Romanos 4

Biblica® ní oore ọ̀fẹ́ láti lo Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde-Òní (YOR) vs AAI

Sair da comparação
AAI TUR GEWASIN O BAIBASIT BOUBUN
1 Ǹjẹ́ kín ni àwa ó ha wí nípa Abrahamu, baba wa ti o ṣàwárí èyí? Májẹ̀mú láéláé jẹ́rìí sí i wí pé, a gba Abrahamu là nípa ìgbàgbọ́.
1 Abraham it uwat regah biyanamaim sawar abisa himatar, imaim itah soso’ob isah boro mi’itube tanao?
2 Nítorí bí a bá dá Abrahamu láre nípa iṣẹ́, ó ní ohun ìṣògo; ṣùgbọ́n kì í ṣe níwájú Ọlọ́run.
2 Anayabin Abraham ana bowabowamaim yamutufuren nabaib na’at, i karam ana ef ema’am boro nao ra’ara’at, baise men God nanamaim.
3 Ìwé Mímọ́ ha ti wí? “Abrahamu gba Ọlọ́run gbọ́, a sì kà á sí òdodo fún un.”
3 En baise, Buk Atamaninamaim iti na’atube eo? “Abraham God itumitum naatu i ana baitumatumamaim God yamutufuren ana i’inanen itin.”
4 Ǹjẹ́ fún ẹni tí ó ṣiṣẹ́, a kò ka èrè náà sí oore-ọ̀fẹ́ bí kò ṣe sí ẹ̀tọ́ rẹ̀.
4 Orot ebowabow isan tibibaiyan, nati i men ana siwar tibitin baise ana bowabow isan baiyan tibitin.
5 Ṣùgbọ́n fún ẹni tí kò ṣiṣẹ́, tí ó sì ń gba ẹni tí ó ń dá ènìyàn búburú láre gbọ́, a ka ìgbàgbọ́ rẹ̀ sí òdodo.
5 Orot yait ana bowabow men i’itin, baise ibitumitum God i sabuw kakafih eyayamutufurih. Nati orot boro yamutufuren ana’i’inanen Godane nab, anayabin ebitumatum, men ana bowabowamaim.
6 Gẹ́gẹ́ bí Dafidi pẹ̀lú ti pe olúwa rẹ̀ náà ní ẹni ìbùkún, ẹni tí Ọlọ́run ka òdodo fún láìsí ti iṣẹ́.
6 Buk Atamaninamaim David i tur ta’imon eo, orot yait yamutufuren ana’i’inanen God bitin boro baigegewasin nab, men ana bowabowamaim. Imih David iti na’atube eorereb eo,
7 Wí pé, “Ìbùkún ni fún àwọn
7 “Orot yait
8 Ìbùkún ni fún ọkùnrin náà
8 Nati orot i boro baigegewasin nab,
9 Ìbùkún yìí ha jẹ́ ti àwọn akọlà nìkan, tàbí ti àwọn aláìkọlà pẹ̀lú? Nítorí tí a wí pé, Abrahamu gba Ọlọ́run gbọ́, a sì kà á sí òdodo fún un.
9 Iti baigegewasin i sabuw iyab hai ar kanabih hi’a’afuw akisih isah, ai hai ar afuwa’e tema’ama auman isah? Baise boun tanowar, “Abraham i ana baitumatumamaim God dogoron botabir ana ef mutufurin rouw eo.”
10 Báwo ni a ṣe kà á sí i? Nígbà tí ó wà ní ìkọlà tàbí ní àìkọlà? Kì í ṣe ni ìkọlà, ṣùgbọ́n ní àìkọlà ni.
10 Iti sawar i mi’itube matar? Abraham ana ar afuwina’e ma’am ana veya matar o ana ar hi’a’afuw ufunamaim matar? Baise anao kwananowar, Abraham i wan God ana baibasit wanawanan run, imaibo ana ar i uf hi’afuw.
11 Ó sì gbé àmì ìkọlà àti èdìdì òdodo ìgbàgbọ́ tí ó ní nígbà tí ó wà ní àìkọlà kí ó lè ṣe baba gbogbo àwọn tí ó gbàgbọ́, bí a kò tilẹ̀ kọ wọ́n ní ilà kí a lè ka òdodo sí wọn pẹ̀lú.
11 Naatu nati ar afu’afuw i Abraham ana baitumatumamaim yamutufuren baib ana i’inanen. Iti sawar i Abraham ana ar kanabin auman ma’am ana veya matar. Isan imih sabuw iyab hai ar kanabih auman baise hina baitumatumayah himamatar tamah i Abraham, anayabin i hai baitumatumamaim God hai ef mutufurin rouw eorereb.
12 Àti baba àwọn tí ìkọlà tí kì í ṣe pé a kàn kọlà fún nìkan, ṣùgbọ́n tiwọn ń tẹ̀lé àpẹẹrẹ ìgbàgbọ́ tí baba wa Abrahamu ní, kí a tó kọ ọ́ nílà.
12 Naatu Abraham auman i tamah, men ar afu’afuw akisin, baise Abraham ana baitumatumamaim ana’ar kanabin auman ma reremor tibi’ufunun auman.
13 Ìlérí fún Abrahamu àti fún irú-ọmọ rẹ̀, ni pé, wọn ó jogún ayé, kì í ṣe nípa òfin bí kò ṣe nípa òdodo ti ìgbàgbọ́.
13 Abraham wawawan bairi God tafaram nowahimih baitih isan eo’omatanih ana veya i men ofafar bobosiyasiyar isan. Baise ana baitumatumamaim ana ef mumutufor isan.
14 Nítorí bí àwọn tí ń ṣe ti òfin bá jẹ ajogún, ìgbàgbọ́ di asán, ìlérí sì di aláìlágbára.
14 Anayabin sabuw iyab ofafar tebobosiyasiyar isan God ana omatanen nabitih na’at, baitumatum i boro nan ana’an en namatar naatu God ana omatanen i owararin.
15 Nítorí òfin ń ṣiṣẹ́ ìbínú, ṣùgbọ́n ní ibi tí òfin kò bá sí, ìrúfin kò sí níbẹ̀.
15 Ofafaramaim ya so’ar emamatar, baise efan menamaim ofafar men ema’am, asto’oben men ema’ama.
16 Nítorí náà ni ó ṣe gbé e ka orí ìgbàgbọ́, kí ìlérí náà bá a lè sinmi lé oore-ọ̀fẹ́, kí a sì lè mú un dá gbogbo irú-ọmọ lójú, kì í ṣe fún àwọn tí ń pa òfin mọ́ nìkan, ṣùgbọ́n bí kò ṣe pẹ̀lú fún àwọn ti ó pín nínú ìgbàgbọ́ Abrahamu, ẹni tí í ṣe baba gbogbo wa pátápátá,
16 Isan imih omatanen etei i baitumatumamaim emamatar, saise manaw kabeber Godane nan Abraham wawawan etei isah, men sabuw iyab ofafar tebobosiyasiyar akisih isah. Baise baitumatumayah auman Abraham bitumatum na’atube. Anayabin it etei ayubit isanane tamat i Abraham.
17 Gẹ́gẹ́ bí a ti kọ ọ́ pé, “Mo ti fi ọ́ ṣe baba orílẹ̀-èdè púpọ̀.” Níwájú Ọlọ́run ẹni tí òun gbàgbọ́, ẹni tí ó sọ òkú di ààyè, tí ó sì pè àwọn ohun tí kò sí bí ẹni pé wọ́n wà.
17 Bukamaim iti na’atube eo, “Ayu o asinafi tafaram tutufin etei tamah imatar. Imih iti omatanen isan Abraham God ana tur itumitum,” anayabin God i murumurubih ebiyayawasih, naatu sawar yanonowat eo hitit tibirerereb.
18 Nígbà tí ìrètí kò sí mọ́, Abrahamu gbàgbọ́ nínú ìrètí bẹ́ẹ̀ ni ó sì di baba orílẹ̀-èdè púpọ̀, gẹ́gẹ́ bí èyí tí a wí fún un pé, “Báyìí ni irú-ọmọ rẹ̀ yóò rí.”
18 Abraham sawar God eo’omatan men itah, baise baitumatumamaim nuhin fot ma kakaif yomaninamaim tafaram maumurih na’in tamah matar. Bukamaim isan eo na’atube matar, “O natunat boro daman na’atube.”
19 Ẹni tí kò rẹ̀wẹ̀sì nínú ìgbàgbọ́, nígbà tí ó mọ pe ara òun tìkára rẹ̀ tí ó ti kú tan, nítorí ó tó bí ẹni ìwọ̀n ọgọ́rùn-ún ọdún, àti nígbà tí ó ro ti yíyàgàn inú Sara.
19 Abraham ana kwamur i ra’at, biyan i morob, naatu aawan Sarah yan wanawanan kek ana bar auman i morob, baise Abraham ana baitumatum i men ririm.
20 Kò fi àìgbàgbọ́ ṣiyèméjì nípa ìlérí Ọlọ́run; ṣùgbọ́n ó lágbára sí i nínú ìgbàgbọ́ bí ó ti fi ògo fún Ọlọ́run,
20 Naatu men kafa’imo God ana omatanen isan erekasiy auman ma’amih, baise ana baitumatum eabar totofar bat God ana merar yi bora’ara’ah.
21 pẹ̀lú ìdánilójú kíkún pé, Ọlọ́run lè ṣe ohun tí ó ti ṣe ìlérí rẹ̀.
21 Abraham ana naniyan tutufin etei bai so’ob God i fairin, abisa isan eo’omatan i karam boro nasinaf.
22 Nítorí náà ni a sì ṣe kà á sí òdodo fún un.
22 Ana’an iti isan, Abraham ana baitumatumamaim ana yawas mumutufor isan God bai.
23 Ṣùgbọ́n ọ̀rọ̀ náà, “A kà á sí òdodo fún un,” ni a kọ kì í ṣe nítorí tirẹ̀ nìkan.
23 Iti tur, “Ana ef mutufurinamaim God baib” i men Abraham akisin isan hikirum.
24 Ṣùgbọ́n nítorí tiwa pẹ̀lú. A ó sì kà á sí fún wa, bí àwa bá gba ẹni tí ó gbé Jesu Olúwa wa dìde kúrò nínú òkú gbọ́.
24 Baise it auman isat hikirum, it iyabowat ata ef emumutufor naatu iyabowat tabitumatum God Jesu ata Regah morobone biyawas maiye isan.
25 Ẹni tí a pa fún ẹ̀ṣẹ̀ wa, tí a sì jí dìde nítorí ìdáláre wa.
25 Jesu it ata kakafin isan God ibasit hi’asabun, baise morobone iyawas maiye, saise it tanawiyit tanan God nanamaim tayamutufurit.

Ler em outra tradução

Comparar com outra

Estude este capítulo no WhatsApp

Peça à IA da Bíblia Fala para explicar Romanos 4, comparar traduções ou montar um estudo — tudo direto pelo WhatsApp.