ṣallumu sì jẹ́ ọmọ Saulu, Mibsamu ọmọ rẹ̀ Miṣima ọmọ rẹ̀.
25 Salum, seu filho; Mibsão, seu filho; Misma, seu filho.
26 Àwọn ọmọ Miṣima:
26 E os filhos de Misma: Hamuel, seu filho; Zacur, seu filho; Simei, seu filho.
27 Ṣimei sì ní ọmọkùnrin mẹ́rìndínlógún àti ọmọbìnrin mẹ́fà, ṣùgbọ́n àwọn ẹ̀gbọ́n rẹ̀ ọkùnrin kò ní ọmọ púpọ̀; bẹ́ẹ̀ ni àwọn ìdílé wọn kò sì pọ̀ gẹ́gẹ́ bí àwọn ènìyàn Juda.
27 E Simei tinha dezesseis filhos e seis filhas; mas os seus irmãos não tiveram muitos filhos, nem se multiplicou toda a família deles, como os filhos de Judá.
28 Wọ́n sì ń gbé ní Beerṣeba, Molada, Hasari-Ṣuali,
28 E eles habitaram em Berseba, e Molada, e Hazar-Sual,
29 àti ní Biliha, àti ní Esemu, àti ní Toladi,
29 e em Bila, e em Ezém, e em Tolade,
30 Betueli, Horma, Siklagi,
30 e em Betuel, e em Horma, e em Ziclague,
31 Beti-Markaboti Hormah; Hasari Susimu, Beti-Biri àti Ṣaraimi. Àwọn wọ̀nyí ni ìlú wọn títí di ìgbà ọba Dafidi,
31 e em Bete-Marcabote, e Hazar-Susim, e em Bete-Biri, e em Saaraim. Estas foram as suas cidades até o reinado de Davi.
32 agbègbè ìlú wọn ni Etamu, Aini, Rimoni, Tokeni, Aṣani àwọn ìlú márùn-ún,
32 E as suas aldeias eram: Etã, e Aim, Rimom, e Toquém, e Asã; cinco cidades,
33 àti gbogbo ìletò wọn, tí ó wà yí ìlú náà ká, dé Baali. Àwọn wọ̀nyí ni ibùgbé wọn.
33 e todas as suas aldeias que estavam ao redor destas cidades, até Baal. Estas foram as suas habitações, e a sua genealogia.
34 Meṣobabu àti Jamleki,
34 E Mesobabe, e Janleque, e Josa, o filho de Amazias,
35 Joẹli,
35 e Joel, e Jeú, o filho de Josibias, o filho de Seraías, o filho de Asiel,
36 àti pẹ̀lú Elioenai, Jaakoba, Jeṣohaiah,
36 e Elioenai e Jaacobá, e Jesoaías, e Asaías, e Adiel, e Jesimiel, e Benaia,
37 àti Sisa ọmọ Ṣifi ọmọ Alloni, ọmọ Jedaiah, ọmọ Ṣimri ọmọ Ṣemaiah.
37 e Ziza, o filho de Sifi, o filho de Alom, o filho de Jedaías, o filho de Sinri, o filho de Semaías;
38 Àwọn ọkùnrin tí a dárúkọ lókè yìí àwọn ni ìjòyè ìdílé wọn.
38 estes mencionados pelos seus nomes foram príncipes nas suas famílias; e a casa dos seus pais aumentou muitíssimo.
39 wọ́n sì lọ sí ojú ọ̀nà Gedori. Lọ títí dé ìlà-oòrùn àfonífojì láti wá koríko fún àwọn agbo ẹran wọn.
39 E eles foram para a entrada de Gedor, a saber, para o lado leste do vale, para procurar pasto para os seus rebanhos.
40 Wọ́n sì rí koríko tútù tí ó dára ilẹ̀ náà gbòòrò ó sì ní àlàáfíà ó sì gbé jẹ́. Àwọn ọmọ Hamu ni ó ti ń gbé ibẹ̀ tẹ́lẹ̀tẹ́lẹ̀.
40 E eles encontraram pasto abundante e bom, e a terra era ampla, e tranquila, e pacífica; porque os de Cam haviam habitado ali desde a antiguidade.
41 Àwọn ọkùnrin tí a kọ orúkọ rẹ̀ sókè, dé ní ọjọ́ Hesekiah ọba Juda. Wọ́n sì kọlu àwọn ará Hamu ní àgọ́ wọn àti pẹ̀lú àwọn ará Mehuni tí a rí níbẹ̀ tí ó sì pa wọ́n run pátápátá títí di òní yìí. Wọ́n sì ń gbé ní ipò wọn, nítorí pé koríko ń bẹ níbẹ̀ fún agbo ẹran wọn.
41 Estes, que estão escritos por seus nomes, vieram nos dias de Ezequias, rei de Judá, e feriram as suas tendas, e as habitações que ali foram achadas, e as destruíram completamente até este dia, e habitaram nos seus lugares; porque havia ali pasto para os seus rebanhos.
42 Ẹ̀ẹ́dẹ́gbẹ̀ta (500) nínú àwọn ará Simeoni, lábẹ́ ìdarí pẹ̀lú Pelatiah, Neariah, Refaiah àti Usieli, àwọn ọmọ Iṣi, gbógun sí àwọn òkè ìlú ti Seiri.
42 E alguns deles, a saber, dos filhos de Simeão, quinhentos homens foram ao monte Seir, tendo como seus capitães: Pelatias, e Nearias, e Refaías, e Uziel, os filhos de Isi.
43 Wọ́n sì pa àwọn ará Amaleki tí ó kù, àwọn tí ó ti sálà, wọ́n sì ti ń gbé ibẹ̀ títí di òní yìí.
43 E feriram o restante dos amalequitas que haviam escapado, e ali habitaram até este dia.

Ler em outra tradução

Comparar com outra

Estude este capítulo no WhatsApp

Peça à IA da Bíblia Fala para explicar 1 Crônicas 4, comparar traduções ou montar um estudo — tudo direto pelo WhatsApp.