Romanos 2
Biblica® ní oore ọ̀fẹ́ láti lo Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde-Òní (YOR) vs AAI
1 Nítorí náà, aláìríwí ni ẹnikẹ́ni tí ó wù kí ó jẹ́ tí ń dá ni lẹ́jọ́, nítorí nínú ohun tí ìwọ ń ṣe ìdájọ́ ẹlòmíràn, ìwọ ń dá ara rẹ lẹ́bi; nítorí ìwọ tí ń dájọ́ ń ṣe ohun kan náà nínú èyí tí ìwọ ń dá ni lẹ́jọ́.
1 Isan imih kwa isa men ef ta ema’am boro imaim kwanabat sabuw afa hai kakafih kwanasebmatar ubar kwanitih, anayabin nati kakafin ta’imon kwa auman kwasisinaf.
2 Ṣùgbọ́n àwa mọ̀ pé ìdájọ́ Ọlọ́run jẹ́ òtítọ́ si gbogbo àwọn tí ó ń ṣe irú ohun báwọ̀nyí.
2 Baise God turobe tafanamaim bat sabuw iyab kakafih tisisinaf isan baibatiyen ebitih i taso’ob.
3 Nítorí bí ìwọ tí ń ṣe ènìyàn lásán bá ń ṣe ìdájọ́ àwọn tí ń ṣe irú ohun báwọ̀nyí, tí ìwọ tìkára rẹ ń ṣe bẹ́ẹ̀, ìwọ ro èyí pé ìwọ o yọ nínú ìdájọ́ Ọlọ́run bí?
3 Imih o orot maiyow, sawar kakafin o kusisinaf na’atube sabuw tisisinaf isan o kubibatiyih o kunotanot God ana baibatiyen boro inahaiw?
4 Tàbí ìwọ ń gàn ọrọ̀ oore àti ìpamọ́ra àti sùúrù rẹ̀? Ìwọ kò ha mọ̀ pé oore Ọlọ́run ni ó ń fà ọ́ lọ sì ìrònúpìwàdà?
4 Ai o God ana baiwanbabanen, ana yawanan, ana yatenub i ku’i’itin furuw. Naatu o iwanbabani dogor baikitabirin isan enanawiyi kwa’i’itin ai en?
5 Ṣùgbọ́n gẹ́gẹ́ bí líle àti àìronúpìwàdà ọkàn rẹ̀, ìwọ ń to ìbínú jọ fún ara rẹ de ọjọ́ ìbínú àti ìfihàn ìdájọ́ òdodo Ọlọ́run.
5 Baise anayabin kwa i kwafokar naatu dogor kwahir, a baimakiy kwama kwatutu ra’at eyey ana Veya’amaim God ana yaso’ar bebeyan nab natit turobe’emaim tafaram boro nabibatiy kwana’itin.
6 Ọlọ́run yóò san án fún olúkúlùkù gẹ́gẹ́ bí iṣẹ́ rẹ̀.
6 God boro ta’ita’imon abowabow ana fofonin a baiyan nit.
7 Àwọn ẹni tí ń fi sùúrù nínú rere ṣíṣe, wá ògo àti ọlá àti àìdíbàjẹ́ ni yóò fi ìyè àìnípẹ̀kun fún.
7 Sabuw iyab yatehnub hima gewasin tisisinaf, naatu marakaw, baifa’en, ma wanatowan tinunuwih boro ma’ama wanatowanin nitih.
8 Ṣùgbọ́n fún àwọn onímọ̀-tara-ẹni-nìkan, tí wọn kò sì gba òtítọ́ gbọ́, ṣùgbọ́n tí wọn ń tẹ̀lé ọ̀nà búburú, wọn yóò ní ìrírí ìrunú àti ìbínú rẹ̀.
8 Baise sabuw iyab i taiyuwih hai yawas tinunuwih, naatu turobe hikwahir kakafih tibi’ufunun, God ana gagamat naatu ana yaso’ar boro tafah yan nisuwai nare.
9 Ìpọ́njú àti ìrora, yóò wà lórí olúkúlùkù ọkàn ènìyàn tí ń hùwà ibi: ti Júù ṣáájú, àti àwọn Helleni pẹ̀lú;
9 Sabuw iyab bowabow kakafih tisisinaf i boro bai’akir naatu biyababan gagamin maiyow hinab. Jew sabuw biyahimaim boro nabusuruf nan Ufun Sabuw biyahimaim nisawar.
10 ṣùgbọ́n ògo, àti ọlá, àti àlàáfíà, fún olúkúlùkù ẹni tí ń hùwà rere, fún Júù, ṣáájú àti fún àwọn Helleni pẹ̀lú.
10 Baise sabuw iyab bowabow gewasih tisisinaf, God boro fair, baifa’en, borara’aten naatu tufuw nitih, Jew sabuw biyahimaim boro nabusuruf nan Ufun Sabuw biyahimaim nisawar.
11 Nítorí Ọlọ́run kì í ṣe ojúsàájú ènìyàn.
11 Anayabin God i ana fofoninamaim sabuw bai’ubaren ebitih, men ta aukoun ebatabatamih.
12 Gbogbo àwọn tí ó ṣẹ̀ ní àìlófin wọn ó sì ṣègbé láìlófin, àti iye àwọn tí ó ṣẹ̀ lábẹ́ òfin, àwọn ni a ó fi òfin dá lẹ́jọ́.
12 Sabuw iyab ofafar ufunane hima kakafin hisisinaf auman boro baimakiy hinab. Naatu sabuw iyab ofafar babanamaim hima kakafin hisisinaf boro ofafar nibatiyih.
13 Nítorí kì í ṣe àwọn olùgbọ́ òfin ni ẹni ìdáláre lọ́dọ̀ Ọlọ́run, ṣùgbọ́n àwọn olùṣe òfin ni a ó dá láre.
13 Anayabin sabuw i boro men ofafar tenonowaramaim nayamutufurih God matanamaim hinatitamih, en baise ofafar hinowar tibi’ufunun boro nayamutufurih.
14 Nítorí nígbà tí àwọn aláìkọlà, tí kò ní òfin, bá ṣe ohun tí ó wà nínú òfin nípa ìwà ẹ̀dá, àwọn wọ̀nyí, jẹ́ òfin fún ara wọn bí wọn kò tilẹ̀ ní òfin.
14 Eteni Sabuw aurih ofafar i en, baise abisa i hai yawasamaim eo na’atube tisisinaf i hai ofafar turaban nati, basit i aurih ofafar anababatun i en.
15 Àwọn ẹni tí ó fihàn pé, a kọ̀wé iṣẹ́ òfin sí wọn lọ́kàn, tí ẹ̀rí ọkàn wọn pẹ̀lú sì tún ń jẹ́ wọn lẹ́rìí, àti pé, èrò ọkàn wọn tí ó jẹ́ ọ̀nà ìfinisùn, sì ń gbè wọ́n lẹ́yìn ní ìsinsin yìí.
15 Anayabin kakafin gewasin kousibin ana not i ofafar na’atube dogoromaim ema’am boro a tur na’owen, a kakafin isan boro ubar nit nakusairi, naatu a gewasin isan boro natafafari.
16 Èyí yóò farahàn ní ọjọ́ náà nígbà tí Ọlọ́run yóò tipasẹ̀ Jesu Kristi ṣe ìdájọ́ àwọn àṣírí ènìyàn gẹ́gẹ́ bí ìyìnrere mi.
16 Tur Gewasin iti ao’orereb na’atube boro namatar. Nati baibatebat ana veya God boro Jesu Keriso narubin sabuw hai not wa’iwa’irih etei boro nabow hinatit rerereb yah naya.
17 Ṣùgbọ́n bí a bá ń pe ìwọ ní Júù, tí o sì sinmi lé òfin, tí o sì ń ṣògo nínú ìbálòpọ̀ rẹ̀ sí Ọlọ́run,
17 Baise kwa Jew sabuw kwarouw kwao, naatu ofafar tafanamaim kwabat God isan kwanao ra’at.
18 tí o sì mọ ìfẹ́ rẹ̀, tí o sì fọwọ́sí ohun tí ó dára jùlọ, nítorí tí a ti kọ́ ọ ní òfin;
18 God ana kokok sinaf isan i kwaso’ob, naatu kakafin gewasin hairi kusibin isan i ofafaramaim ebi’obaiyi.
19 tí o sì dá ara rẹ lójú pé ìwọ ni amọ̀nà àwọn afọ́jú, ìmọ́lẹ̀ fún àwọn tí ó wà ni òkùnkùn,
19 Taiyuw kwaso’ob, kwa i matah fim hai nabatanayah, gugumin ma’ayah hai marakaw
20 Olùkọ́ àwọn aláìmòye, olùkọ́ àwọn ọmọdé, ẹni tí ó ní ètò ìmọ̀ àti òtítọ́ òfin lọ́wọ́.
20 koko’aw sabuw hai roube’atenayah, bereberefiy hai bai’obaiyenayan, naatu ofafar wanawanan ana kinitur tutufin etei naatu turobe etei auman i kwaso’ob.
21 Ǹjẹ́ ìwọ tí o ń kọ́ ẹlòmíràn, ìwọ kò kọ́ ara rẹ? Ìwọ tí ó ń wàásù kí ènìyàn má jalè, ìwọ ha ń jalè bí?
21 Sabuw kwabi’obaibiyih, baise kwa taiyuwiban kwabi’obaiyi ai en? A binanumaim kwao, “Men kwanabain” Baise o kubabain ai en?
22 Ìwọ tí o wí pé, kí ènìyàn má ṣe panṣágà, ìwọ ń ṣe panṣágà bí? Ìwọ tí o kórìíra òrìṣà, ìwọ ń ja tẹmpili ní olè bí?
22 Sabuw turahinah aawah ufun na isan i kuo’otanih, baise o turanah aawah ufuh kwenan ai en? Umataratar baifa’ifa’ih irouw kuo, baise hai kwafiren bar wanawanan o kubabain ai en?
23 Ìwọ ti ń ṣògo nínú òfin, ìwọ ha ń bu Ọlọ́run ni ọlá kù nípa rírú òfin?
23 God ana ofafar isan i kuo’ora’ara’at, baise ofafar i’astu’ub God biya’ohow kubitiniban kui’itin ai en?
24 Nítorí gẹ́gẹ́ bí a ti kọ ọ́, “Orúkọ Ọlọ́run sá à di ìsọ̀rọ̀-òdì sí láàrín àwọn aláìkọlà nítorí yín.”
24 Buk Atamaninamaim iti na’atube hikirum, “Eteni Sabuw God wabin tibigigim anayabin kwa Jew sabuw asinafumaim.”
25 Nítorí ìkọlà ní èrè nítòótọ́, bí ìwọ bá pa òfin mọ́; ṣùgbọ́n bí ìwọ bá jẹ́ arúfin, ìkọlà rẹ di àìkọlà.
25 O ofafar inabobosiyasiyar na’at, a’ar hi’a’afuw i boro nan ana’an gagamin namatar, baise ofafar ina’a’astu’ub, o a’ar kanabin hi’a’afuw ana’itin i afuwina’e.
26 Nítorí náà bí àwọn aláìkọlà bá pa ìlànà òfin mọ́, a kì yóò ha kà wọ́n sí àwọn tí a kọ nílà bí?
26 Sabuw iyab hai ar kanabih men hi’afuw, baise ofafar eo biyunih na’atube tebobosiyasiyar, nati sabuw i sabuw iyab hai ar kanabih hi’a’afuw hinasairih.
27 Aláìkọlà nípa àdánidá, bí ó bá pa òfin mọ́, yóò dá ẹ̀bi fún ìwọ tí ó jẹ́ arúfin nípa ti àkọsílẹ̀ òfin àti ìkọlà.
27 Orot yait biyanane ana ar kanabin men hi’afuw, baise ofafar i ebobosiyasiyar, o boro nasiksairi, anayabin o i ofafar iso’ob naatu a’ar kanabin hi’afuw, baise ofafar men kubobosiyasiyar.
28 Kì í ṣe èyí tí ó farahàn ní òde ni Júù, bẹ́ẹ̀ ni kì í ṣe èyí tí ó farahàn ní ara ni ìkọlà.
28 O yait Jew orot kumamatar i men biya ufunane hi’a’afuw imaim o ina Jew orot kumamataramih.
29 Ṣùgbọ́n Júù ti inú ni Júù, àti ìkọlà sì ni ti ọkàn nínú ẹ̀mí tí kì í ṣe ti àkọsílẹ̀, ìyìn ẹni tí kò sí lọ́dọ̀ ènìyàn, bí kò ṣe lọ́dọ̀ Ọlọ́run.
29 En baise, Jew orot anababatun i dogor wanawanan. Naatu afu’afuw anababatun i dogor wanawananamaim Anun Kakafiyin esisinaf, men biya. Naatu bora’ara’aten etei i Godane nan inab men orot biyahine.
Atalhos do teclado
- Capítulo anterior←
- Próximo capítulo→
- Versículo anteriork
- Próximo versículoj
- Limpar seleçãoEsc
- Esta ajuda?
Estude este capítulo no WhatsApp
Peça à IA da Bíblia Fala para explicar Romanos 2, comparar traduções ou montar um estudo — tudo direto pelo WhatsApp.