Números 34

Biblica® ní oore ọ̀fẹ́ láti lo Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde-Òní (YOR) vs VC

Sair da comparação
VC Versão Católica
1 Olúwa sọ fún Mose pé,
1 O Senhor disse a Moisés: "Eis uma ordem para os israelitas:
2 “Pàṣẹ fún àwọn ọmọ Israẹli, kí o sì sọ fún wọn pé, ‘Tí ẹ bá wọ Kenaani, ilẹ̀ tí a ó fi fún yín, gẹ́gẹ́ bí ogún yín yóò ní ààlà wọn yí:
2 quando entrardes na terra de Canaã, eis a terra que vos tocará como herança: a terra de Canaã, com estes limites:
3 “ ‘Ìhà gúúsù yín yóò bọ́ sí ara aginjù Sini lẹ́bàá Edomu, àti ìlà-oòrùn, ààlà ìhà gúúsù yóò bẹ̀rẹ̀ láti òpin Òkun Iyọ̀,
3 para o lado do meio-dia, vossa fronteira começará no deserto de Sin ao longo de Edom. Essa fronteira meridional partirá, ao oriente, da extremidade do mar Salgado
4 kọjá lọ sí gúúsù Akrabbimu, tẹ̀síwájú lọ si Sini, kó bọ́ si gúúsù Kadeṣi-Barnea, kí o sì dé Hasari-Addari, kí o sì kọjá sí Asmoni.
4 e irá para o lado do meio-dia pela subida de Acrabim. Passará por Sin e chegará até o sul de Cades-Barne, de onde irá até Hatsar-Adar, estendendo-se para Asemon.
5 Kí òpin ilẹ̀ rẹ̀ kí ó sì yíká láti Asmoni lọ dé odò Ejibiti, Òkun Ńlá ni yóò sì jẹ òpin rẹ.
5 De Asemon dirigir-se-á para a torrente do Egito, e terminará no mar.
6 Ìhà ìwọ̀-oòrùn yín yóò jẹ́ òpin lórí Òkun Ńlá. Èyí yóò jẹ́ ààlà yín lórí ìhà ìwọ̀-oòrùn.
6 Vossa fronteira ocidental será o mar Grande, que fará o vosso limite ao ocidente.
7 Fún ààlà ìhà àríwá, fa ìlà láti Òkun Ńlá lọ sí orí òkè Hori,
7 Eis vossa fronteira setentrional: partindo do mar Grande, tereis por limite o monte Hor;
8 àti láti orí òkè Hori sí Lebo-Hamati. Nígbà náà ààlà náà yóò lọ sí Sedadi,
8 desde o monte Hor marcá-la-eis até a entrada de Hamat, terminando em Sedada;
9 tẹ̀síwájú lọ sí Sifroni, kí o sì fò pín si ní Hasari-Enani, èyí yóò jẹ́ ààlà tìrẹ ní ìhà àríwá.
9 estender-se-á em seguida para Zefron até Hatsar-Enã. Este será o vosso limite setentrional.
10 Kí ẹ sì sàmì sí ilẹ̀ tiyín ní ìhà ìlà-oòrùn láti Hasari-Enani lọ dé Ṣefamu.
10 Para vossa fronteira oriental, marcareis uma linha de Hatsar-Enã a Sefão;
11 Ààlà náà yóò ti Ṣefamu sọ̀kalẹ̀ wá lọ sí Ribla ní ìhà ìlà-oòrùn Aini, kí o sì sọ̀kalẹ̀ lọ dé ìhà Òkun Kinnereti ní ìhà ìlà-oòrùn.
11 descerá de Sefão a Rebla, ao oriente de Ain; depois, continuando, atingirá a praia oriental do mar de Ceneret,
12 Nígbà náà, ààlà náà yóò sọ̀kalẹ̀ lọ sí apá Jordani, yóò sì dópin nínú Òkun Iyọ̀.
12 e enfim, descerá ao longo do Jordão, terminando no mar Salgado. Tal será a vossa terra em todo o perímetro de vossas fronteiras."
13 Mose pa á láṣẹ fún àwọn ọmọ Israẹli pé, “Yan ilẹ̀ yìí pẹ̀lú kèké gẹ́gẹ́ bí ìní ogún: Olúwa ti pàṣẹ láti fi fún ẹ̀yà mẹ́sàn-án, àti ààbọ̀.
13 Moisés ordenou aos israelitas o seguinte: "Esta será a terra que possuireis por sorte, e que o Senhor mandou que se desse às nove tribos e à meia tribo,
14 Nítorí ará ilẹ̀ ẹ̀yà ti Reubeni, ẹ̀yà Gadi àti ẹ̀yà ààbọ̀ ti Manase ti gba ogún tiwọn.
14 porque a tribo dos rubenitas, por suas famílias, assim como a tribo dos gaditas, por suas famílias, e a meia tribo de Manassés receberam já a sua porção.
15 Ẹ̀yà méjèèjì àti ààbọ̀ yìí ti gba ogún tiwọn ní ìhà ìhín Jordani létí i Jeriko, ní ìhà ìlà-oòrùn, ní ìdojúkọ Jordani.”
15 Estas duas tribos e a meia tribo têm a sua herança além do Jordão, defronte de Jericó, para o levante."
16 Olúwa sọ fún Mose pé,
16 O Senhor disse a Moisés:
17 “Èyí ni orúkọ àwọn ọkùnrin náà tí yóò pín ilẹ̀, náà fún yín gẹ́gẹ́ bí ogún: Eleasari àlùfáà àti Joṣua ọmọ Nuni.
17 "Eis os nomes dos homens que dividirão a terra entre vós: o sacerdote Eleazar, e Josué, filho de Nun.
18 Kí o sì yan olórí kan nínú ẹ̀yà kọ̀ọ̀kan láti pín ilẹ̀ náà.
18 Tomareis, além disso, um príncipe de cada tribo para proceder à divisão."
19 “Èyí ni orúkọ wọn:
19 Eis os nomes desses príncipes: da tribo de Judá, Caleb, filho de Jefoné;
20 Ṣemueli ọmọ Ammihudu, láti ẹ̀yà Simeoni;
20 da tribo dos filhos de Simeão, Samuel, filho de Amiud;
21 Elidadi ọmọ Kisloni, láti ẹ̀yà Benjamini;
21 da tribo de Benjamim, Elidad, filho de Caselon;
22 Bukki ọmọ Jogli, láti ẹ̀yà olórí àwọn ọmọ Dani;
22 da tribo dos filhos de Dã, um príncipe, Boci, filho de Jogli;
23 Hannieli ọmọ Efodu, láti ẹ̀yà Manase, olórí àwọn ọmọ Josẹfu,
23 dos filhos de José, da tribo dos filhos de Manassés, um príncipe, Haniel, filho de Efod,
24 Kemueli ọmọ Ṣiftani, olórí ẹ̀yà àwọn ọmọ, Efraimu, ọmọ Josẹfu;
24 e da tribo dos filhos de Efraim, um príncipe, Camuel, filho de Seftã;
25 Elisafani ọmọ Parnaki, olórí ẹ̀yà àwọn ọmọ Sebuluni;
25 da tribo dos filhos de Zabulon, um príncipe, Elisafã, filho de Farnac;
26 Paltieli ọmọ Assani, olórí ẹ̀yà àwọn ọmọ Isakari;
26 da tribo dos filhos de Issacar, um príncipe, Faltiel, filho de Ozã;
27 Ahihudu ọmọ Ṣelomi, olórí ẹ̀yà àwọn ọmọ Aṣeri;
27 da tribo dos filhos de Aser, um príncipe, Aiud, filho de Salomi;
28 Pedaheli ọmọ Ammihudu, olórí ẹ̀yà àwọn ọmọ Naftali.”
28 da tribo dos filhos de Neftali, um príncipe, Fedael, filho de Amiud.
29 Èyí ni àwọn ẹni tí Olúwa yàn láti pín ogún náà fún àwọn ọmọ Israẹli ní ilẹ̀ Kenaani.
29 Tais são os que o Senhor designou para repartir entre os israelitas a terra de Canaã.

Ler em outra tradução

Comparar com outra

Estude este capítulo no WhatsApp

Peça à IA da Bíblia Fala para explicar Números 34, comparar traduções ou montar um estudo — tudo direto pelo WhatsApp.