Romanos 9
Biblica® ní oore ọ̀fẹ́ láti lo Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde-Òní (YOR) vs AAI
1 Òtítọ́ ni èmi ń sọ nínú Kristi, èmi kò ṣèké, ọkàn mi sì ń jẹ́ mi ní ẹ̀rí nínú Ẹ̀mí Mímọ́.
1 Ayu i Keriso wabinamaim tur anababatun ao, men abifufuwenamih. Anayabin dogorou naniyan atatatam Anun Kakafiyin ebibasit ayu abisa ao.
2 Pé mo ní ìbìnújẹ́ púpọ̀, àti ìkáàánú ìgbà gbogbo ni ọkàn mi.
2 Ayu dogorou wanawanan yababan awan karatan, naatu baiyufarir isan abiwa’an men ekakaram.
3 Nítorí mo fẹ́rẹ lè gbàdúrà pé kí èmi tìkára mi kúrò lọ́dọ̀ Kristi nítorí àwọn ará mi, àwọn ìbátan mi nípa ti ara.
3 Anayabin ayu au sabuw, biyau finimu turin naatu au rara anababatun, i wabihimaim mi’itube God tao rarafu. Naatu Keriso’one hita’afuru’umu atatit nabin,
4 Àwọn ẹni tí i ṣe Israẹli; tí àwọn ẹni tí ìsọdọmọ í ṣe, àti ògo, àti májẹ̀mú, àti ìfúnilófin, àti ìsìn Ọlọ́run, àti àwọn ìlérí.
4 saise Israel sabuw yawas hitab, God natunatunamih hitamatar: ana marakaw, ana obaibasit, ana obaiyunen tur hitab, kwafiren anababatun, naatu ana omatanen isah tirerereb.
5 Tí ẹni tí àwọn Baba í ṣe, àti láti ọ̀dọ̀ àwọn ẹni tí Kristi ti wá nípa ti ara, ẹni tí ó borí ohun gbogbo, Ọlọ́run olùbùkún láéláé. Àmín.
5 Nati sabuw hai a’agir kwafe’en i Hebrew big ana kik owe’owen, imaim gin tanay boro tanan Keriso ana tufuw ana’an tanatit. God akisinamo sawar etei ana bonawiyenayan tanabora’ara’ah wanatowan wanatowan. Amen.
6 Ṣùgbọ́n kì í ṣe pé nítorí ọ̀rọ̀ Ọlọ́run di asán. Kì í sá í ṣe gbogbo àwọn tí ó ti inú Israẹli wá, àwọn ni Israẹli.
6 Baise God ana omatanen i men ta baifuwenamih, mar etei i yabih temamatar. Iti ao anayabin Israel sabuw etei hai tufuw ana’an i Israelane hitufuw, baise etei’imak boro men hinan Israel sabuw hinamataramih.
7 Bẹ́ẹ̀ ni kì í ṣe pé, nítorí wọ́n jẹ́ irú-ọmọ Abrahamu, gbogbo wọn ni ọmọ. Ní ọ̀nà mìíràn, “Nínú Isaaki ni a ó ti pe irú-ọmọ rẹ̀.”
7 Na’atube Abraham ana rara’ane hitutufuw men etei Abraham natunatunamih. Bukamaim God iti na’atube eo hikirum inu’in kwaso’ob. “O natu Isaac ana rara’ane iti omatanen abit boro i hinab.”
8 Èyí nì ni pé, kì í ṣe àwọn ọmọ nípa ti ara ni ọmọ Ọlọ́run, ṣùgbọ́n àwọn ọmọ ìlérí ni a kà ní irú-ọmọ.
8 Tur iti na’atube ana kubuna kwananowar, God natunatun i men Abraham ana rara’amaim hitutufuw akisih ebowabowamih. Baise sabuw iyab omatanenane hitutufuw God natunatun i nati sabuw.
9 Nítorí ọ̀rọ̀ ìlérí ni èyí: “Ní ìwòyí àmọ́dún ni èmi yóò wá, Sara yóò sì ní ọmọ ọkùnrin.”
9 Anayabin God Abraham iti na’atube eomatan, Veya ayai’iya’imaim boro ana matabir naatu Sarah boro nataub kek orot nayai.
10 Kì í sì í ṣe kìkì èyí, ṣùgbọ́n nígbà tí Rebeka pẹ̀lú lóyún fún ẹnìkan, fún Isaaki baba wa.
10 Men nati akisin baise kwana’itin, Rebecca auman toub kek kikif ya, tamah ta’imon ata’agir Isaac.
11 Nítorí nígbà tí kò tí ì bí àwọn ọmọ náà, bẹ́ẹ̀ ni wọn kò tí ì ṣe rere tàbí búburú—kí ìpinnu Ọlọ́run nípa ti ìyànfẹ́ kí ó lè dúró,
11 Anakubuna gewas kwananowar, kek kikif wanawanahimaim kek ta bai ana kok abisa yayakitifuw isan, naatu Rebecca iu, “Kek ain boro tain isan nabow.” Kek i men hitufuw,
12 kì í ṣe nípa ti iṣẹ́, bí kò ṣe ti ẹni tí ń peni—a ti sọ fún un pé, “Ẹ̀gbọ́n ni yóò máa sin àbúrò.”
12 naatu men sawar ta gewasin o kakafin hisinafumih, baise i ana yayakitifuwen tafanamaim bat ta rubin. Men i hai bowabowamaim ta rubinimih, en.
13 Gẹ́gẹ́ bí a ti kọ ọ́ pé, “Jakọbu ni mo fẹ́ràn, ṣùgbọ́n Esau ni mo kórìíra.”
13 Bukamaim hikirum inu’in kwaso’ob, “Jacob i ayu abiyabuw, baise Esau i ayu abifa’ifai.”
14 Ǹjẹ́ àwa yóò ha ti wí? Àìṣòdodo ha wà lọ́dọ̀ Ọlọ́run bí? Kí a má ri!
14 God isan boro mi’itube tanao? I bowabow kakafin orot? Aiyabin anababatun!
15 Nítorí ó wí fún Mose pé,
15 Anayabin Moses isan eo, “Ayu orot babin yait ta anarurubin i boro anakabibir.”
16 Ǹjẹ́ bẹ́ẹ̀ ni kì í ṣe ti ẹni tí ó fẹ́, kì í sì í ṣe ti ẹni tí ń sáré, bí kò ṣe ti Ọlọ́run tí ń ṣàánú.
16 Isan imih sawar etei i men it sabuw takokok o tabowabowamaim emamatar, baise sabuw iyab God ana kokomaim ekakabibirih.
17 Nítorí ìwé mímọ́ wí fún Farao pé, “Nítorí èyí náà ni mo ṣe gbé ọ dìde, kí èmi kí ó le fi agbára mi hàn lára rẹ, àti kí a bá à le máa ròyìn orúkọ mi ká gbogbo ayé.”
17 Anayabin Buk Atamaninamaim hikirum inu’in, Moses Egypt hai aiwob orot isan eo, “Anayabin iti isan ayu abora’ahi efan yatetoro’ot ayara’ahi. Saise ayu au fair wanawanamaim anayai nabow naatu ayu wabu nara’at tafaram tutufin etei hinanowar.”
18 Nítorí náà ni ó ṣe ń ṣàánú fún ẹni tí ó wù ú, ẹni tí ó wù ú a sì mú ní ọkàn le.
18 Isan imih, God ebiyasisir sabuw iyab baibais tekokok boro nibaisih, baise sabuw iyab dogoroh efofokar boro niwa’an hinafokar.
19 Ìwọ ó sì wí fún mi pé, “Kín ni ó ha tún bá ni wí sí? Nítorí ta ni ó ń de ìfẹ́ rẹ lọ́nà?”
19 Kwa orot ta ayu isau boro iti na’atube inao, “Aisimamih God aki ebi’ubari? Yait boro ana kok nakwahir?”
20 Bẹ́ẹ̀ kọ́, ìwọ ènìyàn, tà ni ìwọ tí ń dá Ọlọ́run lóhùn? “Ohun tí a mọ, a ha máa wí fún ẹni tí ó mọ ọ́n pé, ‘Èéṣe tí ìwọ fi mọ mi báyìí?’ ”
20 O i yait, orot maiyow aisim God awan kuyayafutifut? Noukwat men karam boro ana bu’urayan isan nao, ‘Aisim iti na’atube ibu’uru?’
21 Amọ̀kòkò kò ha ni agbára lórí amọ̀, nínú ìṣù kan náà láti ṣe apá kan nínú ohun èlò sí ọlá, àti apá kan nínú ohun èlò sí àìlọ́lá?
21 Orot noukwat bu’irayan i akisin ana kokomaim me ta’imonamaim noukwat boro rou’ab nabu’ir, ta hiyuw ana noukwat, ta veya maiyow baitab isan ana noukwat.
22 Ǹjẹ́ bí Ọlọ́run bá fẹ́ fi ìbínú rẹ̀ hàn ń kọ́? Tí ó sì fẹ́ sọ agbára rẹ̀ di mí mọ̀, tí ó sì mú sùúrù púpọ̀ fún àwọn ohun èlò ìbínú tí a ṣe fún ìparun.
22 God ana yaso’ar i kok kwanekwan boro sabuw ti’obaiyih. Iyab hisisinaf kakaf isan tagurusih, saise ana fair imaim hita’itin, baise nati efanin i yatenub wainab bairi hima.
23 Àti kí ó lè sọ ọ̀rọ̀ ògo rẹ̀ di mí mọ̀ lára àwọn ohun èlò àánú tí ó ti pèsè ṣáájú fún ògo.
23 Iti na’atube sinaf, saise i ana marakaw bonamanamarin ti’obaiyit tata’itin naatu ana sabuw iyab kabibirih bairi ana marakaw faram isan rurubinih auman tataso’ob.
24 Àní àwa, tí ó ti pè, kì í ṣe nínú àwọn Júù nìkan, ṣùgbọ́n nínú àwọn Kèfèrí pẹ̀lú?
24 Anayabin it sabuw i God ea’afit, men Jew sabuw akisih, baise Ufun Sabuw auman ea’afih.
25 Bí ó ti wí pẹ̀lú ní Hosea pé,
25 God ana tur iti na’atube eo Hosea ana Bukamaim kirum.
26 Yóò sì ṣe,
26 Nati efamaim God eo, “Kwa i men ayu au sabuw.” Baise i boro nao, “Kwa i God ma’ama wanatowanin natunatun.”
27 Isaiah sì kígbe nítorí Israẹli pé:
27 Isaiah Israel sabuw isah tur rererebamaim eo, “Kwa Israel sabuw i tor ana dones na’atube, God boro matan ta’amo niyawasih.
28 Nítorí Olúwa yóò mú ọ̀rọ̀ rẹ̀ ṣẹ lórí ilẹ̀ ayé,
28 Anayabin, Regah i saise’ewat esisinaf sabuw tafaramamaim tema’am etei boro marta’imon baimakiy nitih nasawar.”
29 Àti bí Isaiah ti wí tẹ́lẹ̀:
29 Marasika iti tur Isaiah eo, “Regah Fairin men agir hai durun ta ebihamiy i, it boro tatan bar merar Sodom naatu Gomorah hairi bi’afiyih na’atube ti’afiyit.”
30 Ǹjẹ́ kí ni àwa ó ha wí? Pé àwọn Kèfèrí, tí kò lépa òdodo, ọwọ́ wọn tẹ òdodo, ṣùgbọ́n òdodo tí ó ti inú ìgbàlà wá ni.
30 Tur yomanin boro iti na’atube tanao, Ufun Sabuw i men ofafar hinuwih hibai imaim God hai ef mutufurin rouw eorerebamih, baise abisa Keriso isah sisinaf hitumatum imih God hai ef mutufurin rouw eorereb.”
31 Ṣùgbọ́n Israẹli ti ń lépa òfin òdodo, ọwọ́ wọn kò tẹ òfin òdodo.
31 Baise Israel sabuw ofafar hinuwih hinotanot hai ef i mutufor hirouw hio, baise en, anayabin i ofafar eo’omaim hisisinaf.
32 Nítorí kí ni? Nítorí wọn kò wá a nípa ìgbàgbọ́, ṣùgbọ́n bí ẹni pé nípa iṣẹ́ òfin. Nítorí wọn kọsẹ̀ lára òkúta ìkọ̀sẹ̀ ni.
32 Ana’an aisim? Ana’an i men baitumatumamaim hibat, baise abisa i hisisinafumaim hibat. Imih a rousukusukunen ana kabayamaim ah rusukun hire.
33 Gẹ́gẹ́ bí a ti kọ ọ́ pé,
33 Bukamaim hikikirum na’atube,
Atalhos do teclado
- Capítulo anterior←
- Próximo capítulo→
- Versículo anteriork
- Próximo versículoj
- Limpar seleçãoEsc
- Esta ajuda?
Estude este capítulo no WhatsApp
Peça à IA da Bíblia Fala para explicar Romanos 9, comparar traduções ou montar um estudo — tudo direto pelo WhatsApp.