Neemias 11

Biblica® ní oore ọ̀fẹ́ láti lo Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde-Òní (YOR) vs BKJ

Sair da comparação
1 Nísinsin yìí àwọn olórí àwọn ènìyàn tẹ̀dó sí Jerusalẹmu, àwọn ènìyàn tókù sì dìbò láti mú ẹnìkọ̀ọ̀kan jáde nínú àwọn mẹ́wàá mẹ́wàá láti máa gbé ní Jerusalẹmu, ìlú mímọ́, nígbà tí àwọn mẹ́sàn-án tókù yóò dúró sí àwọn ìlú u wọn.
1 E os governantes do povo habitaram em Jerusalém; o restante do povo também lançou sorte, para tirar um de dez para habitar em Jerusalém, a cidade santa, e nove partes para habitar em outras cidades.
2 Àwọn ènìyàn súre fún gbogbo àwọn ọkùnrin tí wọ́n jọ̀wọ́ ara wọn láti gbé ní Jerusalẹmu.
2 E o povo abençoou todos os homens que, voluntariamente, ofereceram-se para habitar em Jerusalém.
3 Wọ̀nyí ni àwọn olórí agbègbè ìjọba tí wọ́n tẹ̀dó sí Jerusalẹmu (díẹ̀ nínú àwọn ọmọ Israẹli àwọn àlùfáà, àwọn ọmọ Lefi, àwọn ìránṣẹ́ tẹmpili àti àwọn ìran àwọn ìránṣẹ́ Solomoni ń gbé àwọn ìlú Juda, olúkúlùkù ń gbé lórí ilẹ̀ ìní rẹ̀ ní àwọn ìlú náà.
3 Ora, estes são os chefes da província que habitaram em Jerusalém; porém nas cidades de Judá habitou cada um na sua possessão, nas suas cidades, a saber, Israel, os sacerdotes, e os levitas, e os netineus, e os filhos dos servos de Salomão.
4 Nígbà tí àwọn ènìyàn tókù nínú àwọn Juda àti Benjamini ń gbé ní Jerusalẹmu).
4 E, em Jerusalém, habitaram alguns dos filhos de Judá, e dos filhos de Benjamim. Dos filhos de Judá: Ataías, o filho de Uzias, o filho de Zacarias, o filho de Amarias, o filho de Sefatias, o filho de Maalalel, dos filhos de Perez;
5 àti Maaseiah ọmọ Baruku, ọmọ Koli-Hose, ọmọ Hasaiah, ọmọ Adaiah, ọmọ Joiaribu, ọmọ Sekariah, ọmọ Ṣilo.
5 e Maaseias, o filho de Baruque, o filho de Col-Hozé, o filho de Hazaías, o filho de Adaías, o filho de Joiaribe, o filho de Zacarias, o filho do silonita.
6 Àwọn ìran Peresi tó gbé ní Jerusalẹmu jẹ́ àádọ́rinlénírinwó ó dín méjì (468) alágbára ọkùnrin.
6 Todos os filhos de Perez que habitaram em Jerusalém foram, quatrocentos e sessenta e oito homens valentes.
7 Nínú àwọn ìran Benjamini:
7 E estes são os filhos de Benjamim: Salu, o filho de Mesulão, o filho de Joede, o filho de Pedaías, o filho de Colaías, o filho de Maaseias, o filho de Itiel, o filho de Jesaías.
8 àti àwọn ọmọ-ẹ̀yìn rẹ̀, Gabbai àti Sallai jẹ́ ọ̀rìndínlẹ́gbẹ̀rún ó lé mẹ́jọ (928) ọkùnrin.
8 E depois dele Gabai e Salai, novecentos e vinte e oito.
9 Joẹli ọmọ Sikri ni olórí òṣìṣẹ́ wọn, Juda ọmọ Hasenuah sì ni olórí agbègbè kejì ní ìlú náà.
9 E Joel, o filho de Zicri, foi o seu supervisor; e Judá, o filho de Senua foi o segundo sobre a cidade.
10 Nínú àwọn àlùfáà:
10 Dos sacerdotes: Jedaías, filho de Joiaribe, Jaquim.
11 Seraiah ọmọ Hilkiah, ọmọ Meṣullamu, ọmọ Sadoku, ọmọ Meraioti, ọmọ Ahitubu, àwọn ni olórí tó ń bojútó ilé Ọlọ́run,
11 Seraías, o filho de Hilquias, o filho de Mesulão, o filho de Zadoque, o filho de Meraiote, o filho de Aitube, foi o governante da casa de Deus.
12 àti àwọn ẹlẹgbẹ́ wọn, ẹni tí ó ń ṣe iṣẹ́ ní tẹmpili jẹ́ ẹgbẹ̀rin ó lé mẹ́rìnlélógún (822) ọkùnrin:
12 E os seus irmãos que faziam a obra da casa, foram oitocentos e vinte e dois; e Adaías, o filho de Jeroão, o filho de Pelalias, o filho de Anzi, o filho de Zacarias, o filho de Pasur, o filho de Malquias,
13 àti àwọn ẹlẹgbẹ́ ẹ rẹ̀ tí wọ́n jẹ́ olórí ìdílé jẹ́ òjìlúgba ó lé méjì (242) ọkùnrin:
13 e seus irmãos, chefes de famílias, duzentos e quarenta e dois; e Amasai, o filho de Azarel, o filho de Azai, o filho de Mesilemote, o filho de Imer,
14 àti àwọn ẹlẹgbẹ́ ẹ rẹ̀ tí wọ́n jẹ́ alágbára ọkùnrin jẹ́ méjìdínláàádóje (128).
14 e os seus irmãos, homens fortes e valentes, cento e vinte e oito; e o seu supervisor foi Zabdiel, o filho de um dos grandes homens.
15 Láti inú àwọn ọmọ Lefi:
15 Também dos levitas: Semaías, o filho de Hassube, o filho de Azricão, o filho de Hasabias, o filho de Buni;
16 Ṣabbetai àti Josabadi, olórí méjì nínú àwọn ọmọ Lefi, àwọn tí ó jẹ́ alábojútó iṣẹ́ tí ó wà ní ẹ̀yìn àgbàlá ilé Ọlọ́run;
16 e Sabetai e Jozabade, dos chefes dos levitas, tinham a supervisão dos negócios externos da casa de Deus.
17 Mattaniah ọmọ Mika, ọmọ Sabdi, ọmọ Asafu, adarí tí ó ń ṣáájú ìdúpẹ́ àti àdúrà;
17 E Matanias, o filho de Mica, o filho de Zabdi, o filho de Asafe, o chefe, que iniciava as ações de graças na oração; e Baquebuquias, o segundo entre os seus irmãos, e Abda, o filho de Samua, o filho de Galal, o filho de Jedutum.
18 Àwọn ọmọ Lefi nínú ìlú mímọ́ jẹ́ ọ̀rìnlélúgba ó lé mẹ́rin (284).
18 Todos os levitas na cidade santa eram duzentos e oitenta e quatro.
19 Àwọn aṣọ́nà:
19 Além disso, os porteiros, Acube, Talmom, e os seus irmãos que guardavam os portões, eram cento e setenta e dois.
20 Àwọn tókù nínú àwọn ọmọ Israẹli, pẹ̀lú àwọn àlùfáà àti àwọn ọmọ Lefi, wà ní gbogbo ìlú u Juda, olúkúlùkù lórí ilẹ̀ ìní tirẹ̀.
20 E os restantes de Israel, dos sacerdotes, e dos levitas, estavam em todas as cidades de Judá, cada um na sua herança.
21 Àwọn ìránṣẹ́ tẹmpili ń gbé lórí òkè Ofeli, Siha àti Giṣpa sì ni alábojútó wọn.
21 Porém, os netineus habitavam em Ofel; e Zia e Gispa estavam sobre os netineus.
22 Olórí òṣìṣẹ́ àwọn ọmọ Lefi ní Jerusalẹmu ní Ussi ọmọ Bani, ọmọ Haṣabiah, ọmọ Mattaniah ọmọ Mika. Ussi jẹ́ ọ̀kan nínú àwọn ìran Asafu tí wọ́n jẹ́ akọrin ojúṣe nínú ìjọ́sìn ní ilé Ọlọ́run.
22 Também o supervisor dos levitas em Jerusalém era Uzi, o filho de Bani, o filho de Hasabias, o filho de Matanias, o filho de Mica. Dos filhos de Asafe, os cantores estavam sobre os negócios da casa de Deus.
23 Àwọn akọrin wà ní abẹ́ àṣẹ ọba, èyí tí ó n díwọ̀n iṣẹ́ ojoojúmọ́ wọn.
23 Porque havia um mandamento do rei acerca deles, que uma certa porção deveria ser para os cantores, cada qual no seu dia.
24 Petahiah ọmọ Meṣesabeli, ọ̀kan nínú àwọn Sera ọmọ Juda ní aṣojú ọba nínú ohun gbogbo tí ó jẹ mọ́ ti àwọn ènìyàn náà.
24 E Petaías, o filho de Mesezabel, dos filhos de Zerá, o filho de Judá, estava à mão do rei em todas as questões concernentes ao povo.
25 Fún ìletò pẹ̀lú oko wọn, díẹ̀ nínú àwọn ènìyàn Juda tí ń gbé Kiriati-Arba, àti àwọn ìletò agbègbè e rẹ̀, ní Diboni àti ìletò rẹ̀, ní Jekabseeli.
25 E quanto ás aldeias, com os seus campos, alguns dos filhos de Judá habitaram em Quiriate-Arba, e nas suas aldeias, e em Dibom, e nas suas aldeias, e em Jecabzeel, e nas suas aldeias,
26 Ní Jeṣua, ní Molada, ní Beti-Peleti
26 e em Jesuá, e em Molada, e em Bete-Palete,
27 ní Hasari-Ṣuali, ní Beerṣeba àti àwọn agbègbè rẹ̀.
27 e em Hasar-Sual, e em Berseba, e nas suas aldeias,
28 Ní Siklagi, ní Mekona àti àwọn ìletò rẹ̀,
28 e em Ziclague, e em Mecona, e nas suas aldeias,
29 ní Ẹni-Rimoni, ní Sora, ní Jarmatu,
29 e em En-Rimom, e em Zorá, e em Jarmute.
30 Sanoa, Adullamu àti àwọn ìletò o wọn, ní Lakiṣi àti àwọn oko rẹ̀, àti ní Aseka àti àwọn ìletò rẹ̀. Bẹ́ẹ̀ ni wọ́n ń gbé láti Beerṣeba títí dé àfonífojì Hinnomu.
30 em Zanoa, Adulão e nas suas aldeias; em Laquis e nos seus campos; em Azeca e nas suas aldeias. E eles habitaram desde Berseba até o vale de Hinom.
31 Àwọn ọmọ Benjamini láti Geba ń gbé ní Mikmasi, Aija, Beteli àti àwọn ìletò rẹ̀.
31 Também os filhos de Benjamim, de Geba, habitaram em Micmás, e Aia, e Betel, e nas suas aldeias,
32 Ní Anatoti, Nobu àti Ananiah,
32 e em Anatote, em Nobe, em Ananias,
33 ní Hasori Rama àti Gittaimu,
33 Hazor, Ramá, Gitaim,
34 ní Hadidi, Seboimu àti Neballati,
34 Hadide, Zeboim, Nebalate,
35 ní Lodi àti Ono, àti ní àfonífojì àwọn gbẹ́nàgbẹ́nà.
35 em Lode e em Ono, no vale dos artesãos.
36 Nínú ìpín àwọn ọmọ Lefi ni Juda tẹ̀dó sí Benjamini.
36 E dos levitas estavam divisões em Judá e em Benjamim.

Ler em outra tradução

Comparar com outra

Estude este capítulo no WhatsApp

Peça à IA da Bíblia Fala para explicar Neemias 11, comparar traduções ou montar um estudo — tudo direto pelo WhatsApp.