Neemias 10
Biblica® ní oore ọ̀fẹ́ láti lo Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde-Òní (YOR) vs BKJ
1 Àwọn tí ó fi èdìdì dì í ni:
1 Ora, os que selaram foram: Neemias, o tirsata, o filho de Hacalias, e Zedequias,
2 Seraiah, Asariah, Jeremiah,
2 Seraías, Azarias, Jeremias,
3 Paṣuri, Amariah, Malkiah,
3 Pasur, Amarias, Malquias,
4 Hattusi, Ṣebaniah, Malluki,
4 Hatus, Sebanias, Maluque,
5 Harimu, Meremoti, Obadiah,
5 Harim, Meremote, Obadias,
6 Daniẹli, Ginetoni, Baruku,
6 Daniel, Ginetom, Baruque,
7 Meṣullamu, Abijah, Mijamini,
7 Mesulão, Abias, Miamim,
8 Maasiah, Bilgai àti Ṣemaiah.
8 Maaseias, Bilgai, Semaías; estes eram os sacerdotes.
9 Àwọn ọmọ Lefi:
9 E os levitas: Jesuá, o filho de Azanias, Binui, dos filhos de Henadade, e Cadmiel;
10 àti àwọn ẹlẹgbẹ́ ẹ wọn: Ṣebaniah,
10 e os seus irmãos: Sebanias, Hodias, Quelita, Pelaías, Hanã,
11 Mika, Rehobu, Haṣabiah,
11 Mica, Reobe, Hasabias,
12 Sakkuri, Ṣerebiah, Ṣebaniah,
12 Zacur, Serebias, Sebanias,
13 Hodiah, Bani àti Beninu.
13 Hodias, Bani, Beninu.
14 Àwọn olórí àwọn ènìyàn:
14 Os chefes do povo: Parós, Paate-Moabe, Elão, Zatu, Bani,
15 Bunni, Asgadi, Bebai.
15 Buni, Azgade, Bebai,
16 Adonijah, Bigfai, Adini,
16 Adonias, Bigvai, Adim,
17 Ateri, Hesekiah, Assuri,
17 Ater, Ezequias, Azur,
18 Hodiah, Haṣumu, Besai,
18 Hodias, Hasum, Besai,
19 Harifu, Anatoti, Nebai,
19 Harife, Anatote, Nebai,
20 Magpiaṣi, Meṣullamu, Hesiri
20 Magpias, Mesulão, Hezir,
21 Meṣesabeli, Sadoku, Jaddua
21 Mesezabel, Zadoque, Jadua,
22 Pelatiah, Hanani, Anaiah,
22 Pelatias, Hanã, Anaías,
23 Hosea, Hananiah, Haṣubu,
23 Oseias, Hananias, Hassube,
24 Halloheṣi, Pileha, Ṣobeki,
24 Haloés, Pileá, Sobeque,
25 Rehumu, Haṣabna, Maaseiah,
25 Reum, Hasabna, Maaseias;
26 Ahijah, Hanani, Anani,
26 e Aías, Hanã, Anã,
27 Malluki, Harimu, àti Baanah.
27 Maluque, Harim e Baaná.
28 “Àwọn ènìyàn tókù—àwọn àlùfáà, àwọn ọmọ Lefi, àwọn aṣọ́nà, àwọn ìránṣẹ́ tẹmpili àti gbogbo àwọn tí wọ́n ya ara wọn sọ́tọ̀ kúrò lára àwọn ènìyàn àjèjì nítorí òfin Ọlọ́run, papọ̀ pẹ̀lú ìyàwó wọn, gbogbo ọmọkùnrin àti àwọn ọmọbìnrin wọn, tí òye yé
28 E o restante do povo, os sacerdotes, os levitas, os porteiros, os cantores, os netineus, e todos aqueles que haviam se separado dos povos das terras para a lei de Deus, as suas esposas, os seus filhos, e as suas filhas, cada um tendo conhecimento, e tendo entendimento;
29 gbogbo wọn fi ara mọ́ àwọn arákùnrin wọn, àwọn ọlọ́lá, wọ́n sì fi ègún àti ìbúra dé ara wọn láti máa tẹ̀lé òfin Ọlọ́run tí a fi fún wọn ní ipasẹ̀ Mose ìránṣẹ́ Ọlọ́run àti láti pa gbogbo àṣẹ, ìlànà àti òfin Olúwa, wa mọ́ dáradára.
29 eles se apegaram aos seus irmãos, aos seus nobres, e entraram em uma maldição e em um juramento, de andar na lei de Deus, a qual foi dada por Moisés, o servo de Deus, e de observar e praticar todos os mandamentos do SENHOR nosso Senhor, e os seus juízos e os seus estatutos;
30 “A ti ṣe ìlérí pé, a kò ní fi àwọn ọmọbìnrin wa fún àwọn tí wọ́n wà ní àyíká wa bí ìyàwó, tàbí fẹ́ àwọn ọmọbìnrin wọn fún àwọn ọmọkùnrin wa.
30 e que nós não entregaríamos as nossas filhas aos povos da terra, nem tomaríamos as suas filhas para os nossos filhos;
31 “Nígbà tí àwọn ènìyàn àdúgbò bá mú ọjà tàbí oúnjẹ wá ní ọjọ́ ìsinmi láti tà, àwa kò ní rà á ní ọwọ́ wọn ní ọjọ́ ìsinmi tàbí ní ọjọ́ mímọ́ kankan. Ní gbogbo ọdún keje àwa kò ní ro ilẹ̀ náà, a ó sì pa gbogbo àwọn gbèsè rẹ́.
31 e se os povos da terra trouxessem produtos ou alguma provisão no dia do shabat para venderem, que nós não os compraríamos deles nem no shabat nem no dia santo; e que nós desistiríamos do sétimo ano, e da cobrança de todas as dívidas.
32 “Àwa gbà ojúṣe láti máa pa àṣẹ mọ́ pé, a ó máa san ìdámẹ́ta ṣékélì ní ọdọọdún fún iṣẹ́ ilé Ọlọ́run wa:
32 Além disso, fizemos ordenanças para nós, de encarregarmos cada ano, com a terça parte de um shekel para o serviço da casa do nosso Deus;
33 nítorí oúnjẹ tí ó wà lórí tábìlì; nítorí ọrẹ ohun jíjẹ àti ẹbọ sísun ìgbà gbogbo; nítorí ọrẹ ọjọ́ ìsinmi, ti àyajọ́ oṣù tuntun àti àjọ̀dún tí a yàn; nítorí ọrẹ mímọ́; nítorí ọrẹ ẹ̀ṣẹ̀ láti ṣe ètùtù fún Israẹli; àti fún gbogbo iṣẹ́ ilé Ọlọ́run wa.
33 para os pães da proposição, e para a oferta contínua de alimento, para a oferta queimada contínua, dos shabats, das luas novas, para as festas marcadas, e para as coisas santas, e para as ofertas pelo pecado, para fazer expiação por Israel, e para toda a obra da casa do nosso Deus.
34 “Àwa, àwọn àlùfáà, àwọn ọmọ Lefi àti àwọn ènìyàn náà ti dìbò láti pinnu ìgbà tí olúkúlùkù àwọn ìdílé yóò mú ọrẹ igi wá láti sun lọ́ríi pẹpẹ Olúwa Ọlọ́run wa sí ilé Ọlọ́run wa, ní àkókò tí a yàn ní ọdọọdún. Gẹ́gẹ́ bí a ti kọ ọ́ sínú ìwé òfin.
34 E nós lançamos a sorte no meio dos sacerdotes, dos levitas, e do povo, para a oferta de lenha, para trazê-la à casa do nosso Deus, segundo as casas dos nossos pais, nos tempos marcados ano após ano, para queimar sobre o altar do SENHOR nosso Deus, como está escrito na lei;
35 “Àwa tún gbà ojúṣe láti mú àkọ́so àwọn èso wa wá àti gbogbo èso igi wá ní ilé Olúwa.
35 e para que trouxéssemos todos os anos à casa do SENHOR os primeiros frutos do nosso solo, e os primeiros frutos de todos os frutos de todas as árvores;
36 “Gẹ́gẹ́ bí a sì ti kọ ọ́ sínú ìwé òfin, àwa yóò mú àkọ́bí àwọn ọmọkùnrin wa, ti ohun ọ̀sìn wa, ti àwọn abo màlúù àti ti àwọn àgùntàn wa, wá sí ilé Ọlọ́run wa, fún àwọn àlùfáà tí ń ṣiṣẹ́ níbẹ̀.
36 e os primogênitos dos nossos filhos, e os do nosso gado, como está escrito na lei, e os primogênitos das nossas manadas e dos nossos rebanhos, traríamos à casa do nosso Deus, aos sacerdotes que ministram na casa do nosso Deus;
37 “Síwájú sí i, àwa yóò mú àkọ́so oúnjẹ ilẹ̀ wa ti ọrẹ oúnjẹ, ti gbogbo èso àwọn igi àti ti wáìnì tuntun wa àti ti òróró wá sí yàrá ìkó nǹkan pamọ́ sí ilé Ọlọ́run wa àti fún àwọn àlùfáà. Àwa yóò sì mú ìdámẹ́wàá ohun ọ̀gbìn wá fún àwọn ọmọ Lefi, nítorí àwọn ọmọ Lefi ni ó ń gba ìdámẹ́wàá ní gbogbo àwọn ìlú tí a ti ń ṣiṣẹ́.
37 e para que trouxéssemos aos sacerdotes, para as câmaras da casa do nosso Deus, os primeiros frutos da nossa massa, e das nossas ofertas, e dos frutos de toda a sorte de árvores, do vinho, e do óleo; e os dízimos do nosso solo aos levitas; para que eles, os levitas, pudessem ter os dízimos em todas as cidades da nossa lavoura.
38 Àlùfáà tí o ti ìdílé Aaroni wá ni yóò wá pẹ̀lú àwọn ọmọ Lefi nígbà tí wọ́n bá ń gba ìdámẹ́wàá, àwọn ọmọ Lefi yóò sì mú ìdámẹ́wàá ti ìdámẹ́wàá náà wá sí ilé Ọlọ́run, sí yàrá ìkó nǹkan pamọ́ sí inú ilé ìṣúra.
38 E o sacerdote, o filho de Arão, estará com os levitas, quando os levitas receberem dízimos; e os levitas trarão o dízimo dos dízimos à casa do nosso Deus, até as câmaras, à casa do tesouro.
39 Àwọn ènìyàn Israẹli, àti àwọn ọmọ Lefi gbọdọ̀ mú ọrẹ oúnjẹ, wáìnì tuntun àti òróró wá sí yàrá ìkó nǹkan pamọ́ sí níbi tí a pa ohun èlò ibi mímọ́ mọ́ sí àti ibi tí àwọn àlùfáà tí ń ṣe ìránṣẹ́ lọ́wọ́, àwọn aṣọ́nà àti àwọn akọrin máa ń dúró sí.
39 Pois os filhos de Israel e os filhos de Levi trarão a oferta do grão, do vinho novo, e do óleo, até as câmaras, onde estão os vasos do santuário, e os sacerdotes que ministram, e os porteiros, e os cantores; e nós não abandonaremos a casa do nosso Deus.
Atalhos do teclado
- Capítulo anterior←
- Próximo capítulo→
- Versículo anteriork
- Próximo versículoj
- Limpar seleçãoEsc
- Esta ajuda?
Estude este capítulo no WhatsApp
Peça à IA da Bíblia Fala para explicar Neemias 10, comparar traduções ou montar um estudo — tudo direto pelo WhatsApp.