1 Crônicas 23

Biblica® ní oore ọ̀fẹ́ láti lo Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde-Òní (YOR) vs BKJ

Sair da comparação
1 Nígbà tí Dafidi sì dàgbà, tí ó sì di arúgbó, ó sì fi Solomoni ọmọ rẹ̀ jẹ ọba lórí Israẹli.
1 Assim, quando Davi era velho e cheio de dias, ele fez Salomão, o seu filho, rei sobre Israel.
2 Ó sì kó gbogbo àgbàgbà Israẹli jọ, àti gẹ́gẹ́ bí àwọn àlùfáà àti àwọn ará Lefi.
2 E ele reuniu todos os príncipes de Israel, com os sacerdotes e os levitas.
3 Àwọn ọmọ Lefi láti ọgbọ̀n ọdún tàbí jù bẹ́ẹ̀ lọ ni wọ́n kà àpapọ̀ iye àwọn ọkùnrin wọn sì jẹ́ ẹgbàá mọ́kàndínlógún (38,000).
3 Ora, os levitas foram enumerados de trinta anos para cima; e o seu número, segundo seus cabeças, homem por homem, foi trinta e oito mil.
4 Dafidi sì wí pe, ní ti èyí, ẹgbàá méjìlá (24,000) ni kí wọn jẹ́ alábojútó iṣẹ́ ilé fún Olúwa àti ẹgbẹ̀rún mẹ́fà (6,000) ni kí ó ṣe olórí àti onídàájọ́.
4 Dos quais, vinte e quatro mil foram colocados à frente do trabalho da casa do SENHOR; e seis mil foram oficiais e juízes.
5 Ẹgbàajì (4,000) ni kí ó jẹ́ olùtọ́jú ẹnu-ọ̀nà àti ẹgbàajì (4,000) ni kí o sì jẹ́ ẹni ti yóò máa yin Olúwa pẹ̀lú ohun èlò orin, mo ti ṣe èyí fún ìdí pàtàkì yìí.
5 Além disso, quatro mil foram porteiros; e quatro mil louvaram ao SENHOR com os instrumentos que eu fiz, disse Davi, para com eles louvar.
6 Dafidi sì pín àwọn ọmọ Lefi sí ẹgbẹgbẹ́ láàrín àwọn ọmọ Lefi: Gerṣoni, Kohati àti Merari.
6 E Davi os dividiu em classes entre os filhos de Levi, a saber: Gérson, Coate e Merari.
7 Àwọn tí ó jẹ́ ọmọ Gerṣoni:
7 Dos Gersonitas foram: Ladã e Simei.
8 Àwọn ọmọ Laadani
8 Os filhos de Ladã: o chefe foi Jeiel, e Zetã, e Joel, três.
9 Àwọn ọmọ Ṣimei:
9 Os filhos de Simei: Selomite, e Haziel, e Harã, três. Estes foram os chefes dos pais de Ladã.
10 Àti ọmọ Ṣimei:
10 E os filhos de Simei foram: Jaate, e Ziza e Jeús, e Berias. Estes quatro foram os filhos de Simei.
11 Jahati sì ni alákọ́kọ́ Sinah sì ni ẹlẹ́ẹ̀kejì, ṣùgbọ́n Jeuṣi àti Beriah kò ní àwọn ọmọ púpọ̀; bẹ́ẹ̀ ni wọ́n sì ka ara wọn sí ìdílé kan pẹ̀lú ìfilé lọ́wọ́ kan.
11 E Jaate foi o chefe, e Ziza, o segundo; mas Jeús e Berias não tiveram muitos filhos; portanto, eles estavam em uma apuração, de acordo com a casa dos seus pais.
12 Àwọn ọmọ Kohati:
12 E os filhos de Coate: Anrão, Isar, e Hebrom, e Uziel, quatro.
13 Àwọn ọmọ Amramu.
13 Os filhos de Anrão: Arão, e Moisés; e Arão foi separado para que santificasse as coisas mais sagradas, ele e os seus filhos, para sempre, para queimar incenso diante do SENHOR, para ministrar a ele, e para bendizer o seu nome para sempre.
14 Àwọn ọmọ Mose ènìyàn Ọlọ́run ni wọ́n kà gẹ́gẹ́ bí apá kan ẹ̀yà Lefi.
14 Ora, acerca de Moisés, o homem de Deus, os seus filhos foram nomeados da tribo de Levi.
15 Àwọn ọmọ Mose:
15 Os filhos de Moisés foram: Gérson, e Eliézer.
16 Àwọn ọmọ Gerṣomu:
16 Dos filhos de Gérson: Sebuel era o chefe.
17 Àwọn ọmọ Elieseri:
17 E os filhos de Eliézer foram: Reabias, o chefe. E Eliézer não teve outros filhos; porém os filhos de Reabias foram muitíssimos.
18 Àwọn ọmọ Isari:
18 Dos filhos de Isar: Selomite, o chefe.
19 Àwọn ọmọ Hebroni:
19 Dos filhos de Hebrom: Jerias, o primeiro; Amarias, o segundo; Jaaziel, o terceiro, e Jecameão, o quarto.
20 Àwọn ọmọ Usieli:
20 Dos filhos de Uziel: Mica, o primeiro, e Issias, o segundo.
21 Àwọn ọmọ Merari:
21 Os filhos de Merari: Mali e Musi. Os filhos de Mali: Eleazar, e Quis.
22 Eleasari sì kú pẹ̀lú àìní àwọn ọmọkùnrin: Ó ní ọmọbìnrin nìkan. Àwọn ọmọ ẹ̀gbọ́n, àwọn ọmọ Kiṣi, sì fẹ́ wọn.
22 E Eleazar morreu, e não teve filhos, mas filhas; e os seus irmãos, os filhos de Quis, tomaram-nas.
23 Àwọn ọmọ Muṣi:
23 Os filhos de Musi: Mali, e Éder, e Jerimote, três.
24 Àwọn wọ̀nyí sì ni ọmọ Lefi bí ìdílé wọn. Olórí ìdílé gẹ́gẹ́ bí wọ́n ti fi orúkọ sílẹ̀ lábẹ́ orúkọ wọn, ó sì kà wọn ní ẹyọ kọ̀ọ̀kan, wí pé, àwọn òṣìṣẹ́ tí ó jẹ́ ogún ọdún tàbí jù bẹ́ẹ̀ lọ tí ń ṣiṣẹ́ ìsìn nínú ilé Olúwa.
24 Estes foram os filhos de Levi, segundo a casa dos seus pais, a saber: os chefes dos pais, segundo o número dos seus nomes, por suas cabeças; que faziam a obra para o serviço da casa do SENHOR, da idade de vinte anos para cima.
25 Nítorí pé Dafidi ti sọ pé, “Níwọ̀n ìgbà tí Olúwa Ọlọ́run Israẹli, ti fi ìsinmi fún àwọn ènìyàn tí ó kù tí sì ń gbé Jerusalẹmu títí láéláé,
25 Porque Davi disse: O SENHOR Deus de Israel tem dado descanso para o seu povo, para que ele possa habitar em Jerusalém para sempre;
26 àwọn ọmọ Lefi kò sì tún ru àgọ́ tàbí ọ̀kankan lára àwọn ohun èlò tí wọ́n ń lò níbi ìsìn rẹ̀.”
26 e também para os levitas; eles não carregarão mais o tabernáculo, nem quaisquer dos seus vasos para o seu serviço.
27 Gẹ́gẹ́ bí ọ̀rọ̀ ìkẹyìn Dafidi sí, àwọn ọmọ Lefi, wọ́n sì kà wọ́n, bẹ̀rẹ̀ láti orí àwọn ọmọ ogún ọdún tàbí jù bẹ́ẹ̀ lọ.
27 Porque, pelas últimas palavras de Davi, os levitas foram contados de vinte anos de idade para cima;
28 Iṣẹ́ àwọn ọmọ Lefi ni láti ran àwọn ọmọ Aaroni lọ́wọ́ nínú iṣẹ́ wọn fún ti ilé Olúwa: láti wà lábẹ́ ìkáwọ́ agbára ìlú, àti ẹ̀gbẹ́ ilé, àti ìwẹ̀nùmọ́ ti gbogbo ohun ìyàsọ́tọ̀ àti ṣíṣe ohun tí í ṣe iṣẹ́ ìsìn nínú ilé Olúwa.
28 porque o seu ofício era servir aos filhos de Arão no serviço da casa do SENHOR, nos átrios, e nas câmaras, e na purificação de todas as coisas santas, e no trabalho do serviço da casa de Deus;
29 Wọ́n sì wà ní ìkáwọ́ àkàrà tí wọ́n mú jáde láti orí tábìlì, àti ìyẹ̀fun fún ẹbọ, àti àkàrà aláìwú, àti fún púpọ̀ àti èyí tí a pòpọ̀, àti gbogbo onírúurú ìwọ̀n àti wíwọ̀n àti òsùwọ̀n.
29 tanto no pão da proposição, como na flor farinha para a oferta de carne, e para os bolos ázimos, e para aquilo que é assado na panela, e para aquilo que é frito, e para todas as formas de medida e tamanho;
30 Wọ́n sì gbọdọ̀ dúró ní gbogbo òwúrọ̀ láti dúpẹ́ àti láti yin Olúwa. Wọ́n sì gbọdọ̀ ṣe irú kan náà ní àṣálẹ́.
30 e para estarem cada manhã em pé para agradecer e louvar ao SENHOR, e de modo semelhante ao anoitecer;
31 Àti láti rú ẹbọ sísun fún Olúwa ní ọjọ́ ìsinmi àti ní àsìkò oṣù tuntun àti ní àjọ̀dún tí a yàn. Wọ́n gbọdọ̀ sìn níwájú Olúwa lójoojúmọ́ ní iye tó yẹ àti ní ọ̀nà tí a ti pàṣẹ fún wọn.
31 e para oferecerem todos os sacrifícios queimados ao SENHOR nos shabats, nas luas novas, e nas festas marcadas, pelo número, segundo a ordem que lhes foi comandada, continuamente, diante do SENHOR;
32 Bẹ́ẹ̀ ni nígbà náà, àwọn ọmọ Lefi gbé ìgbékalẹ̀ jáde fún ìpàdé àgọ́, fún Ibi Mímọ́ àti, lábẹ́ àwọn arákùnrin àwọn ọmọ Aaroni fún ìsìn ilé Olúwa.
32 e para que eles cumpram a incumbência do tabernáculo da congregação, e a incumbência do lugar santo, e a incumbência dos filhos de Arão, os seus irmãos, no serviço da casa do SENHOR.

Ler em outra tradução

Comparar com outra

Estude este capítulo no WhatsApp

Peça à IA da Bíblia Fala para explicar 1 Crônicas 23, comparar traduções ou montar um estudo — tudo direto pelo WhatsApp.