Zacarias 5
Biblica® ní oore ọ̀fẹ́ láti lo Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde-Òní (YOR) vs NTLH
1 Nígbà náà ni mo yípadà, mo sì gbé ojú mi sókè, mo sì wò, sì kíyèsi i, ìwé kíká ti ń fò.
1 Tive ainda outra visão. Vi um livro em forma de rolo, que estava voando.
2 Ó sì wí fún mi pé, “Kí ni ìwọ rí?”
2 E o anjo me perguntou: — O que é que você está vendo? Eu respondi: — Estou vendo um rolo voando; ele tem nove metros de comprimento por quatro e meio de largura.
3 Ó sì wí fún mi pé, “Èyí ni ègún tí ó jáde lọ sí gbogbo ilẹ̀ ayé, nítorí gbogbo àwọn tí ó bá jalè ni a ó ké kúrò láti ìhín lọ nípa rẹ̀; gbogbo àwọn tí ó bá sì búra èké ni a ó ké kúrò láti ìhín lọ nípa rẹ̀.
3 O anjo explicou: — Neste rolo, está escrita a maldição que vai se espalhar pelo país inteiro. De um lado do rolo, está escrito que serão expulsos do país todos os que roubam; do outro lado, está escrito que serão expulsos todos os que fazem juramentos falsos pelo nome de Deus.
4 Olúwa àwọn ọmọ-ogun wí pé, ‘Èmi yóò mú un jáde, Èmi yóò si wọ inú ilé olè lọ, àti inú ilé ẹni ti o bá fi orúkọ mi búra èké, yóò si wà ni àárín ilé rẹ̀, yóò si rún pẹ̀lú igi àti òkúta inú rẹ̀.’ ”
4 O Senhor Todo-Poderoso promete que ele mandará essa maldição, e ela entrará nas casas dos ladrões e dos que juram falso pelo nome dele. Ela ficará naquelas casas até que estejam completamente destruídas; e não sobrarão nem vigas nem pedras.
5 Angẹli tí ń bá mi sọ̀rọ̀ sì jáde lọ, ó sì wí fún mi pé, “Gbé ojú rẹ sókè nísinsin yìí, kí o sì wo nǹkan tí yóò jáde lọ.”
5 O anjo que havia falado comigo voltou e me disse: — Olhe o que vem vindo agora!
6 Mo sì wí pé, “Kí ni nǹkan náà?”
6 — O que é isto? — eu perguntei. Ele respondeu: — É uma cesta, e ela representa os pecados do povo deste país.
7 Sì kíyèsi i, a gbé tálẹ́ǹtì òjé sókè, obìnrin kan sì nìyìí tí ó jókòó sí àárín àpẹẹrẹ òsùwọ̀n.
7 A cesta tinha uma tampa de chumbo; levantaram a tampa, e lá dentro estava uma mulher sentada.
8 Ó sì wí pé, “Èyí ni ìwà búburú.” Ó sì ti sí àárín òsùwọ̀n, ó sì ju ìdérí òjé sí ẹnu rẹ̀.
8 O anjo explicou: — Esta mulher representa a maldade. Então ele a empurrou para o fundo da cesta e fechou a tampa.
9 Mo sì gbé ojú mi sókè, mo sì wò, sì kíyèsi i, obìnrin méjì jáde wá, ẹ̀fúùfù sì wá nínú ìyẹ́ wọn; nítorí wọ́n ní ìyẹ́ bí ìyẹ́ àkọ̀, wọ́n sì gbé àpẹẹrẹ òsùwọ̀n náà dé àárín méjì ayé àti ọ̀run.
9 Olhei e vi duas mulheres que tinham asas como as da cegonha. As mulheres voavam, levadas pelo vento. Elas chegaram, pegaram a cesta e saíram voando.
10 Mo sì sọ fún angẹli tí ó ń bá mi sọ̀rọ̀ pé, “Níbo ni àwọn wọ̀nyí ń gbé òsùwọ̀n náà lọ.”
10 Perguntei ao anjo: — Para onde elas estão levando a cesta?
11 Ó si wí fún mi pé, “Sí orílẹ̀-èdè Babeli láti kọ ilé fún un. Tí ó bá ṣetán, a ó sì fi ìdí rẹ̀ mulẹ̀, a o sì fi ka orí ìpìlẹ̀ rẹ̀ níbẹ̀.”
11 Ele respondeu: — Para a Babilônia. Lá elas vão construir um templo, onde vão colocar a cesta numa base.
Atalhos do teclado
- Capítulo anterior←
- Próximo capítulo→
- Versículo anteriork
- Próximo versículoj
- Limpar seleçãoEsc
- Esta ajuda?
Estude este capítulo no WhatsApp
Peça à IA da Bíblia Fala para explicar Zacarias 5, comparar traduções ou montar um estudo — tudo direto pelo WhatsApp.