Neemias 12
Biblica® ní oore ọ̀fẹ́ láti lo Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde-Òní (YOR) vs BKJ
1 Àwọn wọ̀nyí ni àwọn àlùfáà àti àwọn ọmọ Lefi tí ó bá Serubbabeli ọmọ Ṣealitieli àti Jeṣua padà:
1 Ora, estes são os sacerdotes e os levitas que subiram com Zorobabel, o filho de Sealtiel, e Jesuá: Seraías, Jeremias, Esdras,
2 Amariah, Malluki, Hattusi,
2 Amarias, Maluque, Hatus,
3 Ṣekaniah, Rehumu, Meremoti,
3 Secanias, Reum, Meremote,
4 Iddo, Ginetoni, Abijah,
4 Ido, Ginetoi, Abias,
5 Mijamini, Moadiah, Bilgah,
5 Miamim, Maadias, Bilga,
6 Ṣemaiah, Joiaribu, Jedaiah,
6 Semaías, e Joiaribe, Jedaías,
7 Sallu, Amoki, Hilkiah, àti Jedaiah.
7 Salu, Amoque, Hilquias e Jedaías. Estes foram os chefes dos sacerdotes e dos seus irmãos nos dias de Jesuá.
8 Àwọn ọmọ Lefi ni Jeṣua, Binnui, Kadmieli, Ṣerebiah, Juda àti Mattaniah ẹni tí òun pẹ̀lú àwọn ẹlẹgbẹ́ rẹ̀, ni wọn ṣe àkóso orin ìdúpẹ́.
8 Além disso, os levitas: Jesuá, Binui, Cadmiel, Serebias, Judá e Matanias que com seus irmãos estavam encarregados de dar graças.
9 Bakbukiah àti Unni, àwọn ẹlẹgbẹ́ wọn dúró sí òdìkejì wọn nínú ìsìn.
9 Além disso, Baquebuquias e Uni, os seus irmãos, estavam defronte deles nas guardas.
10 Jeṣua ni baba Joiakimu,
10 E Jesuá gerou Joiaquim, e Joiaquim gerou Eliasibe, e Eliasibe gerou Joiada,
11 Joiada ni baba Jonatani,
11 e Joiada gerou Jônatas, e Jônatas gerou Jadua.
12 Ní ìgbé ayé Joiakimu, wọ̀nyí ni àwọn olórí àwọn ìdílé àwọn àlùfáà:
12 E nos dias de Joiaquim foram sacerdotes, os chefes dos pais; de Seraías, Meraías; de Jeremias, Hananias;
13 ti ìdílé Esra, Meṣullamu;
13 e Esdras, Mesulão; de Amarias, Joanã;
14 ti ìdílé Malluki, Jonatani;
14 de Maluqui, Jônatas; de Sebanias, José;
15 ti ìdílé Harimu, Adna;
15 de Harim, Adna; de Meraiote, Helcai;
16 ti ìdílé Iddo, Sekariah;
16 de Ido, Zacarias; de Ginetom, Mesulão;
17 ti ìdílé Abijah, Sikri;
17 de Abias, Zicri; de Miniamim, de Moadias, Piltai;
18 ti ìdílé Bilgah, Ṣammua;
18 de Bilga, Samua; de Semaías, Jônatas;
19 ti ìdílé Joiaribu, Mattenai;
19 e de Joiaribe, Matenai; de Jedaías, Uzi;
20 ti ìdílé Sallu, Kallai;
20 de Salai, Calai; de Amoque, Héber;
21 ti ìdílé Hilkiah, Haṣabiah;
21 de Hilquias, Hasabias; de Jedaías, Netanel.
22 Àwọn olórí ìdílé àwọn ọmọ Lefi ní ìgbà ayé Eliaṣibu, Joiada, Johanani àti Jaddua, àti pẹ̀lú ti àwọn àlùfáà ni a kọ sílẹ̀ ní ìgbà ìjọba Dariusi ará Persia.
22 Dos levitas nos dias de Eliasibe, Joiada, e Jonã, e Jadua, foram registrados chefes dos pais; também os sacerdotes, para o reinado de Dario, o persa.
23 Àwọn olórí ìdílé láàrín àwọn ọmọ Lefi títí di àkókò Johanani ọmọ Eliaṣibu ni a kọ sílẹ̀ nínú ìwé ìtàn.
23 Os filhos de Levi, os chefes dos pais, estavam escritos no livro das Crônicas, até os dias de Joanã, o filho de Eliasibe.
24 Àti àwọn olórí àwọn ọmọ Lefi ni Haṣabiah, Ṣerebiah, Jeṣua ọmọ Kadmieli, àti àwọn ẹlẹgbẹ́ wọn, tí wọ́n dúró ní ìdojúkojú wọn láti fi ìyìn àti láti dúpẹ́, apá kan ń dá èkejì lóhùn, gẹ́gẹ́ bí àṣẹ Dafidi ènìyàn Ọlọ́run.
24 E o chefe dos levitas: Hasabias, Serebias e Jesuá, o filho de Cadmiel, com os seus irmãos diante deles, para louvar e dar graças, segundo o mandamento de Davi, o homem de Deus, guarda contra guarda.
25 Mattaniah, Bakbukiah, Obadiah, Meṣullamu, Talmoni àti Akkubu ni aṣọ́nà tí wọ́n ń sọ yàrá ìkó nǹkan pamọ́ sí ní ẹnu-ọ̀nà.
25 Matanias, Baquebuquias, Obadias, Mesulão, Talmom e Acube, foram porteiros mantendo a guarda nas soleiras dos portões.
26 Wọ́n ṣiṣẹ́ ìránṣẹ́ ní ìgbà ayé e Joiakimu ọmọ Jeṣua, ọmọ Josadaki, àti ní ọjọ́ ọ Nehemiah baálẹ̀ àti ní ọjọ́ Esra àlùfáà àti akọ̀wé.
26 Estes foram nos dias de Joaquim, o filho de Jesuá, o filho de Jozadaque, e nos dias de Neemias, o governador, e do sacerdote Esdras, o escriba.
27 Nígbà ìyàsímímọ́ odi Jerusalẹmu a mú àwọn ọmọ Lefi jáde wá láti ibi tí wọ́n ń gbé, wọ́n sì mú wọn wá sí Jerusalẹmu láti fi ayọ̀ ṣe ayẹyẹ ìyàsímímọ́ pẹ̀lú orin ìdúpẹ́ àti pẹ̀lú ohun èlò orin kimbali, haapu àti ohun èlò orin olókùn.
27 E na dedicação da muralha de Jerusalém eles buscaram os levitas de todos os seus lugares, para trazê-los a Jerusalém, para celebrar a dedicação com alegria, com ações de graças, e com cânticos, com címbalos, saltérios e com harpas.
28 A kó àwọn akọrin náà jọ papọ̀ láti àwọn ìletò tí ó yí Jerusalẹmu náà ká—láti àwọn abúlé Netofa,
28 E os filhos dos cantores se reuniram, tanto da planície ao redor de Jerusalém, quando das aldeias de Netofatitas;
29 láti Beti-Gilgali, àti láti àwọn agbègbè Geba àti Asmafeti, nítorí àwọn akọrin ti kọ́ àwọn ìletò fúnra wọn ní agbègbè Jerusalẹmu.
29 também da casa de Gilgal, e dos campos de Gibeá e Azmavete; porquanto os cantores tinham edificado para si aldeias ao redor de Jerusalém.
30 Nígbà tí àwọn àlùfáà àti àwọn ọmọ Lefi ti ya ara wọn sí mímọ́, wọ́n ya àwọn ènìyàn sí mímọ́, àti ẹnu ibodè àti odi pẹ̀lú.
30 E os sacerdotes e os levitas se purificaram, e purificaram o povo, e os portões, e a muralha.
31 Mo sì tún yan àwọn olórí Juda láti gun orí odi náà. Mo sì tún yan àwọn ẹgbẹ́ akọrin ńlá méjì láti dúpẹ́. Àwọn kan yóò gòkè odi lọ sí apá ọ̀tún sí ọ̀nà ibodè Ààtàn.
31 Então, eu trouxe os príncipes de Judá ao alto da muralha, e constituí duas grandes companhias para dar graças, das quais uma seguiu pelo lado direito da muralha em direção ao portão do esterco;
32 Hoṣaiah àti ìdajì àwọn olórí Juda tẹ̀lé wọn,
32 e depois deles, vieram Hosaías, e a metade dos príncipes de Judá,
33 àwọn wọ̀nyí náà sì lọ pẹ̀lú wọn, Asariah, Esra, Meṣullamu,
33 e Azarias, Esdras, Mesulão,
34 Juda, Benjamini, Ṣemaiah, Jeremiah,
34 Judá, e Benjamim, e Semaías e Jeremias,
35 pẹ̀lú àwọn àlùfáà díẹ̀ pẹ̀lú ìpè, pẹ̀lú u Sekariah ọmọ Jonatani, ọmọ Ṣemaiah, ọmọ Mattaniah, ọmọ Mikaiah, ọmọ Sakkuri, ọmọ Asafu,
35 e alguns dos filhos dos sacerdotes com trombetas; a saber, Zacarias, o filho de Jônatas, o filho de Semaías, o filho de Matanias, o filho de Micaías, o filho de Zacur, o filho de Asafe;
36 àti àwọn ẹlẹgbẹ́ rẹ̀, Ṣemaiah, Asareeli, Milalai, Gilalai, Maai, Netaneli, Juda àti Hanani—pẹ̀lú ohun èlò orin bí àṣẹ Dafidi ènìyàn Ọlọ́run. Esra akọ̀wé ni ó ṣáájú wọn bí wọ́n ti ń tò lọ lọ́wọ̀ọ̀wọ́.
36 e os seus irmãos, Semaías, Azarel, Milalai, Gilalai, Maai, Netanel, Judá e Hanani, com os instrumentos musicais de Davi, o homem de Deus, e Esdras, o escriba, adiante deles.
37 Ní ẹnu ibodè orísun wọ́n ti ń lọ tààrà sí ọ̀nà ní orí àtẹ̀gùn ìlú Dafidi ní orí òkè tí ó kángun sí odi, wọ́n sì gba ẹ̀gbẹ́ ilé Dafidi kọjá títí dé ẹnu ibodè omi ní ìhà ìlà-oòrùn.
37 E na porta da fonte, a qual estava defronte deles, subiram as escadas da cidade de Davi, onde começa a subida da muralha, desde cima da casa de Davi, até o portão das águas na parte leste.
38 Àwọn ẹgbẹ́ akọrin kejì gba ọ̀nà òdìkejì lọ. Mo tẹ̀lé wọn ní orí odi, pẹ̀lú ìdajì àwọn ènìyàn, kọjá ilé ìṣọ́ ìléru lọ sí odi fífẹ̀,
38 E a outra companhia que dava graças seguia em direção a eles, e eu depois deles, e a metade do povo sobre a muralha, desde além da torre das fornalhas até a muralha larga;
39 kọjá ẹnu ibodè Efraimu ibodè Jeṣana, ẹnu ibodè ẹja, ilé ìṣọ́ Hananeli àti ilé ìṣọ́ ọgọ́rùn-ún, títí dé ẹnu ibodè àgùntàn. Wọ́n sì dúró ní ibodè ìṣọ́.
39 e do alto do portão de Efraim, e do alto do portão velho, e do alto do portão do peixe, e da torre de Hananeel, e da torre de Meá, até o portão das ovelhas; e eles pararam no portão da prisão.
40 Àwọn ẹgbẹ́ akọrin méjèèjì tí wọ́n dúpẹ́ wà ní ààyè nínú ilé Ọlọ́run, èmi náà sì dúró ní ààyè mi pẹ̀lú ìdajì àwọn ìjòyè,
40 Assim se puseram em pé as duas companhias que davam graças na casa de Deus, como também eu, e a metade dos governantes comigo,
41 àti àwọn àlùfáà Eliakimu, Maaseiah, Miniamini, Mikaiah, Elioenai, Sekariah àti Hananiah pẹ̀lú àwọn ìpè wọn.
41 e os sacerdotes: Eliaquim, Maaseias, Miniamim, Micaías, Elioenai, Zacarias e Hananias, com as trombetas;
42 Àti pẹ̀lú Maaseiah, Ṣemaiah, Eleasari àti Ussi, àti Jehohanani, àti Malkiah, àti Elamu, àti Eseri. Àwọn akọrin kọrin sókè ní abẹ́ alábojútó Jesrahiah.
42 e Maaseias, e Semaías, e Eleazar, e Uzi, e Joanã, e Malquias, e Elão, e Ezer. E os cantores cantaram em voz alta, com Jezraías, o seu supervisor.
43 Ní ọjọ́ náà wọ́n rú ẹbọ ńlá, wọ́n ṣe àjọyọ̀ nítorí Ọlọ́run ti fún wọn ní ayọ̀ ńlá. Àwọn obìnrin àti àwọn ọmọdé sì yọ̀ pẹ̀lú. A lè gbọ́ ariwo ayọ̀ tí ó jáde láti Jerusalẹmu ní jìnnà réré.
43 Além disso, naquele dia eles ofereceram grandes sacrifícios, e se regozijaram; porque Deus havia feito com que eles se regozijassem com grande alegria; também as esposas e os filhos se regozijaram; de modo que a alegria de Jerusalém se ouviu de longe.
44 Ní àkókò náà, a yan àwọn ènìyàn láti jẹ́ alábojútó yàrá ìṣúra fún àwọn ọrẹ àkọ́so èso àti àwọn ìdámẹ́wàá. Láti inú àwọn oko tí ó wà ní àyíká ìlú ni wọ́n ti ní láti mú wá sínú yàrá ìṣúra, ìpín tí òfin sọ fún àwọn àlùfáà àti àwọn ọmọ Lefi, nítorí inú àwọn ará a Juda yọ́ sí àwọn àlùfáà àti àwọn ọmọ Lefi tó ń ṣiṣẹ́ ìránṣẹ́.
44 E, naquele tempo, alguns foram indicados sobre as câmaras para os tesouros, para as ofertas, para os primeiros frutos, e para os dízimos, para nelas ajuntar, dos campos das cidades, as porções da lei para os sacerdotes e levitas; porque Judá se regozijava pelos sacerdotes e pelos levitas que serviam.
45 Wọ́n ń ṣiṣẹ́ Ọlọ́run wọn àti iṣẹ́ ìyàsímímọ́, bẹ́ẹ̀ náà ni fún àwọn akọrin àti àwọn aṣọ́nà, wọ́n ń ṣe gẹ́gẹ́ bí Dafidi àti Solomoni ọmọ rẹ̀ ti pàṣẹ fún wọn.
45 E, tanto os cantores, como os porteiros, mantinham a guarda do seu Deus, e a guarda da purificação, de acordo com o mandamento de Davi, e de seu filho Salomão.
46 Ní ọjọ́ pípẹ́ sẹ́yìn ní ìgbà Dafidi àti Asafu, ni àwọn atọ́nisọ́nà ti wà fún àwọn akọrin àti fún orin ìyìn àti orin ọpẹ́ sí Ọlọ́run.
46 Porque nos dias de Davi e Asafe, desde a antiguidade, havia chefes dos cantores, e cânticos de louvor e ações de graças a Deus.
47 Nítorí náà ní ìgbà ayé Serubbabeli àti Nehemiah, gbogbo Israẹli ni ó ń dá ìpín lójoojúmọ́ fún àwọn akọrin àti àwọn aṣọ́nà. Wọ́n sì tún yan ìpín mìíràn sọ́tọ̀ fún àwọn ọmọ Lefi tókù, àwọn ọmọ Lefi náà tún ya ìpín ti àwọn ọmọ Aaroni sọ́tọ̀ fún wọn.
47 E todo o Israel, nos dias de Zorobabel, e nos dias de Neemias, davam aos cantores e aos porteiros as porções de cada dia; e eles santificavam coisas santas aos levitas; e os levitas as santificavam para os filhos de Arão.
Atalhos do teclado
- Capítulo anterior←
- Próximo capítulo→
- Versículo anteriork
- Próximo versículoj
- Limpar seleçãoEsc
- Esta ajuda?
Estude este capítulo no WhatsApp
Peça à IA da Bíblia Fala para explicar Neemias 12, comparar traduções ou montar um estudo — tudo direto pelo WhatsApp.