1 Crônicas 12

Biblica® ní oore ọ̀fẹ́ láti lo Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde-Òní (YOR) vs BKJ

Sair da comparação
1 Àwọn wọ̀nyí ni ọkùnrin tí ó wá sí ọ̀dọ̀ Dafidi ní Siklagi, nígbà tí ó sá kúrò níwájú Saulu ọmọ Kiṣi (wọ́n wà lára àwọn jagunjagun ẹni tí ó ràn án lọ́wọ́ láti ibi ìjà.
1 Ora, estes são os que vieram até Davi, em Ziclague, enquanto ele ainda se mantinha enclausurado por causa de Saul, o filho de Quis; e eles estavam entre os homens valentes, ajudadores da guerra.
2 Wọ́n sì mú wọn pẹ̀lú ìtẹríba wọ́n sì lágbára láti ta ọfà tàbí láti ta kànnàkànnà òkúta ní ọwọ́ òsì tàbí ní ọwọ́ ọ̀tún, wọ́n sì jẹ́ ìbátan ọkùnrin Saulu láti ẹ̀yà Benjamini):
2 Eles estavam armados com arcos, e podiam usar tanto a mão direita, como a esquerda para lançar pedras e atirar flechas com arco, eram dos irmãos de Saul de Benjamim.
3 Ahieseri olórí wọn àti Joaṣi àwọn ọmọ Ṣemaah ará Gibeah:
3 O chefe era Aiezer, depois Joás, os filhos de Semaá; o gibeatita; e Jeziel, e Pelete, os filhos de Azmavete; e Beraca, e Jeú, o anatotita;
4 Àti Iṣmaiah ará Gibeoni, ọkùnrin alágbára kan lára àwọn ọgbọ̀n ẹni tí ó jẹ́ olórí nínú àwọn ọgbọ̀n;
4 e Ismaías, o gibeonita, um homem poderoso entre os trinta e sobre os trinta; e Jeremias, e Jaaziel, e Joanã, e Jozabade, o gederatita;
5 Elusai, Jerimoti, Bealiah, Ṣemariah àti Ṣefatia ará Harufiti;
5 Eluzai, e Jerimote, e Bealias, e Semarias, e Sefatias, o harufita;
6 Elkana, Iṣiah, Asareeli, Joeseri àti Jaṣobeamu ará Kora;
6 Elcana, e Issias, e Azarel, e Joezer, e Jasobeão, os coraítas;
7 àti Joẹla, àti Sebadiah àwọn ọmọ Jerohamu láti Gedori.
7 e Joela, e Zebadias, os filhos de Jeroão, de Gedor.
8 Díẹ̀ lára àwọn ará Gadi yà sọ́dọ̀ Dafidi ní ibi gíga ní aginjù. Wọ́n sì jẹ́ onígboyà ológun tí ó múra fún ogun tí ó sì lágbára láti di asà àti ẹṣin mú. Ojú wọn sì dàbí ojú kìnnìún, wọ́n sì yára bí àgbọ̀nrín lórí àwọn òkè.
8 Os gaditas também foram juntar-se a Davi na fortaleza, no deserto, homens de força, e homens de guerra, aptos para a batalha, que eram capazes de empunhar escudo e broquel, cujas faces eram como as faces de leões, e eram tão ágeis como os cabritos sobre os montes:
9 Eseri sì jẹ́ ìjòyè,
9 Eser, o primeiro; Obadias, o segundo; Eliabe, o terceiro;
10 Miṣimana ẹlẹ́ẹ̀kẹrin, Jeremiah ẹlẹ́ẹ̀karùnún
10 Mismana, o quarto; Jeremias, o quinto;
11 Attai ẹlẹ́ẹ̀kẹfà, Elieli èkeje,
11 Atai, o sexto; Eliel, o sétimo;
12 Johanani ẹlẹ́ẹ̀kẹjọ Elsabadi ẹlẹ́ẹ̀kẹsàn-án
12 Joanã, o oitavo; Elzabade, o nono;
13 Jeremiah ẹlẹ́ẹ̀kẹwàá àti Makbannai ẹlẹ́ẹ̀kọkànlá.
13 Jeremias, o décimo; Macbanai, o undécimo;
14 Àwọn ará Gadi wọ́n sì jẹ́ olórí ogun; ẹni tí ó kéré jù sì jẹ́ àpapọ̀ ọgọ́rùn-ún, àti fún ẹni tí ó pọ̀jù fún ẹgbẹ̀rún (1,000).
14 estes foram dos filhos de Gade, capitães do exército; um dos menores esteve sobre uma centúria, e o maior sobre um mil.
15 Àwọn ni ẹni tí ó rékọjá Jordani ní oṣù àkọ́kọ́ nígbà tí ó kún bo gbogbo bèbè rẹ̀, wọ́n sì lé gbogbo àwọn tí ó ń gbé nínú àfonífojì, lọ sí ìlà-oòrùn àti níhà ìwọ̀-oòrùn.
15 Estes são aqueles que atravessaram o Jordão no primeiro mês, quando ele tinha alagado todas as suas margens; e afugentaram todos os dos vales, tanto na direção leste, como na direção oeste.
16 Ìyókù ará Benjamini àti àwọn díẹ̀ ọkùnrin láti Juda lọ sí ọ̀dọ̀ Dafidi ní ibi gíga.
16 Alguns dos filhos de Benjamim e de Judá vieram a Davi, ao lugar forte.
17 Dafidi sì lọ láti lọ pàdé wọn ó sì wí fún wọn pé, “Tí ẹ bá wá sọ́dọ̀ mi lálàáfíà, láti ràn mí lọ́wọ́ mo ṣetán láti mú un yín wà ní ìṣọ̀kan pẹ̀lú mi ṣùgbọ́n tí ẹ bá wá láti dá mi sí fún àwọn ọ̀tá mi nígbà tí ọwọ́ mi bá mọ́ kúrò nínú ìwà agbára, kí Ọlọ́run àwọn baba wa kí ó sì ri kí ó sì ṣe ìdájọ́.”
17 E Davi saiu para se encontrar com eles, e lhes falou, dizendo: Se vós viestes em paz até mim para me ajudar, o meu coração estará ligado a vós; mas se viestes para me traíres diante dos meus inimigos, vendo que não há erro nas minhas mãos, o Deus dos nossos pais olhe sobre isto, e o repreenda.
18 Nígbà náà Ẹ̀mí Mímọ́ wa sórí Amasai ìjòyè àwọn ọgbọ̀n, ó sì wí pé,
18 Então, o Espírito veio sobre Amasai, que era chefe dos capitães, e ele disse: Somos teus, ó Davi, e contigo estamos, ó filho de Jessé! Paz, paz seja contigo, e paz seja com os teus ajudadores; porque o teu Deus te ajuda. Então, Davi os recebeu, e fez deles capitães das tropas.
19 Díẹ̀ nínú àwọn ọkùnrin Manase sì yà sí ọ̀dọ̀ Dafidi nígbà tí ó lọ pẹ̀lú àwọn ará Filistini láti bá Saulu jà. (Òun àti àwọn ọkùnrin rẹ̀ wọn kò sì ran ará Filistini lọ́wọ́ nítorí, lẹ́yìn tiwọn sọ̀rọ̀ papọ̀, àwọn olórí wọn rán wọn jáde, wọ́n sì wí pé, “Yóò jẹ́ ìparun fún wa tí ó bá padà tọ ọ̀gá rẹ̀ Saulu lọ.”)
19 E ali se prostraram alguns de Manassés para Davi, quando ele veio com os filisteus para a batalha contra Saul; mas eles não lhes ajudaram; porque os senhores dos filisteus, mediante conselho, o repeliram, dizendo: Ele passará para o lado do seu mestre Saul, com perigo de nossas cabeças.
20 Nígbà tí Dafidi lọ sí Siklagi, àwọn wọ̀nyí ni ọkùnrin ti Manase ẹni tí ó sì yà sọ́dọ̀ rẹ̀. Adina, Josabadi, Jediaeli, Mikaeli, Josabadi, Elihu àti Siletai, àwọn olórí ìrẹ́pọ̀ ti ẹgbẹẹgbẹ̀rún ní Manase.
20 Enquanto ele seguia para Ziclague, prostraram-se ali diante dele, de Manassés: Adna, e Jozadabe, e Jediael, e Micael, Jozabade, e Eliú, e Ziletai, capitães dos milhares que eram de Manassés.
21 Wọ́n sì ran Dafidi lọ́wọ́ lórí ẹgbẹ́ ogun náà, nítorí gbogbo wọn ni akọni ènìyàn àwọn sì tún ni olórí nínú àwọn ọmọ-ogun rẹ̀.
21 E eles ajudaram Davi contra o bando dos salteadores; porque eles eram todos homens fortes e valentes, e eram capitães no exército.
22 Ọjọ́ dé ọjọ́ ni àwọn ọkùnrin wá láti ran Dafidi lọ́wọ́, títí tí ó fi ní àwọn ológun ńlá, bí ogun Ọlọ́run.
22 Porque naquele tempo, dia a dia, vinham a Davi para o ajudar, até que este foi um grande exército, como o exército de Deus.
23 Àwọn wọ̀nyí sì ni iye ọkùnrin tí ó ti di ìhámọ́ra fún ogun àwọn ẹni tí ó wá sọ́dọ̀ Dafidi ní Hebroni láti yí ìjọba Dafidi padà sí ọ̀dọ̀ rẹ̀, gẹ́gẹ́ bí Olúwa ti sọ.
23 E estes são os números dos chefes que estavam prontamente armados para a guerra, e vieram para Davi em Hebrom, para transferir o reino de Saul para ele, de acordo com a palavra do SENHOR.
24 Ọkùnrin Juda, tí o ń gbé asà àti ọ̀kọ̀, ẹgbàáta lé lẹ́gbẹ̀rin (6,800) tí ó ti di ìhámọ́ra fún ogun.
24 Os filhos de Judá, que empunhavam escudo e lança eram seis mil e oitocentos, prontamente armados para a guerra.
25 Àwọn ọkùnrin Simeoni, akọni tó mú fún ogun sì jẹ́ ẹ̀ẹ́dẹ́gbàárin ó lé ọgọ́rùn-ún (7,100);
25 Dos filhos de Simeão, homens fortes e valentes; sete mil e cem.
26 àwọn ọkùnrin Lefi ẹgbàajì ó le ẹgbẹ̀ta (4,600),
26 Dos filhos de Levi, quatro mil e seiscentos.
27 pẹ̀lú Jehoiada, olórí ìdílé Aaroni pẹ̀lú ẹgbẹ̀rún mẹ́ta ó lé ẹ̀ẹ́dẹ́gbẹ̀rin (3,700) ènìyàn,
27 E Joiada foi o líder dos aronitas, e com ele estavam três mil e setecentos;
28 àti Sadoku akọni ọ̀dọ́mọkùnrin, pẹ̀lú àwọn méjìlélógún ìjòyè láti ọ̀dọ̀ àwọn ìdílé rẹ̀;
28 e Zadoque, um jovem forte e valente, e da casa do seu pai vinte e dois capitães.
29 àwọn arákùnrin Benjamini ìbátan ọkùnrin Saulu ẹgbẹ̀rún mẹ́ta (3,000), ọ̀pọ̀ nínú àwọn ẹni tí ó si kù ní olóòtítọ́ sí ilé Saulu títí di ìgbà náà;
29 E dos filhos de Benjamim, a parentela de Saul, três mil; porque até aquele momento a maior parte deles havia mantido a guarda da casa de Saul.
30 àwọn arákùnrin Efraimu, ògbójú akọni, ènìyàn Ọlọ́run ni wọ́n nílé baba wọn ogún ẹgbẹ̀rún ó le ẹgbẹ̀rin (20,800);
30 E dos filhos de Efraim, vinte mil e oitocentos, homens fortes e valentes, afamados por toda a casa dos seus pais.
31 àwọn ọkùnrin nínú ààbọ̀ ẹ̀yà Manase, tí a yàn nípa orúkọ láti wá àti láti yan Dafidi gẹ́gẹ́ bí ọba, ẹgbàá mẹ́sàn (18,000).
31 E da meia tribo de Manassés, dezoito mil, os quais foram designados por nome, para virem fazer de Davi rei.
32 Àti ní ti àwọn ọmọ Isakari, àwọn ẹni tí ó ní òye àkókò, láti mọ ohun tí Israẹli ìbá máa ṣe; olórí wọn jẹ́ ìgbà; àti gbogbo àwọn ìbátan wọn ń bẹ ní ìkáwọ́ wọn.
32 E dos filhos de Issacar, os quais eram homens que tinham entendimento dos tempos, para saber o que Israel deveria fazer; os cabeças deles eram duzentos; e todos os seus irmãos estavam sob o seu comando.
33 Àwọn ọkùnrin Sebuluni, àti àwọn jagunjagun tí ó ti nípa ogun múra fún ogun pẹ̀lú oríṣìíríṣìí ohun èlò ìjà, láti ran Dafidi lọ́wọ́ pẹ̀lú àwọn tí kò fi iyèméjì ṣe ìjólóòótọ́ wọn jẹ́ ẹgbàá mẹ́ẹ̀ẹ́dọ́gbọ̀n (50,000).
33 De Zebulom, os que saíam para a batalha, peritos na guerra, com todas as armas de guerra, cinquenta mil, os quais conseguiam ordenar a batalha; eles não eram de duplo coração.
34 Àwọn ọkùnrin Naftali, ẹgbẹ̀rún (1,000) ìjòyè àpapọ̀ pẹ̀lú ẹgbàá méjìdínlógún (36,000). Ọkùnrin tí wọ́n gbé asà àti ọ̀kọ̀ wọn.
34 E de Naftali, mil capitães, e com eles, com escudo e lança, trinta e sete mil.
35 Àwọn ọkùnrin Dani, tí wọ́n ṣetán fún ogun ẹgbàá mẹ́tàlá (28,600).
35 E, dos danitas, peritos em guerra, vinte e oito mil e seiscentos.
36 Àwọn ọkùnrin Aṣeri, àwọn tí ó ti ní ìmọ̀ ogun múra fún ogun ọ̀kẹ́ méjì (40,000).
36 E de Aser, os tais que saíam para a batalha, peritos em guerra, quarenta mil.
37 Láti ìlà-oòrùn Jordani, ọkùnrin Reubeni, Gadi, àti ìdajì ẹ̀yà Manase, dìmọ́ra pẹ̀lú gbogbo onírúurú ohun èlò ìjà ọ̀kẹ́ mẹ́fà (120,000).
37 E, no outro lado do Jordão, dos rubenitas, e dos gaditas, e da meia tribo de Manassés, com toda espécie de instrumentos de guerra para a batalha; cento e vinte mil.
38 Gbogbo èyí ni àwọn ọkùnrin ológun tí ó fi ara wọn fún ogun láti ṣe iṣẹ́ fún nínú ẹgbẹ́.
38 Todos estes homens de guerra, que conseguiam ordenar a batalha, vieram com um coração perfeito para Hebrom, para fazer de Davi rei sobre todo o Israel; e também todo o restante de Israel era um só coração para fazer de Davi rei.
39 Àwọn ọkùnrin náà lo ọjọ́ mẹ́ta níbẹ̀ pẹ̀lú Dafidi, wọ́n jẹ, wọ́n sì ń mu, nítorí ìdílé wọn ti pèsè oúnjẹ fún wọn.
39 E ali eles estiveram com Davi três dias, comendo e bebendo; porque os seus irmãos lhes tinham preparado.
40 Àwọn aládùúgbò láti ọ̀nà jíjìn gẹ́gẹ́ bí Isakari, Sebuluni àti Naftali gbé oúnjẹ wá lórí kẹ́tẹ́kẹ́tẹ́, lórí ràkunmí, àti lórí ìbáaka àti lórí màlúù, àní oúnjẹ ti ìyẹ̀fun, èso àjàrà gbígbẹ, èso ọ̀pọ̀tọ́, àkàrà dídùn, ọtí wáìnì, òróró, màlúù àti àgùntàn, nítorí ọ̀pọ̀lọpọ̀ ayọ̀ wà ní Israẹli.
40 Além disso, aqueles que lhes estavam próximos, a saber, de Issacar e Zebulom e Naftali, trouxeram pão sobre jumentos, e sobre camelos, e sobre mulas, e sobre bois, e carne, farinha, bolos de figos, e cachos de uvas passas, e vinho, e azeite, e bois, e ovelhas em abundância; porque havia alegria em Israel.

Ler em outra tradução

Comparar com outra

Estude este capítulo no WhatsApp

Peça à IA da Bíblia Fala para explicar 1 Crônicas 12, comparar traduções ou montar um estudo — tudo direto pelo WhatsApp.