Oséias 6

Biblica® ní oore ọ̀fẹ́ láti lo Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde-Òní (YOR)

1 “Ẹ wá, ẹ jẹ́ kí a padà sọ́dọ̀ Olúwa

2 Lẹ́yìn ọjọ́ méjì, yóò sọ wá jí

3 Ẹ jẹ́ kí a mọ Olúwa;

4 “Kí ni èmi ó ṣe pẹ̀lú rẹ, Efraimu?

5 Nítorí náà ni mo ṣe gé e yín sí wẹ́wẹ́ láti ọwọ́ àwọn wòlíì,

6 Nítorí àánú ni mo fẹ́, kì í ṣe ẹbọ;

7 Bí i Adamu, wọ́n da májẹ̀mú

8 Gileadi jẹ́ ìlú àwọn ènìyàn búburú

9 Bí adigunjalè ṣe ń ba ní bùba de àwọn ènìyàn

10 Mo ti rí ohun tó ba ni lẹ́rù

11 “Àti fún ìwọ, Juda,

Ler em outra tradução

Comparar lado a lado

Estude este capítulo no WhatsApp

Peça à IA da Bíblia Fala para explicar Oséias 6, comparar traduções ou montar um estudo — tudo direto pelo WhatsApp.