1 Crônicas 23

Biblica® ní oore ọ̀fẹ́ láti lo Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde-Òní (YOR) vs NTLH

Sair da comparação
NTLH Nova Tradução na Linguagem de Hoje 2000
1 Nígbà tí Dafidi sì dàgbà, tí ó sì di arúgbó, ó sì fi Solomoni ọmọ rẹ̀ jẹ ọba lórí Israẹli.
1 Quando já estava bem velho, Davi pôs o seu filho Salomão como rei de Israel.
2 Ó sì kó gbogbo àgbàgbà Israẹli jọ, àti gẹ́gẹ́ bí àwọn àlùfáà àti àwọn ará Lefi.
2 O rei Davi reuniu todos os líderes israelitas e todos os sacerdotes e levitas .
3 Àwọn ọmọ Lefi láti ọgbọ̀n ọdún tàbí jù bẹ́ẹ̀ lọ ni wọ́n kà àpapọ̀ iye àwọn ọkùnrin wọn sì jẹ́ ẹgbàá mọ́kàndínlógún (38,000).
3 Foram contados os levitas de trinta anos para cima, e o total foi de trinta e oito mil homens.
4 Dafidi sì wí pe, ní ti èyí, ẹgbàá méjìlá (24,000) ni kí wọn jẹ́ alábojútó iṣẹ́ ilé fún Olúwa àti ẹgbẹ̀rún mẹ́fà (6,000) ni kí ó ṣe olórí àti onídàájọ́.
4 O rei nomeou vinte e quatro mil deles para administrarem o trabalho de construção do Templo. Nomeou também seis mil para fazerem a escrita e resolverem os problemas que surgissem.
5 Ẹgbàajì (4,000) ni kí ó jẹ́ olùtọ́jú ẹnu-ọ̀nà àti ẹgbàajì (4,000) ni kí o sì jẹ́ ẹni ti yóò máa yin Olúwa pẹ̀lú ohun èlò orin, mo ti ṣe èyí fún ìdí pàtàkì yìí.
5 E ainda nomeou quatro mil para serem guardas dos portões e quatro mil para louvarem o Senhor com os instrumentos que o próprio rei tinha mandado fazer para isso.
6 Dafidi sì pín àwọn ọmọ Lefi sí ẹgbẹgbẹ́ láàrín àwọn ọmọ Lefi: Gerṣoni, Kohati àti Merari.
6 Davi dividiu os levitas de acordo com os seus três grupos de famílias, que descendiam de Gérson, Coate e Merari.
7 Àwọn tí ó jẹ́ ọmọ Gerṣoni:
7 Gérson foi pai de dois filhos: Ladã e Simei.
8 Àwọn ọmọ Laadani
8 Ladã foi pai de três filhos: Jeiel, Zetã e Joel,
9 Àwọn ọmọ Ṣimei:
9 que foram os chefes dos grupos de famílias descendentes de Ladã. (Simei foi pai de três filhos: Selomite, Haziel e Harã.)
10 Àti ọmọ Ṣimei:
10 — ausente —
11 Jahati sì ni alákọ́kọ́ Sinah sì ni ẹlẹ́ẹ̀kejì, ṣùgbọ́n Jeuṣi àti Beriah kò ní àwọn ọmọ púpọ̀; bẹ́ẹ̀ ni wọ́n sì ka ara wọn sí ìdílé kan pẹ̀lú ìfilé lọ́wọ́ kan.
11 — ausente —
12 Àwọn ọmọ Kohati:
12 Coate foi pai de quatro filhos: Anrão, Isar, Hebrom e Uziel.
13 Àwọn ọmọ Amramu.
13 Anrão, o filho mais velho, foi o pai de Arão e Moisés. (Arão e os seus descendentes foram separados para sempre a fim de tomar conta dos objetos sagrados, para queimarem incenso na adoração a Deus, o Senhor , para o servirem e para abençoarem o povo em seu nome.
14 Àwọn ọmọ Mose ènìyàn Ọlọ́run ni wọ́n kà gẹ́gẹ́ bí apá kan ẹ̀yà Lefi.
14 Mas os filhos de Moisés, homem de Deus, foram contados entre os levitas.)
15 Àwọn ọmọ Mose:
15 Moisés foi pai de dois filhos: Gérson e Eliézer.
16 Àwọn ọmọ Gerṣomu:
16 O líder dos filhos de Gérson foi Sebuel.
17 Àwọn ọmọ Elieseri:
17 Eliézer foi pai de somente um filho, chamado Reabias, mas Reabias teve muitos descendentes.
18 Àwọn ọmọ Isari:
18 Isar, o segundo filho de Coate, foi pai de um filho chamado Selomite, que foi o chefe do seu grupo de famílias.
19 Àwọn ọmọ Hebroni:
19 Hebrom, o terceiro filho de Coate, foi pai de quatro filhos: Jerias, Amariá, Jaaziel e Jecameão.
20 Àwọn ọmọ Usieli:
20 Uziel, o quarto filho de Coate, foi pai de dois filhos: Mica e Issias.
21 Àwọn ọmọ Merari:
21 Merari foi pai de dois filhos: Mali e Musi. Mali também foi pai de dois filhos: Eleazar e Quis,
22 Eleasari sì kú pẹ̀lú àìní àwọn ọmọkùnrin: Ó ní ọmọbìnrin nìkan. Àwọn ọmọ ẹ̀gbọ́n, àwọn ọmọ Kiṣi, sì fẹ́ wọn.
22 mas Eleazar morreu sem deixar nenhum filho homem; só deixou filhas. Estas casaram com os primos, os filhos de Quis.
23 Àwọn ọmọ Muṣi:
23 Musi, o segundo filho de Merari, foi pai de três filhos: Mali, Éder e Jerimote.
24 Àwọn wọ̀nyí sì ni ọmọ Lefi bí ìdílé wọn. Olórí ìdílé gẹ́gẹ́ bí wọ́n ti fi orúkọ sílẹ̀ lábẹ́ orúkọ wọn, ó sì kà wọn ní ẹyọ kọ̀ọ̀kan, wí pé, àwọn òṣìṣẹ́ tí ó jẹ́ ogún ọdún tàbí jù bẹ́ẹ̀ lọ tí ń ṣiṣẹ́ ìsìn nínú ilé Olúwa.
24 Foram estes os descendentes de Levi, por famílias e por grupos de famílias, registrados nome por nome. Todos os seus descendentes da idade de vinte anos para cima eram responsáveis pelos serviços do Templo de Deus, o Senhor .
25 Nítorí pé Dafidi ti sọ pé, “Níwọ̀n ìgbà tí Olúwa Ọlọ́run Israẹli, ti fi ìsinmi fún àwọn ènìyàn tí ó kù tí sì ń gbé Jerusalẹmu títí láéláé,
25 Davi disse: — O
26 àwọn ọmọ Lefi kò sì tún ru àgọ́ tàbí ọ̀kankan lára àwọn ohun èlò tí wọ́n ń lò níbi ìsìn rẹ̀.”
26 Por isso, os levitas não precisam mais carregar a Tenda da Presença de Deus nem os objetos usados na adoração.
27 Gẹ́gẹ́ bí ọ̀rọ̀ ìkẹyìn Dafidi sí, àwọn ọmọ Lefi, wọ́n sì kà wọ́n, bẹ̀rẹ̀ láti orí àwọn ọmọ ogún ọdún tàbí jù bẹ́ẹ̀ lọ.
27 Assim, de acordo com as últimas ordens de Davi, quando completavam vinte anos de idade, os levitas eram registrados para o serviço.
28 Iṣẹ́ àwọn ọmọ Lefi ni láti ran àwọn ọmọ Aaroni lọ́wọ́ nínú iṣẹ́ wọn fún ti ilé Olúwa: láti wà lábẹ́ ìkáwọ́ agbára ìlú, àti ẹ̀gbẹ́ ilé, àti ìwẹ̀nùmọ́ ti gbogbo ohun ìyàsọ́tọ̀ àti ṣíṣe ohun tí í ṣe iṣẹ́ ìsìn nínú ilé Olúwa.
28 Então eram escalados para ajudar os sacerdotes descendentes de Arão na adoração no Templo, para cuidar dos seus pátios e salas e para conservar puro tudo o que era sagrado;
29 Wọ́n sì wà ní ìkáwọ́ àkàrà tí wọ́n mú jáde láti orí tábìlì, àti ìyẹ̀fun fún ẹbọ, àti àkàrà aláìwú, àti fún púpọ̀ àti èyí tí a pòpọ̀, àti gbogbo onírúurú ìwọ̀n àti wíwọ̀n àti òsùwọ̀n.
29 para serem responsáveis pelos pães oferecidos a Deus, pela farinha de trigo usada nas ofertas, pelos pães achatados feitos sem fermento, pelas ofertas assadas em frigideiras e pela farinha de trigo misturada com azeite. Eram também encarregados de pesar e medir as ofertas para o Templo;
30 Wọ́n sì gbọdọ̀ dúró ní gbogbo òwúrọ̀ láti dúpẹ́ àti láti yin Olúwa. Wọ́n sì gbọdọ̀ ṣe irú kan náà ní àṣálẹ́.
30 de louvar e glorificar o Senhor todas as manhãs e todas as tardes
31 Àti láti rú ẹbọ sísun fún Olúwa ní ọjọ́ ìsinmi àti ní àsìkò oṣù tuntun àti ní àjọ̀dún tí a yàn. Wọ́n gbọdọ̀ sìn níwájú Olúwa lójoojúmọ́ ní iye tó yẹ àti ní ọ̀nà tí a ti pàṣẹ fún wọn.
31 e sempre que as ofertas a Deus eram queimadas no sábado, na Festa da Lua Nova e em outras festas. Foram feitas regras a respeito do número de levitas escalados de cada vez para fazerem esse trabalho. Eles ficaram encarregados para sempre da adoração ao Senhor .
32 Bẹ́ẹ̀ ni nígbà náà, àwọn ọmọ Lefi gbé ìgbékalẹ̀ jáde fún ìpàdé àgọ́, fún Ibi Mímọ́ àti, lábẹ́ àwọn arákùnrin àwọn ọmọ Aaroni fún ìsìn ilé Olúwa.
32 Eles receberam a responsabilidade de cuidar da Tenda da Presença de Deus e do Templo e de ajudar os seus parentes, os sacerdotes descendentes de Arão, na adoração no Templo.

Ler em outra tradução

Comparar com outra

Estude este capítulo no WhatsApp

Peça à IA da Bíblia Fala para explicar 1 Crônicas 23, comparar traduções ou montar um estudo — tudo direto pelo WhatsApp.