Mateus 24

Biblica® ní oore ọ̀fẹ́ láti lo Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde-Òní (YOR) vs AAI

Sair da comparação
AAI TUR GEWASIN O BAIBASIT BOUBUN
1 Bí Jesu ti ń kúrò ni tẹmpili, àwọn ọmọ-ẹ̀yìn rẹ̀ tọ̀ ọ́ wá, wọ́n fẹ́ fi ẹwà tẹmpili náà hàn án.
1 Jesu Tafaror Bar gagamin ihamiy tit inan auman, ana bai’ufununayah hina hiu, “Tafaror bar kwi’itin gewasin maiyow.”
2 Ṣùgbọ́n ó wí fún wọn pé, “Ẹ̀yin kò ha rí gbogbo nǹkan wọ̀nyí? Lóòótọ́ ni mo wí fún yín gbogbo ilé yìí ni a yóò wó lulẹ̀, kò ní sí òkúta kan tí a ó fi sílẹ̀ lórí òmíràn, tí a kì yóò wó lulẹ̀.”
2 Jesu iyafutih eo, “Sawar iti kwa’i’itan, a tur ao’owen, kabay etei boro natafofor nare naatu kabay ta boro men ana efanamaim na’inu’in kwana’itinimih.”
3 Bí ó ti jókòó ní orí òkè Olifi, àwọn ọmọ-ẹ̀yìn tọ̀ ọ́ wá ní ìkọ̀kọ̀, wọ́n wí pé, “Sọ fún wa nígbà wo ni èyí yóò ṣẹlẹ̀? Kí ni yóò jẹ́ àmì ìpadà wá rẹ, àti ti òpin ayé?”
3 Jesu yen Olive Oyaw tafan mare, ana bai’ufununayah wa’iwa’iramaim hina biyan hitit hibatiy hio, “Kuo anowar mar i boro biy iti sawar hinamatar? Naatu o inanan ina’inanen boro abisa ana’itin anaso’ob. Naatu mar yomanin nakakabon boro mi’itube ana so’ob?”
4 Jesu dá wọn lóhùn pé, “Ẹ má ṣe jẹ́ kí ẹnikẹ́ni tàn yín jẹ.
4 Jesu iyafutih eo, “Matato niwa’an, men sabuw hinan hinifufuwimih.
5 Nítorí ọ̀pọ̀ yóò wá ní orúkọ mi tí wọn yóò máa pe ara wọn ní Kristi náà. Wọn yóò ṣi ọ̀pọ̀lọpọ̀ lọ́nà.
5 Sabuw moumurih na’in boro ayu wabu’umaim hinan hinao, ‘Ayu i Keriso’ naatu sabuw moumurih na’in boro hinifufuwih.
6 Ẹ ó máa gbọ́ ìró ogun àti ìdágìrì ogun, kí ẹ̀yin má ṣe jáyà nítorí nǹkan wọ̀nyí kò lè ṣe kí ó ma ṣẹlẹ̀, ṣùgbọ́n òpin kì í ṣe àkókò náà.
6 Baiyow ana tur boro kwananowar, naatu baiyow isan ana tur boro kwananowar, baise men kwanabir. Sawar yumatah ta ta boro hinamatar, baise nati i men mar yomanin.
7 Orílẹ̀-èdè yóò dìde sí orílẹ̀-èdè, àti ìjọba sí ìjọba. Ìyàn àti ilẹ̀ mímì yóò wà ní ibi púpọ̀.
7 Tafaram ta boro tafaram ta hairi hiniyow, na’atube bar merar ta boro bar merar ta ana aiwob hairi hiniyow. Baimar kakafin, iriyoy boro tafaram awan nakaratan.
8 Ṣùgbọ́n gbogbo nǹkan wọ̀nyí sì jẹ́ ìbẹ̀rẹ̀ ìpọ́njú tí ó ń bọ̀.
8 Sawar iti etei hinamatar i kek tufuwamih ebobotukwar na’atube.
9 “Nígbà náà ni a ó sì dá a yín lóró. A ó pa yín, a ó sì kórìíra yín ni gbogbo orílẹ̀-èdè, nítorí pé ẹ̀yin jẹ́ tèmi.
9 “Sabuw boro hinafatumi hinabuw kwanan hini’a’akir, hina’asbuni kwanamorob, ayu wabu’umaim kwabowabow isan.
10 Àti pé, ọ̀pọ̀ nínú yín yóò kọsẹ̀, ẹ̀yin yóò ṣòfófó ara yín, ẹ̀yin yóò kórìíra ara yín pẹ̀lú,
10 Nati ana veya’amaim baitumatumayah boro hai baitumatum hinihamiy, naatu turahinah babah hinao, taiyuwih turahinah hinifa’ifa’ih,
11 ọ̀pọ̀ àwọn èké wòlíì yóò farahàn, wọn yóò tan ọ̀pọ̀lọpọ̀ ènìyàn jẹ.
11 dinab baifufuwenayah moumurih na’in boro hinatit sabuw moumurih na’in hinifufuwih.
12 Ẹ̀ṣẹ̀ yóò wà níbi gbogbo, yóò sì sọ ìfẹ́ ọ̀pọ̀ di tútù,
12 Tafa’asar boro nara’at natasasar sabuw momurih na’in hai yabow boro wan natutum.
13 ṣùgbọ́n ẹni tí ó bá forítì í dópin ni a ó gbàlà.
13 Baise yait nabukikin nan yomanin natitit i boro yawas nab.
14 A ó sì wàásù ìyìnrere nípa ìjọba náà yìí ní gbogbo ayé ká, láti ṣe ẹ̀rí fún gbogbo orílẹ̀-èdè, nígbà náà ni òpin yóò dé.
14 Tur Gewasin, mar ana aiwob isan, i boro tafaram wanawanan etei hinabinan sabuw etei hinanowar, imaibo mar yomanin boro nan natit.
15 “Nítorí náà, nígbà tí ẹ̀yin bá rí ìríra ‘ìsọdahoro, tí a ti ẹnu wòlíì Daniẹli sọ,’ tí ó bá dúró ní ibi mímọ́ (ẹnikẹ́ni tí ó bá kà á kí ó yé e),
15 “Biya’ohow Ana Sawar Kakafin boro efan kakafiyinamaim nabatabat kwana’itin, dinab orot Daniel eo na’atube. Baiyabayan orot iti tur nabiyab naniyan nab gewas.
16 nígbà náà ni kí àwọn tí ń bẹ ni Judea sálọ sí orí òkè.
16 Sabuw iyab Judea wanawananamaim tema’ama boro hinabihir hinan oyaw wan hinayen.
17 Kí ẹni tí ó wà lórí ilé rẹ̀ má ṣe sọ̀kalẹ̀ wá mú ohunkóhun jáde nínú ilé rẹ̀.
17 Orot yait ana bar faifiy wan ema’am boro men nare ana sawar bar wanawanan nabowamih, veya en.
18 Kí àwọn tí ó sì wà lóko má ṣe darí wá sí ilé láti mú àwọn aṣọ wọn.
18 Orot yait masaw ebowabow boro men namatabir ana biya baibiyon bar nabaimih.
19 Ṣùgbọ́n àánú ṣe mí fún àwọn obìnrin ti ó lóyún, àti fún àwọn tí ó ń fún ọmọ loyan ní ọjọ́ wọ̀n-ọn-nì!
19 Nati ana veya’amaim baibin iyab siasiar tema’ama naatu baibin iyab kek tibitotoman boro hini’akir yababan hinab.
20 Ẹ sì máa gbàdúrà kí sísá yín má ṣe jẹ́ ìgbà òtútù, tàbí ọjọ́ ìsinmi.
20 God isan kwanayoyoban, saise men rarab kokou ana veya’amaim o Sabbath ana veya’amaim namataramih.
21 Nítorí ìpọ́njú ńlá yóò wà, irú èyí tí kò tí ì ṣẹlẹ̀ láti ìgbà ìbẹ̀rẹ̀ ọjọ́ ayé wá títí di ìsinsin yìí irú rẹ̀ kì yóò sì ṣí.
21 Nati ana veya’amaim boro yababan kakafin men marasika anamaim o boro namamatar na’atube namataramih.
22 “Lóòótọ́, àfi bí a ké ọjọ́ wọ̀n-ọn-nì kúrú, gbogbo ẹ̀dá alààyè yóò ṣègbé. Ṣùgbọ́n nítorí ti àwọn àyànfẹ́ ni a ó fi ké ọjọ́ wọ̀n-ọn-nì kúrú.
22 God nati veya narurukabum na’at sabuw boro yawas men hinab. Baise ana sabuw rurubiniyih isah enotanot, imih veya boro narukabum.
23 Nígbà náà, bí ẹnikẹ́ni bá sọ fún yín pé, ‘Wo Kristi náà,’ tàbí pé ó ti farahàn níhìn-ín tàbí lọ́hùn ún, ẹ má ṣe gbà á gbọ́.
23 “Nati ana veya sabuw afa hinan hina’uwi, ‘Keriso’oban iti!’ o ‘Iban ni’i!’ men kwanitumatum.
24 Nítorí àwọn èké Kristi àti àwọn èké wòlíì yóò dìde. Wọn yóò sì ṣe ọ̀pọ̀ iṣẹ́ àmì àti ìyanu. Bí ó bá lè ṣe é ṣe wọn yóò tan àwọn àyànfẹ́ Ọlọ́run pàápàá jẹ.
24 Anayabin Keriso na’atube naatu dinab baifufuwenayah boro hinan ina’inan fokarih hinasinaf God ana rourubinen sabuw moumurih na’in boro hinabow.
25 Wò ó, mo ti kìlọ̀ fún yín tẹ́lẹ̀.
25 Imih abimatuwibo sawar hinamatar.
26 “Nítorí náà, bí ẹnìkan bá sọ fún yín pé, ‘Olùgbàlà ti dé,’ àti pé, ‘Ó wà ní aginjù,’ ẹ má ṣe wàhálà láti lọ wò ó, tàbí tí wọ́n bá ní, ó ń fi ara pamọ́ sí iyàrá,” ẹ má ṣe gbà wọn gbọ́.
26 “Sabuw a tur hinaowen hinao, ‘Iban nati arar yan ema’am,’ men imaim kwanan kwananuwih. O hinao, ‘Nati nanawan bar wanawanan wa’ir ema’am,’ men kwanitumatum.
27 Nítorí bí mọ̀nàmọ́ná ti ń tàn láti ìlà-oòrùn títí dé ìwọ̀-oòrùn, bẹ́ẹ̀ ni wíwá Ọmọ Ènìyàn yóò jẹ́.
27 Veya yeninane namanamar ebowabow veya ra’iyinane uman emamarakaw, Orot Natun nanan ana marakaw boro nati na’atube.
28 Nítorí ibikíbi tí òkú bá gbé wà, ibẹ̀ ni àwọn ẹyẹ igún ń kójọpọ̀ sí.
28 Menamaim orot babin biyan murubin inu’in mamu ikou boro etei imaim hinaru’ay.
29 “Lójúkan náà, lẹ́yìn ìpọ́njú ọjọ́ wọ̀n-ọn-nì,
29 “Yababan iti hinamamatar ufunamaim
30 “Nígbà náà ni àmì Ọmọ Ènìyàn yóò sì fi ara hàn ní ọ̀run, nígbà náà ni gbogbo ẹ̀yà ayé yóò káàánú, wọn yóò sì rí Ọmọ Ènìyàn tí yóò máa ti ojú ọ̀run bọ̀ ti òun ti ògo àti agbára ńlá.
30 “Imaibo Orot Natun maramaim boro natit, tafaram wanawanan sabuw etei orot Natun ana fair ana marakaw bonamanamarin auman natit sakuk wanawanan nanan hina’itin hinama hinarerey.
31 Yóò sì rán àwọn angẹli rẹ̀ jáde pẹ̀lú ohùn ìpè ńlá, wọn yóò sì kó gbogbo àwọn àyànfẹ́ rẹ̀ láti orígun mẹ́rẹ̀ẹ̀rin ayé àti ọ̀run jọ.
31 Ana tounamatar boro taur douduf auman hinatit tafaram tutufin wanawanan umasusun kwafe’en etei God ana sabuw rurubinih hinabow hinita’ay.
32 “Nísinsin yìí, ẹ kọ́ òwe lára igi ọ̀pọ̀tọ́. Nígbà tí ẹ̀ka rẹ̀ bá ti ń yọ tuntun tí ó bá sì ń ru ewé, ẹ̀yin mọ̀ pé ìgbà ẹ̀ẹ̀rùn súnmọ́ tòsí.
32 “Ai fofou raurihimaim ebi’obaiyih kwanaso’ob, ai raurih boubuh tititit kwa kwaso’ob, ai hai buwayan ana veya i natit.
33 Bẹ́ẹ̀ gẹ́gẹ́, nígbà tí ẹ̀yin bá sì rí i tí gbogbo nǹkan wọ̀nyí bá ń ṣẹlẹ̀, kí ẹ mọ̀ pé ìpadàbọ̀ mi dé tán lẹ́yìn ìlẹ̀kùn.
33 Bai’obaiyen i ta’imon, sawar iti na’atube hinamamatar kwa boro kwanaso’ob, veya i nakabom etawan awanamaim ebatabat.
34 Lóòótọ́ ni mo wí fún yín, ìran yìí kì yóò kọjá títí tí gbogbo nǹkan wọ̀nyí yóò fi ṣẹ.
34 Anababatun a tur ao’owen, sabuw iti boun yawas kwama’am boro iti sawar namatar kwana’itinibo kwanamorob.
35 Ọ̀run àti ayé yóò rékọjá, ṣùgbọ́n ọ̀rọ̀ mi kì yóò rékọjá.
35 Mar tafaram i boro nasawar, baise ayu au tur boro men nasawar.
36 “Ṣùgbọ́n kò sí ẹnìkan ti ó mọ ọjọ́ àti wákàtí tí òpin náà yóò dé, àwọn angẹli ọ̀run pàápàá kò mọ̀ ọ́n. Àní, ọmọ kò mọ̀ ọ́n, bí kò ṣe Baba mi nìkan ṣoṣo ló mọ̀ ọ́n.
36 “Orot men yait ta Jesu ana na isan veya o sumar so’obamih. tounamatar maramaim men hiso’ob na’atube i Natun auman men so’ob, baise Tamah akisinamo so’ob.
37 Bí ó ṣe rí ní ìgbà ayé Noa, bẹ́ẹ̀ gẹ́gẹ́ ni wíwá Ọmọ Ènìyàn yóò sì rí.
37 Noah ana veya’amaim abisa mamatar na’atube Orot Natun nanan boro na’atube namatar.
38 Nítorí bí àwọn ọjọ́ náà ti wà ṣáájú ìkún omi, tí wọ́n ń jẹ́ tí wọ́n ń mu, tí wọ́n ń gbéyàwó, tí wọ́n sì ń fa ìyàwó fún ni, títí tí ó fi di ọjọ́ tí Noa fi bọ́ sínú ọkọ̀.
38 Nati ana veya tuw yena’e ana veya orot babin hiyuw hibow, hiaa hitom, hitabin hibiyasisir ufut Noah ark wanawanan run;
39 Ènìyàn kò gbàgbọ́ nípa ohun tí o ṣẹlẹ̀ títí tí ìkún omi fi dé nítòótọ́, tí ó sì kó wọn lọ. Bẹ́ẹ̀ gẹ́gẹ́ ni wíwá Ọmọ Ènìyàn.
39 naatu so’oba’e hima’am kwanekwan tuw yen etei e’aruwih hin himorob. Imih orot Natun nanan ana itinin i boro nati na’atube.
40 Àwọn ọkùnrin méjì yóò máa ṣiṣẹ́ nínú oko, a o mú ẹnìkan, a ó sì fi ẹni kejì sílẹ̀.
40 Orot rou’ab boro hai masaw hinama hinabob, Orot ta boro tounamatar hinabora’ah ta boro hinihamiy nama.
41 Àwọn obìnrin méjì yóò jùmọ̀ máa lọ ọlọ pọ̀, a yóò mú ọ̀kan, a ó fi ẹni kejì sílẹ̀.
41 Baibin rou’ab boro hinama maiwok hinakakair, babin ta boro hinabora’ah, babin ta boro hinihamiy nama.
42 “Nítorí náà, ẹ múra sílẹ̀, nítorí ẹ kò mọ ọjọ́ tí Olúwa yín yóò dé.
42 “Isan imih mata to niwa’an, anayabin men kwaso’ob mar biy boro a Regah nan.
43 Ṣùgbọ́n, kí ẹ mọ èyí pé, baálé ilé ìbá mọ wákàtí náà tí olè yóò wá, ìbá máa ṣọ́nà, òun kì bá ti jẹ́ kí a já wọ ilé rẹ̀.
43 Baise tur iti ao i naniyan kwanab. Orot bar matuwan bainowan hai veya nasoso’ob, boro matan nanuw nama’am nanunih hinabihir, ana bar boro men hinakwib hinabainuwimih.
44 Nítorí náà, ẹ gbọdọ̀ wà ní ìmúrasílẹ̀, nítorí ní wákàtí àìròtẹ́lẹ̀ ni dídé Ọmọ Ènìyàn yóò jẹ́.
44 Imih mar etei mata to niwa’an kwanabobuna kwanama, anayabin Orot Natun boro men o veya kunotanotamaim natitamih.
45 “Ǹjẹ́ olóòtítọ́ àti ọlọ́gbọ́n ọmọ ọ̀dọ̀ wo ni olúwa rẹ̀ lè fi ṣe olùbojútó ilé rẹ̀ láti bọ́ àwọn ọmọ rẹ̀ lójoojúmọ́?
45 “Akir wairafin bosunusunubayan naatu not wairafin ana orot ukwarin boro nayara’ah akir wairafih afa nakaifih hai bay ana veya’amaim nitih.
46 Alábùkún fún ni ọmọ ọ̀dọ̀ ti olúwa rẹ̀ dé tí ó sì bá a lórí iṣẹ́ ṣíṣe.
46 Naatu ana orot ukwarin namatabir nanan bowabow gewasin nabowabow na’itin boro niyasisir.
47 Lóòótọ́ ni mo wí fún yín, èmi yóò sì fi irú ẹni bẹ́ẹ̀ ṣe alákòóso gbogbo ohun tí mo ní.
47 A tur ao’owen nati akir wairafin boro nayara’ah sawar etei nakaifen.
48 Ṣùgbọ́n bí ọmọ ọ̀dọ̀ náà bá jẹ́ ènìyàn búburú náà bá wí ní ọkàn rẹ̀ pé, ‘Olúwa mi kì yóò tètè dé.’
48 Baise akir wairafin nitafasar nao, ‘Au orot ukwarin men saise matabir enanamih.’
49 Tí ó sì bẹ̀rẹ̀ si í fi ìyà jẹ́ àwọn ìránṣẹ́ ẹlẹgbẹ́ rẹ̀, tí ó ń jẹ, tí ó sì ń mu àmupara.
49 Naatu natatabir akir wairafih afa narauw ni’a’afiyih bay naa, harew tomayah bairi hinaa hinatom hinabikoko’aw wanawanan
50 Nígbà náà ni olúwa ọmọ ọ̀dọ̀ yóò wá ní ọjọ́ àti wákàtí tí kò retí.
50 veya naatu sumar so’oba’e nama’am kwanekwan ana orot ukwarin namatabir nan natit.
51 Yóò sì jẹ ẹ́ ní ìyà gidigidi, yóò sì rán an sí ibùgbé àwọn àgàbàgebè, níbẹ̀ ni ẹkún àti ìpayínkeke yóò wà.
51 Naatu orot ukwarin nati ana akir wairafin boro nab narab ufun narauwatait, sabuw afa wanawanah rerekabih bairi baimakiy kakafin hinab hinama hinarerey wah takitak niwa’an.

Ler em outra tradução

Comparar com outra

Estude este capítulo no WhatsApp

Peça à IA da Bíblia Fala para explicar Mateus 24, comparar traduções ou montar um estudo — tudo direto pelo WhatsApp.