Mateus 7

Biblica® ní oore ọ̀fẹ́ láti lo Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde-Òní (YOR) vs AAI

Sair da comparação
AAI TUR GEWASIN O BAIBASIT BOUBUN
1 “Ẹ má ṣe dá ni lẹ́jọ́, kí a má bà dá yín lẹ́jọ́.
1 “Taituwa hai kakafin men ina’itin inibibatiyih, God boro nibatiyi.
2 Nítorí irú ìdájọ́ tí ẹ̀yin bá ṣe, òun ni a ó sì ṣe fún yín; irú òsùwọ̀n tí ẹ̀yin bá fi wọ́n, òun ni a ó sì fi wọ́n fún yín.
2 Anayabin God boro ef ta’imon taituwa ibibatiyih na’atube, o boro nibatiy, naatu fufun ta’imon taituwa ifufufunihimaim, o boro nafufuni.
3 “Èétiṣe tí ìwọ fi ń wo ẹ̀rún igi tí ń bẹ ní ojú arákùnrin rẹ, ṣùgbọ́n ìwọ kò kíyèsi ìtì igi tí ń bẹ ní ojú ara rẹ?
3 “Aisim taituwa matah mutusukwar i’itin kikin ku’o naatu o mata ahay gagamin yi ebatabat men kui’itin.
4 Tàbí ìwọ ó ti ṣe wí fún arákùnrin rẹ pé, ‘Jẹ́ kí èmi yọ ẹ̀rún igi tí ń bẹ ni ojú rẹ,’ sì wò ó ìtì igi ń bẹ ní ojú ìwọ tìkára rẹ.
4 O taituwa isan boro mi’itube awa fariniwa’an inao, ‘Aro nekuna mata mutusukwar abosair.’ Naatu baise o mar etei i matan ahay yi ebatabat.
5 Ìwọ àgàbàgebè, tètè kọ́ yọ ìtì igi jáde kúrò ní ojú ara rẹ ná, nígbà náà ni ìwọ yóò sì tó ríran kedere láti yọ ẹ̀rún igi tí ń bẹ ní ojú arákùnrin rẹ kúrò.
5 Wanawan rerekabih, mat o taiyuw mata a’ahay ina’uy, saise boro inanuw gewas taituwa matan ana ahay ina’uy.
6 “Ẹ má ṣe fi ohun mímọ́ fún ajá jẹ, ẹ má sì ṣe sọ ohun ọ̀ṣọ́ olówó iyebíye yín fún ẹlẹ́dẹ̀, bí ẹ̀yin bá ṣe bẹ́ẹ̀ kí wọ́n má bà fi ẹsẹ̀ tẹ̀ wọ́n mọ́lẹ̀, wọn a sì yí padà sí yín, wọn a sì bù yín jẹ.
6 “Abisa kakafiyin men haru aninamih kwanitih, boro hinatatabir hinayubi. Naatu a nugunug men for nahimaim kwanarub nare, boro tafan hinayen hinawasu’uru’um.
7 “Béèrè, a ó sì fi fún yín; wá kiri, ẹ̀yin yóò sì rí; kànkùn, a ó sì ṣí i sílẹ̀ fún yín.
7 “Inafefeyan boro inab, inanuwet boro inatita’ur, naatu inarukikitar etawan boro isa nabotawiy.
8 Nítorí ẹnikẹ́ni tí ó béèrè ń rí gbà, ẹni tí ó bá sì wà kiri ń rí, ẹni bá sì kànkùn ni a yóò ṣi sílẹ̀ fún.
8 Anayabin orot yait efefeyan boro nab, orot yait enunuwet boro natita’ur naatu orot yait erurukikitar etawan boro isan nabotawiy.
9 “Ta ni ọkùnrin náà tí ń bẹ nínú yín, bí ọmọ rẹ̀ béèrè àkàrà, tí yóò jẹ́ fi òkúta fún un?
9 “O yait natu, wahimih fefeyan kabay ibai itin ean?
10 Tàbí bí ó béèrè ẹja, tí yóò jẹ́ fún un ní ejò?
10 Na’atube siyamih rererey kok ibai itin ean?
11 Ǹjẹ́ bí ẹ̀yin tí í ṣe ènìyàn búburú bá mọ̀ bí a ti í fi ẹ̀bùn rere fún àwọn ọmọ yín, mélòó mélòó ni Baba yín tí ń bẹ ní ọ̀run yóò fi ohun rere fún àwọn tí ó béèrè lọ́wọ́ rẹ̀?
11 En baise Kwa i bowabow kakafih sinafuyah, baise kwaso’ob natunat boro siwar gewasih kwanitih, imih Tamat maramaim i ma tainin erubirub orot yait efefeyan boro siwar gewasin nitin.
12 Nítorí náà, nínú gbogbo ohunkóhun ti ẹ̀yin bá ń fẹ́ kí ènìyàn kí ó ṣe sí yín, bẹ́ẹ̀ ni kí ẹ̀yin kí ó ṣe sí wọn gẹ́gẹ́; nítorí èyí ni òfin àti àwọn wòlíì.
12 Imih sawar etei taituwa isah inabow, o kukok isa tebowabow na’atube, anayabin Moses ana ofafar naatu dinab oro’orot hai bai’obaiyen an anababatun i iti’imaim ku’ay inu’in.
13 “Ẹ ba ẹnu-ọ̀nà tóóró wọlé; gbòòrò ni ẹnu-ọ̀nà náà, àti oníbùú ni ojú ọ̀nà náà tí ó lọ sí ibi ìparun, ọ̀pọ̀lọpọ̀ ni àwọn ẹni tí ń bá ibẹ̀ wọlé.
13 “Etawan awan kukurinamaim kwanarun kwan, anayabin etawan awan gagamin, naatu ef awan hahabin inarun inanan yomaninamaim i gurugurusen ema’am naatu sabuw moumurih na’in imaim tenan.
14 Nítorí kékeré ni ẹnu-ọ̀nà náà, tóóró sì ni ojú ọ̀nà náà, ti ó lọ sí ibi ìyè, díẹ̀ ni àwọn ẹni tí ó ń rìn ín.
14 Baise etawan awan kukurin naatu ef awan tuwafutin inarun inanan yomaninamaim i yawas ema’am, naatu sabuw matan ta’amo imaim tenan.
15 “Ẹ máa ṣọ́ra fún àwọn èké wòlíì tí wọ́n ń tọ̀ yín wá ní àwọ̀ àgùntàn, ṣùgbọ́n ní inú wọn apanijẹ ìkookò ni wọ́n.
15 “Mata to niwa’an dinab baifufuwenayah hinanan kwana’itih, anayabin hinanan ufuhine ana itinin boro sheep na’atube, baise dogoroh wanawanan ana itinin i haru tuwetuwenih.
16 Nípa èso wọn ni ẹ̀yin ó fi mọ̀ wọn. Ǹjẹ́ ènìyàn ha lè ká èso àjàrà lára igi ọ̀gàn tàbí èso ọ̀pọ̀tọ́ lára ẹ̀gún òṣùṣú?
16 Hai bowabowamaim boro kwana’inanih, agor ro’on boro men kiw tafanamaim inima’ub, naatu wanob ro’on boro men kiw tafanamaim inima’ub?
17 Bẹ́ẹ̀ ni gbogbo igi rere a máa so èso rere ṣùgbọ́n igi búburú a máa so èso búburú.
17 Ai gewasin boro niw gewas, baise ai wanawanan kour nabiw ro’on boro nukunukuwin.
18 Igi rere kò le so èso búburú, bẹ́ẹ̀ ni igi búburú kò lè so èso rere.
18 Ai gewasin boro men ro’on nukunukuwin nayai, na’atube ai kakafin boro men ro’on gewasin nayai.
19 Gbogbo igi tí kò bá so èso rere, a gé e lulẹ̀, à wọ́ ọ jù sínú iná.
19 Ai menatan men ebiw gewas boro natar nare nab nan wairaf wan nayara’ah na’arah.
20 Nítorí náà, nípa èso wọn ni ẹ̀yin yóò mọ̀ wọn.
20 Imih dinab baifufuwenayah boro hai bowabowamaim kwana’inanih.
21 “Kì í ṣe gbogbo ẹni tó ń pè mí ní, ‘Olúwa, Olúwa,’ ni yóò wọ ìjọba ọ̀run, bí kò ṣe ẹni tó bá ń ṣe ìfẹ́ baba mi tí ń bẹ ní ọ̀run.
21 “Men sabuw etei ayu wabu hisu’ub teo, ‘Regah, Regah’ boro mar ana aiwobomaim hinarun, baise sabuw iyabowat ayu Tamai ana kok tisisinafuwat boro hinarun.
22 Ọ̀pọ̀ ni yóò wí fún mi ní ọjọ́ náà pé, ‘Olúwa, Olúwa, àwa kò ha sọtẹ́lẹ̀ ní orúkọ rẹ, àti ní orúkọ rẹ kọ́ ni a fi lé ọ̀pọ̀ ẹ̀mí èṣù jáde, tí a sì ṣe ọ̀pọ̀ iṣẹ́ ìyanu?’
22 Baibatebat ana veya nanan, sabuw moumurih na’in boro hinao, Regah, Regah, o wabimaim aki tur abai aorereb, o wabimaim aki demon kakafih anunih hibihir, naatu o wabimaim aki ina’inan moumurih na’in asinaf.
23 Nígbà náà ni èmi yóò wí fún wọn pé, ‘Èmi kò mọ̀ yín rí, ẹ kúrò lọ́dọ̀ mi ẹ̀yin oníṣẹ́ ẹ̀ṣẹ̀.’
23 Imaibo ayu boro anauwih anao, Ayu men aso’ob kwa iyab. Biyau’umaim kwatit sa’ab kwan, bowabow kakafih sinafuyah.
24 “Nítorí ẹnikẹ́ni tí ó bá gbọ́ ọ̀rọ̀ tèmi wọ̀nyí, tí ó bá sì ṣe wọn, èmi ó fiwé ọlọ́gbọ́n ènìyàn kan, ti ó kọ́ ilé rẹ̀ sí orí àpáta.
24 “Isan imih orot yait au tur nowar ebobosiyasiyar, i orot not wairafin ana bar to tafan wowab batabat na’atube.
25 Òjò sì rọ̀, ìkún omi sì dé, afẹ́fẹ́ sì fẹ́, wọ́n sí bì lu ilé náà; síbẹ̀síbẹ̀ náà kò sì wó, nítorí tí a fi ìpìlẹ̀ rẹ̀ sọlẹ̀ lórí àpáta.
25 Taun gagamin yar, harew tit, naatu wowog tit bar babin, baise bar men ufar re’emih, anayabin bar ana bubu an i to wanawanan rouw re wowab.
26 Ẹnikẹ́ni tí ó bá sì gbọ́ ọ̀rọ̀ tèmi wọ̀nyí, tí kò bá sì ṣe wọ́n, òun ni èmi yóò fiwé aṣiwèrè ènìyàn kan tí ó kọ́ ilé rẹ̀ sí orí iyanrìn.
26 Baise orot yait au tur nowar naatu men ebobosiyasiyar, i orot aurin not en bar ana bubu dones yan rouw wowowab na’atube.
27 Òjò sì rọ̀, ìkún omi sì dé, afẹ́fẹ́ sì fẹ́, wọ́n sì bì lu ilé náà, ilé náà sì wó; wíwó rẹ̀ sì pọ̀ jọjọ.”
27 Taun yar, harew tit, naatu wowog babin, bar babinakouw, naatu nati bar re’ere i ra’iy tagurugurus sawar.”
28 Nígbà tí Jesu sì parí sísọ nǹkan wọ̀nyí, ẹnu ya àwọn ọ̀pọ̀ ènìyàn sí ẹ̀kọ́ rẹ̀,
28 Jesu iti tur eo in sasawar ufunamaim, sabuw rou’ay gagamin na’in Jesu binan hinonowar isan hifofofor men kafaita.
29 nítorí ó ń kọ́ wọn bí ẹni tí ó ní àṣẹ, kì í ṣe bí i ti olùkọ́ òfin wọn.
29 Anayabin bi’obaiyih ana itinin i roubabaruwen ana fair isan ma’am na’atube, men Ofafar Bai’obaiyenayah na’atube’emih.

Ler em outra tradução

Comparar com outra

Estude este capítulo no WhatsApp

Peça à IA da Bíblia Fala para explicar Mateus 7, comparar traduções ou montar um estudo — tudo direto pelo WhatsApp.