Neemias 1

Biblica® ní oore ọ̀fẹ́ láti lo Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde-Òní (YOR) vs BKJ

Sair da comparação
1 Ọ̀rọ̀ Nehemiah ọmọ Hakaliah.
1 As palavras de Neemias, o filho de Hacalias. E sucedeu no mês de quisleu, no vigésimo ano, quando eu estava no palácio em Susã,
2 Hanani, ọ̀kan nínú àwọn arákùnrin mi wá láti Juda pẹ̀lú àwọn ọkùnrin kan, mo sì béèrè lọ́wọ́ wọn nípa àwọn Júù tí ó ṣẹ́kù tí wọn kò kó ní ìgbèkùn, àti nípa Jerusalẹmu.
2 que veio Hanani, um dos meus irmãos, ele e alguns homens de Judá; e eu perguntei-lhes a respeito dos judeus que haviam escapado, e que restaram do cativeiro, e a respeito de Jerusalém.
3 Wọ́n sọ fún mi pé, “Àwọn tí ó kù tí a kó ní ìgbèkùn tí wọ́n sì padà sí agbègbè ìjọba wà nínú wàhálà púpọ̀ àti ẹ̀gàn. Odi Jerusalẹmu ti wó lulẹ̀ a sì ti fi iná sun ẹnu ibodè rẹ̀.”
3 E eles me disseram: Os restantes, que ficaram do cativeiro, lá na província, estão em grande aflição e desprezo; e a muralha de Jerusalém também está demolida, e os seus portões estão queimados pelo fogo.
4 Nígbà tí mo gbọ́ àwọn nǹkan wọ̀nyí, mo jókòó mo sì sọkún. Mo ṣọ̀fọ̀, mo gbààwẹ̀, mo sì gbàdúrà fún ọjọ́ díẹ̀ níwájú Ọlọ́run ọ̀run.
4 E sucedeu, quando ouvi estas palavras, que eu me assentei e chorei, e lamentei alguns dias, e jejuei, e orei diante do Deus do céu,
5 Nígbà náà ni mo wí pé:
5 e disse: Eu te busco, ó ­SENHOR Deus do céu, o grande e terrível Deus, que guarda o pacto e a misericórdia por aqueles que o amam e observam os seus mandamentos;
6 Jẹ́ kí etí rẹ kí ó ṣí sílẹ̀, kí ojú ù rẹ kí ó sì ṣí sílẹ̀ láti gbọ́ àdúrà tí ìránṣẹ́ rẹ ń gbà ní iwájú rẹ ní ọ̀sán àti ní òru fún àwọn ìránṣẹ́ rẹ, àwọn ènìyàn Israẹli. Mo jẹ́wọ́ ẹ̀ṣẹ̀ àwa ọmọ Israẹli àti tèmi àti ti ilé baba mi, tí a ti ṣẹ̀ sí ọ.
6 que agora estejam atentos os teus ouvidos, e os teus olhos abertos, para que possas ouvir a oração do teu servo, a qual oro diante de ti agora, dia e noite, pelos filhos de Israel, os teus servos, e confesso os pecados dos filhos de Israel, os quais temos pecado contra ti; tanto eu, como a casa do meu pai temos pecado.
7 Àwa ti ṣe búburú sí ọ. A kò sì pa àṣẹ ìlànà àti òfin tí ìwọ fún Mose ìránṣẹ́ rẹ mọ́.
7 Temos agido mui corruptamente contra ti, e não temos guardado os mandamentos, nem os estatutos, nem os juízos que tu ordenaste ao teu servo Moisés.
8 “Rántí ìlànà tí o fún Mose ìránṣẹ́ rẹ, wí pé, ‘Bí ìwọ bá jẹ́ aláìṣòótọ́, èmi yóò fọ́n yín ká sí àárín àwọn orílẹ̀-èdè.
8 Lembra-te, rogo-te, a palavra que tu ordenaste ao teu servo Moisés, dizendo: Se vós transgredirdes, eu vos espalharei por entre as nações;
9 Ṣùgbọ́n tí ẹ̀yin bá yípadà sí mi, tí ẹ bá sì pa àṣẹ mi mọ́, nígbà náà bí àwọn ènìyàn yín tí a kó ní ìgbèkùn tilẹ̀ wà ní jìnnà réré ìpẹ̀kun ọ̀run, èmi yóò kó wọn jọ láti ibẹ̀, èmi yóò sì mú wọn wá, sí ibi tí èmi ti yàn bí i ibùgbé fún orúkọ mi.’
9 mas se vós converterdes a mim, e guardardes os meus mandamentos, e praticá-los; então, ainda que os vossos rejeitados estejam na extremidade do céu, ainda assim eu os reunirei de lá, e os trarei ao lugar que tenho escolhido para ali pôr o meu nome.
10 “Àwọn ni ìránṣẹ́ rẹ àti ènìyàn rẹ àwọn tí ìwọ rà padà pẹ̀lú agbára ńlá rẹ àti ọwọ́ agbára ńlá rẹ.
10 Ora, estes são os teus servos e o teu povo, os quais tens redimido pelo teu grande poder, e pela tua mão forte.
11 Olúwa, jẹ́ kí etí rẹ ṣí sílẹ̀ sí àdúrà ìránṣẹ́ rẹ yìí, àti sí àdúrà àwọn ìránṣẹ́ rẹ tí wọ́n ní inú dídùn láti bọ̀wọ̀ fún orúkọ rẹ. Fún ìránṣẹ́ rẹ ní àṣeyọrí lónìí kí o sì síjú àánú wò ó níwájú ọkùnrin yìí.”
11 Ó Senhor, rogo-te, que estejam atentos os teus ouvidos à oração do teu servo, e à oração dos teus servos, que desejam temer o teu nome; e faze prosperar hoje o teu servo, e concede-lhe misericórdia à vista deste homem. Porquanto, eu era o copeiro do rei.

Ler em outra tradução

Comparar com outra

Estude este capítulo no WhatsApp

Peça à IA da Bíblia Fala para explicar Neemias 1, comparar traduções ou montar um estudo — tudo direto pelo WhatsApp.