Salmos 29

Biblica® ní oore ọ̀fẹ́ láti lo Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde-Òní (YOR)

1 Ẹ fi fún Olúwa, ẹ̀yin ẹ̀dá ọ̀run,

2 Fi fún Olúwa, àní ògo orúkọ rẹ̀;

3 Ohùn Olúwa n ré àwọn omi kọjá;

4 Ohùn Olúwa ní agbára;

5 Ohùn Olúwa fa igi kedari;

6 Ó mú Lebanoni fo bí i ọmọ màlúù,

7 Ohùn Olúwa ń ya

8 Ohùn Olúwa ń mi aginjù.

9 Ohùn Olúwa ní ó lọ igi óákù, ó n mú abo àgbọ̀nrín bí,

10 Olúwa jókòó, Ó sì jẹ ọba lórí ìṣàn omi;

11 Kí Olúwa fi agbára fún àwọn ènìyàn rẹ̀;

Ler em outra tradução

Comparar lado a lado

Estude este capítulo no WhatsApp

Peça à IA da Bíblia Fala para explicar Salmos 29, comparar traduções ou montar um estudo — tudo direto pelo WhatsApp.