Mateus 25
Biblica® ní oore ọ̀fẹ́ láti lo Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde-Òní (YOR) vs AAI
1 “Nígbà náà ni ó fi ìjọba ọ̀run wé àwọn wúńdíá mẹ́wàá. Ti wọ́n gbé fìtílà wọn láti lọ pàdé ọkọ ìyàwó.
1 “Nati ana veya’amaim mar ana aiwob itinin i boro baibitar nah ten biyah numin tabin boubun itinamih hai ramef hibow hinan na’atube.
2 Márùn-ún nínú wọn jẹ́ ọlọ́gbọ́n, márùn-ún nínú wọn ni wọ́n jẹ́ aláìgbọ́n.
2 Baibitar five i not wairafih, naatu baibitar five i men not wairafih.
3 Àwọn tí wọ́n jẹ́ aláìgbọ́n gbé fìtílà wọn ṣùgbọ́n wọn kò mú epo kankan lọ́wọ́.
3 Baibitar men not wairafih hai ramef hibow, baise karisin men ta hirirabar hibaimih.
4 Àwọn ọlọ́gbọ́n mú epo sínú kólòbó lọ́wọ́ pẹ̀lú fìtílà wọn.
4 Baibitar five not wairafih hai ramef hibow naatu kibubumaim karisin hirirbaren hibow auman hin.
5 Nígbà tí ọkọ ìyàwó pẹ́, gbogbo wọn tòògbé wọn sì sùn.
5 Tabin boubun ana orot men saise na, baibitar isan hima hikakaif matah fot hi’inurir hi’in.”
6 “Nígbà tí ó di ọ̀gànjọ́, igbe ta sókè, ‘Wò ó, ọkọ ìyàwó ń bọ̀, ẹ jáde sóde láti pàdé rẹ̀.’
6 “Fainaiwan sabuw fanah sibisib hinowar, ‘Tabin boubun ana orot enan kwana kwa’itin.’”
7 “Nígbà náà ni àwọn wúńdíá sì tají, wọ́n tún fìtílà wọn ṣe.
7 “Imaibo baibitar ten hi’inu’in himisir, hai ramef matah hibobaituturen naatu hito’aben.
8 Àwọn aláìgbọ́n márùn-ún tí kò ní epo rárá bẹ àwọn ọlọ́gbọ́n pé kí wọn fún àwọn nínú èyí tí wọ́n ní nítorí fìtílà wọn ń kú lọ.
8 Baibitar men not wairafih turahinah not wairafih isah hio, ‘A karisin turin kwaibaisi, aki ai ramef temomorob.’”
9 “Ṣùgbọ́n àwọn ọlọ́gbọ́n márùn-ún dáhùn pé, bẹ́ẹ̀ kọ́; kí ó má ba à ṣe aláìtó fún àwa àti ẹ̀yin, ẹ kúkú tọ àwọn tí ń tà á lọ, kí ẹ sì rà fún ara yín.
9 “Baise baibitar five not wairafih hiyafutih hio, ‘Men karam boro kwa turin anit naatu aki turin anab. Gewasin boro kwanan sabuw biyahimaim kwabo isa kwanatobon.’”
10 “Ní àsìkò tí wọ́n lọ ra epo tiwọn, ni ọkọ ìyàwó dé. Àwọn wúńdíá tí ó múra tán bá a wọlé sí ibi àsè ìgbéyàwó, lẹ́yìn náà, a sì ti ìlẹ̀kùn.
10 “Basit baibitar karisin tobonamih hinan ufut, tabin boubun ana orot natit, baibitar five hibobuna hima’am bairi hin tabin ana yasisir wanawanan hirun etawan hitufabon.”
11 “Ní ìkẹyìn ni àwọn wúńdíá márùn-ún ìyókù dé, wọ́n ń wí pé, ‘Olúwa, Olúwa, ṣílẹ̀kùn fún wa.’
11 “Men manin baibitar five hina hitit hi’afririy ‘Regah, Regah, etawan kubotawiy arun!’”
12 “Ṣùgbọ́n ọkọ ìyàwó dáhùn pé, ‘Lóòótọ́ ni mo wí fún yín èmi kò mọ̀ yín rí.’
12 “Baise orot efatait eo, ‘Anababatun a tur ao’owen, ayu men aso’ob kwa iyab.’”
13 “Nítorí náà, ẹ máa ṣọ́nà. Nítorí pé ẹ̀yin kò mọ ọjọ́ tàbí wákàtí tí Ọmọ Ènìyàn yóò dé.
13 “Isan imih mata to niwa’an kwanama, anayabin veya o sumar men kwa so’ob, mar biy boro iti sawar hinamatar.”
14 “A sì tún fi ìjọba ọ̀run wé ọkùnrin kan tí ó ń lọ sí ìrìnàjò. Ó pe àwọn ọmọ ọ̀dọ̀ rẹ̀, ó sì kó ohun ìní rẹ̀ fún wọn.
14 “Maramaim mar ana aiwob itinin ta i iti na’atube. Orot ef yok bainanawan isan bobobunabuna ana veya; ana akir wairafih e’afih hina ana sawar kaifen isan faramih.
15 Ó fún ọ̀kan ni tálẹ́ǹtì márùn-ún, ó fún èkejì ni tálẹ́ǹtì méjì, ó sì fún ẹ̀kẹta ni tálẹ́ǹtì kan, ó fún olúkúlùkù gẹ́gẹ́ bí agbára rẹ̀ ti mọ, ó sì lọ ìrìnàjò tirẹ̀.
15 Hai so’ob ana fofoninamaim orot ta ana kabay 5,000 itin, orot ta 2,000, orot ta 1,000. Imaibo i ana nanawan busuruf in.
16 Ọkùnrin tí ó gba tálẹ́ǹtì márùn-ún bẹ̀rẹ̀ lẹ́sẹ̀kẹsẹ̀ láti fi owó náà ṣòwò. Láìpẹ́, ó sì jèrè márùn-ún mìíràn.
16 Akir wairafin 5,000 baib in banikamaim yari’iy in bowabow, 5,000 tafan hiya’abar bai.
17 Ọkùnrin tí ó gba tálẹ́ǹtì méjì náà fi tirẹ̀ ṣòwò. Láìpẹ́, ó sì jèrè tálẹ́ǹtì méjì mìíràn.
17 Akir wairafin bairou’abin i na’atube sinaf. Kabay 2,000 bai in imaim ma bikukumiyaw 2,000 tafan hiya’abar bai.
18 Ṣùgbọ́n ọkùnrin tí ò gba tálẹ́ǹtì kan, ó wa ihò ní ilẹ̀, ó sì bo owó ọ̀gá mọ́ ibẹ̀.
18 Baise akir wairafin ta ana kabay 1,000 baib i mutufor in hub bai regah ana kabay hub iwan taunafut in.
19 “Lẹ́yìn ọjọ́ pípẹ́, olúwa àwọn ọmọ ọ̀dọ̀ dé láti àjò rẹ̀. Ó pè wọ́n jọ láti bá wọn ṣírò owó rẹ̀.
19 “Hima manin maiyow, imaibo akir wairafih hai orot ukwarin matabir na tit, naatu hai bowabow nuteteyan itah.
20 Ọkùnrin tí ó gba tálẹ́ǹtì márùn-ún, mú márùn-ún mìíràn padà wá, ó wí pé, ‘Olúwa, ìwọ ti fi tálẹ́ǹtì márùn-ún fún mi, mo sì ti jèrè márùn-ún mìíràn pẹ̀lú rẹ̀.’
20 Naatu akir wairafin kabay 5,000 baib na run ana regah nanamaim eo, ‘Regah o 5,000 itu, baise ayu abowabow tafanamaim 5,000 abaib i iti kubai.’”
21 “Olúwa rẹ̀ wí fún un pé, ‘O ṣeun ìwọ ọmọ ọ̀dọ̀ rere àti olóòtítọ́: ìwọ ṣe olóòtítọ́ nínú ohun díẹ̀, èmi yóò fi ọ́ ṣe olórí ohun púpọ̀, bọ́ sínú ayọ̀ olúwa rẹ.’
21 “Regah iya’afut eo, ‘A merar ayiy, o i bowayan orot gewas naatu bosunusunubayan, bowabow gidigidih ibosunusunub kukakaifen gewas, imih boro anayara’ahi inayen sawar gagamih inakaifen. Kuna kurun au yasisir turin kubai!’
22 “Èyí tí ó gba tálẹ́ǹtì méjì wí pé ‘Olúwa, ìwọ fún mi ní tálẹ́ǹtì méjì láti lò, èmi sì ti jèrè tálẹ́ǹtì méjì mìíràn.’
22 “Naatu akir wairafin bairou’abin kabay 2,000 baib na run eo, ‘Regah o a kabay 2,000 ibitu i iti, naatu abowabow tafanamaim 2,000 abaib i iti kubai.’
23 “Olúwa rẹ̀ sì wí fún un pé, ‘O ṣeun, ìwọ ọmọ ọ̀dọ̀ rere àti olóòtítọ́. Ìwọ ti jẹ́ olóòtítọ́ nínú ohun díẹ̀, èmi yóò fi ọ ṣe olórí ohun púpọ̀. Ìwọ bọ́ sínú ayọ̀ olúwa rẹ.’
23 “Regah eo, ‘A merar ayiyi, o i bowayan orot gewas naatu bosunusunubayan, sawar matan ta ibosunusunub kukakaifen gewas. Imih boro anayara’ahi inayen sawar moumurihika inakaifen. Kuna kurun au yasisir turin kubai.’
24 “Níkẹyìn, ọkùnrin tí a fún ní tálẹ́ǹtì kan wá, ó wí pé, ‘Olúwa, mo mọ̀ pé òǹrorò ènìyàn ni ìwọ ń ṣe ìwọ ń kórè níbi tí ìwọ kò gbìn sí, ìwọ ń kójọ níbi tí ìwọ kò ó ká sí.
24 “Imaibo akir wairafin baitonin kabay 1,000 baib na run eo, ‘Regah ayu aso’ob, o i a tur fokarin, turanah hai masaw o aribe kufafaur naatu turanah nowah o kutatanumabe kutaratar.
25 Èmi bẹ̀rù, mo sì lọ pa tálẹ́ǹtì rẹ mọ́ sínú ilẹ̀. Wò ó, nǹkan rẹ nìyìí.’
25 Imih ayu o isa abir. A kabay abai an hub agais aibun inu’in, iti abai ana abit maiye kwitin.’
26 “Ṣùgbọ́n olúwa rẹ̀ dáhùn pé, ‘Ìwọ ọmọ ọ̀dọ̀ búburú, ìwọ mọ̀ pé èmi ń kórè níbi tí èmi kò fúnrúgbìn sì, èmi sì ń kójọ níbi tí èmi kò fọ́nká ká sí.
26 “Ana Regah iya’afut eo, ‘O i orot kakaf nokonokow anababatun! O iso’ob, ayu i tebob nonowatih afafour naatu tetatanum nonowatih ataratar.
27 Nígbà náà ìwọ ìbá kúkú fi owó mi sí ilé ìfowópamọ́ tí èmi bá dé èmi ìbá le gba owó mi pẹ̀lú èrè.
27 Gewasin au kabay banikamaim itayi ta’in tabowabow, ayu atanan, saise tafan hitaya’abar auman hitutu atab.’
28 “ ‘Ó sì pàṣẹ kí a gba tálẹ́ǹtì náà lọ́wọ́ rẹ̀, kí a sì fún ọkùnrin tí ó ní tálẹ́ǹtì mẹ́wàá.
28 “Naatu orot ukwarin eo, ‘Kabay iti orot umanamaim kwabosair kwabai kwan akir wairafin kabay 10,000 baib i kwaitin.
29 Nítorí ẹnikẹ́ni tí ó bá ní a ó fún sí i, yóò sí tún ní sí lọ́pọ̀lọ́pọ̀. Ṣùgbọ́n láti ọwọ́ ẹni tí kò ní ni a ó ti gbà èyí tí ó ní.
29 Anayabin orot yait uman ebi’e’etaw boro sawar tafan hinaya’abar moumurihika nabow isan nakaram. Baise orot yait uman nutanub ema’am biyanamaim sawar etei’imak boro hinabosairen.
30 Nítorí ìdí èyí, gbé aláìlérè ọmọ ọ̀dọ̀, jù ú sínú òkùnkùn lóde, ibẹ̀ ni ẹ̀kún òun ìpayínkeke yóò gbé wà.’
30 Imih iti akir wairafin nukunukuwin kwabai kwan kwarauw ufun gugumin wanawanan ere, nati imaim nama narerey wan nayob nitafofofor.’
31 “Ṣùgbọ́n nígbà ti Ọmọ Ènìyàn yóò wá nínú ògo rẹ̀ pẹ̀lú gbogbo àwọn angẹli rẹ̀ nígbà náà ni yóò jókòó lórí ìtẹ́ ògo ní ọ̀run.
31 “Orot Natun ni’aiwob nanan ana maramaim ana tounamatar kakafiyih boro bairi hinan ana urama’am bonamanamarin tafan namare.
32 Gbogbo orílẹ̀-èdè ni a ó kójọ níwájú rẹ̀, òun yóò sì ya àwọn ènìyàn ayé sí ọ̀tọ̀ gẹ́gẹ́ bí olùṣọ́-àgùntàn ṣe é ya àgùntàn kúrò lára àwọn ewúrẹ́.
32 Naatu tafaram wanawanan sabuw tutufin etei boro hinaru’ay Jesu nanamaim hinabat. Imaibo i boro sabuw nakusib rou’ab hinamatar, nabatanenayan sheep naatu goat bairi ekukusibih na’atube.
33 Òun yóò sì fi àgùntàn sí ọwọ́ ọ̀tún àti ewúrẹ́ sí ọwọ́ òsì.
33 Sheep i boro uman ana asukwafune hinabat naatu goat boro uman ana beyawane hinabat.”
34 “Nígbà náà ni ọba yóò wí fún àwọn tí ó wà lọ́wọ́ ọ̀tún pé, ‘Ẹ wá, ẹ̀yin tí Baba mi ti bùkún fún, ẹ jogún ìjọba tí a ti pèsè fún yín láti ìpilẹ̀ṣẹ̀ ayé.
34 “Imaibo aiwob orot boro sabuw uman ana asukwafune isah nao, ‘Kwa i Tamai ebigegewasini, kwana mar ana aiwob nowamih kwabai. Anayabin tafaram matara’e ana veya God kwa isa yabuna.
35 Nítorí ebi pa mi, ẹ̀yin sì fún mi ní oúnjẹ, òǹgbẹ gbẹ mí, ẹ̀yin sì fún mi ní omi. Mo jẹ́ àlejò, ẹ̀yin sì pè mí sínú ilé yín.
35 Ayu bayumih amomorob bay kwaitu, sikau mamamah harew kwaitu atom, abinanawan au merar kwayi a baremaim ama ra’at ama.
36 Mo wà ní ìhòhò, ẹ̀yin sì daṣọ bò mí. Nígbà tí mo ṣe àìsàn ẹ ṣe ìtójú mi, àti ìgbà tí mo wà ní ọgbà ẹ̀wọ̀n ẹ̀yin bẹ̀ mí wò.’
36 Segar ama’am faifuw kwaitu aus, asawow ainu’in, kwakaifu naatu dibur bar ama’am kwana kwainanawanu.’”
37 “Nígbà náà ni àwọn olódodo yóò fèsì pé, ‘Olúwa, nígbà wo ni àwa rí ọ tí ebi ń pa ọ́, tí a sì fún ọ ní oúnjẹ? Tàbí tí òǹgbẹ ń gbẹ ọ́ tí a sì fún ọ ní ohun mímu?
37 “Sabuw gewasih boro hiniya’afut hinao, ‘Regah mar biyika bayumih imomorob ai’it bay ait, o sika mamamah harew ait itom?
38 Tàbí tí o jẹ́ àlejò tí a gbà ó sínú ilé wa? Tàbí tí o wà ní ìhòhò, tí a sì daṣọ bò ọ́?
38 Naatu biyika inanawan inan ai’it a merar ayiy abuwi ai sebomaim imara’at? O segar ima’am faifuw ait ius?
39 Nígbà wo ni a tilẹ̀ rí i tí o ṣe àìsàn, tàbí tí o wà ní ọgbà ẹ̀wọ̀n, tí a bẹ̀ ọ́ wò?’
39 Naatu mar biyika isawow inu’in akaifi, o dibur bar ima’ama ainanawani?’”
40 “Ọba náà yóò sì dáhùn yóò sì wí fún wọn pé, ‘Lóòótọ́ ni mo wí fún yín pé níwọ̀n ìgbà tí ẹ̀yin ṣe nǹkan wọ̀nyí fún àwọn arákùnrin mi yìí tí o kéré jú lọ, ẹ̀ ń ṣe wọn fún mi ni.’
40 “Aiwob orot boro niyafutih nao, ‘Anababatun au’uwi, nati ana veya’amaim ayu taitu gidigidih isah kwasisinaf, i ayu isau kwasinaf.’”
41 “Nígbà náà ni yóò sọ fún àwọn tí ọwọ́ òsì pé, ‘Ẹ kúrò lọ́dọ̀ mi, ẹ̀yin ẹni ègún, sínú iná àìnípẹ̀kun tí a ti tọ́jú fún èṣù àti àwọn angẹli rẹ̀.
41 “Imaibo sabuw ana beyawane hinabatabat isah boro nao, ‘Biyau’umaim kwatit sa’ab kwan. Kwa i orarafen wanawanan kwarun, Demon Mowan ana tounamatar bairi isah wairaf wanatowan hibobogaigiwas kwan imaim kwarun bairi e’arahi.
42 Nítorí tí ebi pa mi, ẹ̀yin kò tilẹ̀ bọ́ mi, òrùngbẹ gbẹ mi, ẹ kò tilẹ̀ fún mi ní omi láti mu.
42 Ayu aa amomorob, men abisa ta kwaitu aan, sikau mamamah harew men kwaitu atom.
43 Mo jẹ́ àlejò, ẹ̀yin kò tilẹ̀ gbà mi sílé. Mo wà ní ìhòhò, ẹ̀yin kò fi aṣọ bò mi. Mo ṣàìsàn, mo sì wà lọ́gbà ẹ̀wọ̀n, ẹ̀yin kò bẹ̀ mí wò.’
43 Ai nanawan anan men au merar kwayi a sebomaim amara’at. Segar ama’am faifuw men kwaitu ausimih, a sawow ainu’in, o dibur baremaim ama’am men kwana kwainanawanu.’”
44 “Nígbà náà àwọn pẹ̀lú yóò dáhùn pé, ‘Olúwa, nígbà wo ni àwa rí ọ, tí ebi ń pa ọ́ tàbí tí òǹgbẹ ń gbẹ ọ́, tàbí tí o ṣàìsàn, tàbí tí o wà lọ́gbà ẹ̀wọ̀n, tí a kò sí ràn ọ́ lọ́wọ́?’
44 “Naatu i boro hiniya’afut hinao, ‘Regah, mar biyika o aa imomorob, o harewamih sika mamamah, o ibinanawan, o segar ima’am, o isawow inu’in, o dibur bar ima’am men aibaisimih?’”
45 “Nígbà náà àwọn yóò dáhùn pé, ‘Lóòótọ́ ni mo wí fún pé, nígbà tí ẹ̀yin ti kọ̀ láti ran ọ̀kan nínú àwọn tí ó kéré jù lọ́wọ́ nínú arákùnrin mi, ẹ̀yin tí kọ̀ láti ṣe ìrànlọ́wọ́ fún mi ni.’
45 “Imaibo i boro niyafutih nao, ‘Anababatun a tur ao’owen, ayu taitu gidigidih men kwabibaisih, nati i men kwakok ayu kwatibaisu.’”
46 “Nígbà náà wọn yóò sì kọjá lọ sínú ìyà àìnípẹ̀kun, ṣùgbọ́n àwọn olódodo yóò lọ sí ìyè àìnípẹ̀kun.”
46 “Naatu nati sabuw i boro hinan ma’ama wanatowan ana baimakiy hinab. Baise sabuw gewasih boro hinan yawas ma’ama wanatowan hinab hinama hiniyasisir.”
Atalhos do teclado
- Capítulo anterior←
- Próximo capítulo→
- Versículo anteriork
- Próximo versículoj
- Limpar seleçãoEsc
- Esta ajuda?
Estude este capítulo no WhatsApp
Peça à IA da Bíblia Fala para explicar Mateus 25, comparar traduções ou montar um estudo — tudo direto pelo WhatsApp.