Mateus 10
Biblica® ní oore ọ̀fẹ́ láti lo Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde-Òní (YOR) vs AAI
1 Jesu sì pe àwọn ọmọ-ẹ̀yìn rẹ̀ méjìlá sí ọ̀dọ̀; ó fún wọn ní àṣẹ láti lé ẹ̀mí àìmọ́ jáde àti láti ṣe ìwòsàn ààrùn àti àìsàn gbogbo.
1 Jesu ana bai’ufununayah etei 12 eaf ayuwih hina, sawow yumatah ta ta, feher yumatah ta ta, sabuw biyahimaim baiyawasih isan fair itih naatu igegewasinih.
2 Orúkọ àwọn aposteli méjèèjìlá náà ni wọ̀nyí:
2 Naatu iti i bai’ufununayah nah 12 wabih, wantoro’ot i Simon wabin ta Peter tufuturan Andrew hairi, James tufuturan John hairi, orot Zebedee natunatun.
3 Filipi àti Bartolomeu;
3 Philip, Bartholomew hairi, kabay onayan wabin Matthew i Thomas hairi, naatu Alpheus natun James i Thaddeus hairi,
4 Simoni ọmọ ẹgbẹ́ Sealoti, Judasi Iskariotu, ẹni tí ó da Jesu.
4 tafaram kafafarayan orot wabin Simon. Jesu ana yanuwayan orot Judas Iscariot hairi.
5 Àwọn méjèèjìlá wọ̀nyí ni Jesu ran, ó sì pàṣẹ fún wọn pé, “Ẹ má ṣe lọ sì ọ̀nà àwọn kèfèrí, ẹ má ṣe wọ̀ ìlú àwọn ará Samaria.
5 Orot nah 12 Jesu iyunih hititit iuwih eo, “Ufun Sabuw hai tafaramamaim men kwanan naatu Samaria sabuw hai bar hai meraramaim men kwanarun.
6 Ẹ kúkú tọ̀ àwọn àgùntàn ilé Israẹli tí ó nù lọ.
6 Baise kwanan Israel sabuw bobaituw na’atube hikasiy tema’am biyahimaim kwanarun kwaniyawasih.
7 Bí ẹ̀yin ti ń lọ, ẹ máa wàásù yìí wí pé, ‘Ìjọba ọ̀run kù sí dẹ̀dẹ̀.’
7 Kwanan iti tur i kwanabinan, Mar ana aiwob i na iyubinaka.
8 Ẹ máa ṣe ìwòsàn fún àwọn aláìsàn, ẹ si jí àwọn òkú dìde, ẹ sọ àwọn adẹ́tẹ̀ di mímọ́, kí ẹ sì máa lé àwọn ẹ̀mí èṣù jáde. Ọ̀fẹ́ ni ẹ̀yin gbà á, ọ̀fẹ́ ni kí ẹ fi fún ni.
8 Sawusawuwih kwaniyawasih, murumurubih kwanao hinamisir, sabuw iyab biyah kokom ani’anih kwaniyawasih naatu demon kakafih kwananunih hinatit. Sawar ana baiyan en kwabaib, imih kwanabow ana baiyan en.
9 “Ẹ má ṣe mú wúrà tàbí fàdákà tàbí idẹ sínú àpò ìgbànú yín,
9 Men kabay ta kwanab a koukut kwaniwan, naiw a kikiramaim kwanarobere auman kwananamih.
10 ẹ má ṣe mú àpò fún ìrìnàjò yín, kí ẹ má ṣe mú ẹ̀wù méjì, tàbí bàtà, tàbí ọ̀pá; oúnjẹ oníṣẹ́ yẹ fún un.
10 Remor isan men hafoy ta kwanab, men biya baibiyon ta, a baibiyon ta, tu ta, kwanabow auman kwananamih. anayabin bowayah abis kikimin tibitin boro nakaram.
11 Ìlúkílùú tàbí ìletòkíletò tí ẹ̀yin bá wọ̀, ẹ wá ẹni ti ó bá yẹ níbẹ̀ rí, níbẹ̀ ni kí ẹ sì gbé nínú ilé rẹ̀ títí tí ẹ̀yin yóò fi kúrò níbẹ̀.
11 “Kwanan bar merar kikimin o bar merar gagamin kwanarur, sabuw iyab merarayow wairafih kwananuwihih, naatu i hai baremaim kwanama, a bowabow kwanisawar imaibo kwihamiyih kwanan.
12 Nígbà tí ẹ̀yin bá sì wọ ilé kan, ẹ kí i wọn.
12 Naatu bar runamih sabuw a merarayow kwanitih.
13 Bí ilé náà bá sì yẹ, kí àlàáfíà yín kí ó bà sórí rẹ̀; ṣùgbọ́n bí kò bá yẹ, kí àlàáfíà yín kí ó padà sọ́dọ̀ yín.
13 Naatu sabuw bar wanawanan tufuw ana merarayow hinabaib, basit a merarayow kwanihamiy nati baremaim nama, baise men hinabaib a tufuw ana merarayow kwanabosair kwanab maiye.
14 Bí ẹnikẹ́ni tí kò bá sì gbà yín, tàbí tí kò gba ọ̀rọ̀ yín, ẹ gbọn eruku ẹ̀ṣẹ̀ yín sílẹ̀ tí ẹ bá ń kúrò ní ilé tàbí ìlú náà.
14 Orot babin yait a merar men nay naatu a tur men nanonowar, kwanamisir ura kwanarutatab efan nati kwanihamiy kwanan efan ta.
15 Lóòótọ́ ni mo wí fún yín, yóò sàn fún ìlú Sodomu àti Gomorra ní ọjọ́ ìdájọ́ ju àwọn ìlú náà lọ.
15 Anababatun a tur ao’owen, baibatebat ana veya God Sodom, Gomorah sabuw boro nakabibirih, baise nati bar merar sabuw hai baimakiy i boro God tafan nayara’ah gagamin na’in hinab.
16 “Mò ń rán yín lọ gẹ́gẹ́ bí àgùntàn sáàrín ìkookò. Nítorí náà, kí ẹ ní ìṣọ́ra bí ejò, kí ẹ sì ṣe onírẹ̀lẹ̀ bí àdàbà.
16 “Kwananowar, kwa i bobaituw sheep na’atube haru fairih wanawanahimaim abiyuni kwanatit kwananamih, imih kok na’atube kwanakakaf naatu mamu imak na’atube kwananutanub.
17 Ẹ ṣọ́ra lọ́dọ̀ àwọn ènìyàn nítorí wọn yóò fi yín le àwọn ìgbìmọ̀ ìgbèríko lọ́wọ́ wọn yóò sì nà yín nínú Sinagọgu.
17 “Mata toniwa’an sabuw isah, anayabin boro hinabuw hinafatumi kwanan kanisel nahimaim hibabatiy, naatu Kou’ay Baremaim boro hinaborabirabi.
18 Nítorí orúkọ mi, a ó mú yín lọ síwájú àwọn baálẹ̀ àti àwọn ọba, bí ẹlẹ́rìí sí wọn àti àwọn aláìkọlà.
18 Ayu wabu’umaim kwabowabow isan boro aiwob sabuw naatu gawan orot gagamih na’atube Ufun Sabuw nahimaim Tur Gewasin kurereb nowar isan boro hinarab hinataini.
19 Nígbà tí wọ́n bá mú yín, ẹ má ṣe ṣàníyàn ohun tí ẹ ó sọ tàbí bí ẹ ó ṣe sọ ọ́. Ní ojú kan náà ni a ó fi ohun tí ẹ̀yin yóò sọ fún yín.
19 Baise hinafatum hinabuw baibabatiyimih kwanan men kwaniyababan tur isan, o tur o isan, hinabibatiy ana veya’amaim tur boro imaim natit kwanao.
20 Nítorí pé kì í ṣe ẹ̀yin ni ó sọ ọ́, bí kò ṣe Ẹ̀mí Baba yín tí ń sọ̀rọ̀ nípasẹ̀ yín.
20 Anayabin nati tur i men o a notamaim tit kuo’omih, baise Tamat Anunin o iwani awa rukirir kuo.
21 “Arákùnrin yóò sì fi arákùnrin fún pípa. Baba yóò fi àwọn ọmọ rẹ̀ fún ikú pa. Àwọn ọmọ yóò ṣọ̀tẹ̀ sí òbí wọn, wọn yóò sì mú kí a pa wọ́n.
21 “Orot ain boro tain baban nao namorob, regah boro natun nifa’ifa’i baban nao namorob, na’atube kek boro hinah tamah hinifa’ifa’ih babah hinao hinamorob.
22 Gbogbo ènìyàn yóò sì kórìíra yín nítorí mi, ṣùgbọ́n gbogbo ẹni tí ó bá dúró ṣinṣin dé òpin ni a ó gbàlà.
22 Ayu wabu’umaim kwabowabow isan sabuw boro hinifa’ifa’i, baise orot yait nabat kikin nabowabow yomaninamaim boro yawas natita’ur.
23 Nígbà tí wọn bá ṣe inúnibíni sì i yín ní ìlú kan, ẹ sálọ sì ìlú kejì. Lóòótọ́ ni mo wí fún yín, ẹ̀yin kò tì í le la gbogbo ìlú Israẹli já tán kí Ọmọ Ènìyàn tó dé.
23 Bar merar ta’amaim hinarukoukuw kwanabia’akir, kwanabihir kwanan bar merar ta, anababatun a tur ao’owen, Israel wanawanan bar merar etei boro men kwanabow kwanisawaribo Orot Natun namatabir maiye nanamih.
24 “Akẹ́kọ̀ọ́ kì í ju olùkọ́ rẹ̀ lọ, bẹ́ẹ̀ ni ọmọ ọ̀dọ̀ kì í ju ọ̀gá rẹ̀ lọ.
24 “Kirum kek boro men ana bai’obaiyen orot na natabirimih, na’atube akir wairafin boro men ana orot ukwarin na natabirimih.
25 Ó tọ́ fún akẹ́kọ̀ọ́ láti dàbí olùkọ́ rẹ̀ àti fún ọmọ ọ̀dọ̀ láti rí bí ọ̀gá rẹ̀. Nígbà tí wọ́n bá pe baálé ilé ní Beelsebulu, mélòó mélòó ni ti àwọn ènìyàn ilé rẹ̀!
25 Baise kirum kek na kok ana bai’obaiyen orot na’atube mataramih, basit i ukwarin na rerekab na kirum gewas, na’atube akir wairafin nabow gewas ana orot ukwarin boro nayara’ah ibe namatar, baise bar matuwan orot isan Beelzebul hinarouw hinao na’at, i ana akir wairafin isah boro tur kakafin maiyow hina’uwih wabih hini’a’afiy.
26 “Nítorí náà, ẹ má ṣe bẹ̀rù wọn, nítorí kò sí ohun tó ń bọ̀ tí kò ní í fi ara hàn, tàbí ohun tó wà ní ìkọ̀kọ̀ tí a kò ní mọ̀ ni gbangba.
26 “Baise sabuw isah men kwanabir, anayabin abisa sum wanawanan wa’iwa’irin inu’in boro hina botait nirereb, naatu sawar baibunuwenamaim ti’inu’in etei boro hinatit hinibebeyan sabuw etei hinaso’ob.
27 Ohun tí mo bá wí fún yín ní òkùnkùn, òun ni kí ẹ sọ ní ìmọ́lẹ̀. Èyí tí mo sọ kẹ́lẹ́kẹ́lẹ́ sì etí yín ni kí ẹ kéde rẹ́ lórí òrùlé.
27 Abisa wa’iwa’iramaim ao kwanonowar sabuw etei nahimaim kwanao hinanowar, naatu abisa akisimo ao kwanonowar, kwanayen gem tafahimaim kwanabat kwanabinan sabuw etei hinanowar.
28 Ẹ má ṣe bẹ̀rù àwọn tí ó le pa ara nìkan; ṣùgbọ́n tí wọn kò lè pa ẹ̀mí. Ẹ bẹ̀rù Ẹni tí ó le pa ẹ̀mí àti ara run ní ọ̀run àpáàdì.
28 Sabuw biya te’a’asabun isan men kwanabirumih, anayabin anun boro men hina’asabunimih, baise God isan i kwanabir, anayabin i boro biya naatu anun hairi’ika na’asbunuwen hinamorob.
29 Ológoṣẹ́ méjì kọ́ ni à ń tà ní owó idẹ wẹ́wẹ́ kan? Síbẹ̀ kò sí ọ̀kan nínú wọn tí yóò ṣubú lu ilẹ̀ lẹ́yìn Baba yin.
29 Mamu kwikwik rou’ab hai baiyan i one toea’maim boro inatubun, baise mamu ta boro men Tamat so’oba’e namorob haw nare’emih.
30 Àti pé gbogbo irun orí yín ni a ti kà pé.
30 Naatu kwa ukwarimaim arib i etei God iyab sawar.
31 Nítorí náà, ẹ má ṣe fòyà; ẹ̀yin ní iye lórí ju ọ̀pọ̀ ológoṣẹ́ lọ.
31 Imih men kwanabir, Tamat ana yabow kwa isa i ra’at men mamu kwikwik na’atube’emih.
32 “Ẹnikẹ́ni tí ó bá jẹ́wọ́ mi níwájú ènìyàn, òun náà ni èmi yóò jẹ́wọ́ rẹ̀ níwájú Baba mi ní ọ̀run.
32 “Orot yait sabuw etei nahimaim ayu isou eo’orereb, ayu auman boro maramaim na’atube ana sinaf Tamai nanamaim.
33 Ṣùgbọ́n ẹni tí ó bá sẹ́ mí níwájú àwọn ènìyàn, òun náà ni èmi náà yóò sọ wí pé n kò mọ̀ níwájú Baba mi ní ọ̀run.
33 Baise orot babin yait sabuw etei nahimaim ayu ekwakwahiru, ayu auman mar Tamai nanamaim boro ibo anakwahir.
34 “Ẹ má ṣe rò pé mo mú àlàáfíà wá sí ayé, Èmi kò mú àlàáfíà wá bí kò ṣe idà.
34 “Men kwananot ayu i tufuw abai tafaramamaim anan, En. Ayu i men tufuw abai ananamih, baise kauseb abai anan.
35 Nítorí èmi wá láti ya
35 Ayu anan anayabin
36 Ará ilé ènìyàn ni yóò sì máa ṣe ọ̀tá rẹ̀.’
36 Imih orot ana kamabiy anababatun i boro i taiyuwin ana rara.’
37 “Ẹni tí ó bá fẹ́ baba rẹ̀ tàbí ìyá rẹ̀ jù mí lọ, kò yẹ ní tèmi, ẹni tí ó ba fẹ́ ọmọkùnrin tàbí ọmọbìnrin rẹ̀ jù mí lọ, kò yẹ ní tèmi.
37 “Orot yait ana yabow ayu isou ikikimin naatu hinah tamah isah ebiyabow kwanekwan i men karam boro ni’ufnunu, na’atube orot yait ana yabow ayu isou ikikimin naatu i natun orot naatu babitai isah ebiyabow kwanekwan, i men karam boro ni’ufnunu.
38 Ẹni tí kò bá gbé àgbélébùú rẹ̀ kí ó tẹ̀lé mi kò yẹ ní tèmi.
38 Naatu orot babin yait ana onaf men na’abar ayu nabi’ufnunu i men karam boro ayu airi ani’of.
39 Ẹni tí ó bá wa ẹ̀mí rẹ̀ yóò sọ ọ́ nù, ṣùgbọ́n ẹni tí ó bá sọ ẹ̀mí rẹ̀ nú nítorí tèmi ni yóò rí i.
39 Orot babin yait taiyuwin ana yawas enunuwih boro ana yawas nikasiy, baise orot babin yait ana yawas isou ebi’inuw boro natita’ur.
40 “Ẹni tí ó bá gbà yín, ó gbà mí, ẹni tí ó bá sì gbà mí gba ẹni tí ó rán mi.
40 “Orot yait kwa a merar eyiyi, ayu au merar eyiyi, naatu orot yait ayu au merar eyiyi, i orot yait ayu iyunu anan i ana merar eyiyi.
41 Ẹni tí ó ba gba wòlíì, nítorí pé ó jẹ́ wòlíì yóò jẹ èrè wòlíì, ẹni tí ó bá sì gba olódodo nítorí ti ó jẹ́ ènìyàn olódodo, yóò jẹ èrè olódodo.
41 Orot babin yait dinab orot ana merar eyiyi, anayabin i dinab orot, nati orot boro dinab orot ana baiyan turin nab. Naatu orot yait, orot ana yawas mutufurin ana merar eyiy, anayabin i orot ana yawas mutufurin boro orot ana yawas mutufurin ana baiyan turin nab.
42 Ẹnikẹ́ni tí ó bá fi ago omi tútù fún ọ̀kan nínú àwọn onírẹ̀lẹ̀ wọ̀nyí mu nítorí tí ó jẹ́ ọmọ-ẹ̀yìn mi, lóòótọ́ ni mo wí fún yín, kò ní pàdánù èrè rẹ̀.”
42 Naatu orot babin yait kek kikimin harewawat hun itin etomatom, anayabin i ayu au bai’ufununayan, anababatun a tur ao’owen i ana baiyan boro nab.”
Atalhos do teclado
- Capítulo anterior←
- Próximo capítulo→
- Versículo anteriork
- Próximo versículoj
- Limpar seleçãoEsc
- Esta ajuda?
Estude este capítulo no WhatsApp
Peça à IA da Bíblia Fala para explicar Mateus 10, comparar traduções ou montar um estudo — tudo direto pelo WhatsApp.