Salmos 121

Biblica® ní oore ọ̀fẹ́ láti lo Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde-Òní (YOR)

1 Èmi yóò gbé ojú mi sórí òkè wọ̀n-ọn-nì—

2 Ìrànlọ́wọ́ mi tí ọwọ́ Olúwa wá,

3 Òun kì yóò jẹ́ kí ẹsẹ̀ rẹ kí ó yẹ̀;

4 Kíyèsi, ẹni tí ń pa Israẹli mọ́,

5 Olúwa ni olùpamọ́ rẹ;

6 Oòrùn kì yóò pa ọ́ ní ìgbà ọ̀sán

7 Olúwa yóò pa ọ́ mọ́ kúrò nínú ibi gbogbo

8 Olúwa yóò pa àlọ àti ààbọ̀ rẹ mọ́

Ler em outra tradução

Comparar lado a lado

Estude este capítulo no WhatsApp

Peça à IA da Bíblia Fala para explicar Salmos 121, comparar traduções ou montar um estudo — tudo direto pelo WhatsApp.