Marcos 13

Biblica® ní oore ọ̀fẹ́ láti lo Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde-Òní (YOR) vs AAI

Sair da comparação
AAI TUR GEWASIN O BAIBASIT BOUBUN
1 Bí Jesu ti ń jáde láti inú tẹmpili ní ọjọ́ náà, ọ̀kan nínú ọmọ-ẹ̀yìn rẹ̀ sọ fún un pé, “Olùkọ́, wo ilé ńlá tí ó dára wọ̀nyí. Sì wo òkúta tí a ṣe lọ́ṣọ̀ọ́ lára àwọn ògiri ilé náà.”
1 Jesu Tafaror Bar bihamiy ana veya, ana bai’ufununayah orot ta eo, “Bai’obaiyenayan kwi’itin! Kabay gewagewasin maiyow naatu bar hiwowowab ana’itin gewasin maiyow.”
2 Jesu dáhùn pé, “Ìwọ rí ilé ńlá wọ̀nyí? Kì yóò sí òkúta kan tí a ó fi sílẹ̀ lórí èkejì tí a kì yóò wó lulẹ̀.”
2 Jesu iya’afut eo, “Iti bar gagamin kwi’i’itin boro men kafa’imo kabay ta ana efanamaim kwana’itinimih, etei boro nihururuw nara’iy nasawar.”
3 Bí Jesu si ti jókòó lórí òkè olifi tí ó kọjú sí tẹmpili, Peteru, Jakọbu, Johanu àti Anderu wà pẹ̀lú rẹ̀ níbẹ̀, wọ́n bi í léèrè ni ìkọ̀kọ̀ pé,
3 Jesu yen in Olive Oyaw tafan Tafaror Bar batabat rounane imaim mare ma’am basit Peter, James, John naatu Andrew wa’iwa’iramaim hina biyan hitit,
4 “Sọ fún wa, nígbà wo ni nǹkan wọ̀nyí yóò ṣẹlẹ̀ sí tẹmpili náà? Kí ni yóò sì jẹ́ àmì nígbà tí gbogbo nǹkan wọ̀nyí yóò ṣẹ?”
4 hibatiy, “Kuo anowar mar boro biy iti sawar hinamatar? Naatu ina’inanen boro abisa ni’obaiyi ana so’ob veya ina ebiyubin.”
5 Jesu kìlọ̀ fún wọn pé, “Ẹ má ṣe jẹ́ kí ẹnikẹ́ni tàn yín.
5 Imaibo Jesu hai tur eowen eo, “Mata toniwa’an men yait ta nan nikubibiruwimih.
6 Nítorí pé ọ̀pọ̀lọpọ̀ yóò wá ní orúkọ mi, wọn yóò wí pé, ‘Èmi ni Kristi,’ wọn yóò tan ọ̀pọ̀ ènìyàn jẹ.
6 Sabuw moumurih na’in boro ayu wabu’umaim hinao, ‘Ayu’uban iti!’ Naatu moumurih maiyow boro hinanawiyih hai ef hinasair.
7 Nígbà tí ẹ̀yin bá ń gbọ́ ìró ogun àti ìdágìrì ogun, kí ẹ̀yin má ṣe jáyà, nítorí irú nǹkan wọ̀nyí kò le ṣe kí ó má ṣẹlẹ̀, ṣùgbọ́n òpin náà kì í ṣe ìgbà yìí.
7 Baiyow nidun iti yubinamaim o ef yokamaim kwananonowar men kwanabir, sawar iti na’atube boro hinamatar, baise men kwananot mar yomanin i natit.
8 Orílẹ̀-èdè yóò dìde sí orílẹ̀-èdè, àti ìjọba sí ìjọba ilẹ̀ yóò máa jì ní ibi púpọ̀. Ìyàn yóò sì wà níbi gbogbo. Gbogbo nǹkan wọ̀nyí ni ìbẹ̀rẹ̀ ìpọ́njú tí ń bọ̀ níwájú.
8 Tafaram ta boro namisir tafaram ta hairi hiniyow, aiwob ta boro aiwob ta hairi hiniyow. Nati’imaim iriyoy tafaram etei boro nab, naatu baimar kakafin boro namatar. Iti sawar hinamamatar i babin taubumih kek ebobotukwar na’atube.
9 “Ṣùgbọ́n nígbà tí àwọn nǹkan wọ̀nyí bá bẹ̀rẹ̀ sí i ṣẹlẹ̀, ẹ kíyèsára! Nítorí ẹ̀yin yóò wà nínú ewu. Wọn yóò fà yín lọ ilé ẹjọ́ gbogbo. Wọn yóò fi ìyà jẹ yín nínú Sinagọgu wọn. Àwọn ènìyàn yóò fẹ̀sùn kàn yín níwájú àwọn baálẹ̀ àti níwájú àwọn ọba nítorí orúkọ mi, fún ẹ̀rí fún wọn.
9 Kwa i kwanakaifi gewas mata toniwa’an, kwa boro hinafatumi naatu hinabuwi kwanan baibabatiyi isan, Kou’ay Baremaim boro hinaborabirabi, bonawiyenayah hai ukwarih naatu aiwob nahimaim kwanabat ayu wabu’umaim tur Gewasin hai tur kwana’owen.
10 Nítorí pé ẹ gbọdọ̀ kọ́kọ́ wàásù ìyìnrere náà fún gbogbo orílẹ̀-èdè kí òpin tó dé.
10 Baise wan tur gewasin tafaram wanawanan sabuw etei isah kwanabinan.
11 Ṣùgbọ́n nígbà tí wọ́n bá ń fà yín lọ, tí wọ́n bá sì ń fi yín lé wọn lọ́wọ́, ẹ má ṣe ṣàníyàn ṣáájú ohun tí ẹ ó sọ. Ṣùgbọ́n ohun tí bá fi fún yín ní wákàtí náà, òun ni kí ẹ̀yin kí ó wí. Nítorí kì í ṣe ẹ̀yin ni ó ń wí, bí kò ṣe Ẹ̀mí Mímọ́.
11 Naatu hinafatumi baibabatiy isan kwananan men tur isan kwaniyababan kwanabirumih, tur o ana veya abisa a notamaim etitit i kwanao, anayabin men kwa kwao’omih, baise Anun Kakafiyin.
12 “Arákùnrin yóò máa fi ẹ̀sùn kan arákùnrin rẹ̀, tí yóò sì yọrí sí ikú. Baba yóò máa ṣe ikú pa ọmọ rẹ̀. Àwọn ọmọ yóò máa dìtẹ̀ sí òbí wọn. Àní, àwọn ọmọ pẹ̀lú yóò máa ṣe ikú pa òbí wọn.
12 “Oro’orot boro taiyuwih taituwah babah hinao hinamorob, regaregah boro natunatuh babah hinao hinamorob, kek boro hinitafasar hinah tamah babah hinao hinamorob.
13 Àwọn ènìyàn yóò kórìíra yín nítorí tí ẹ jẹ́ tèmi. Ṣùgbọ́n ẹni tó bá fi ara da ìyà títí dé òpin tí kò sì kọ̀ mí sílẹ̀ òun ni yóò rí ìgbàlà.
13 Sabuw etei boro hinifa’ifa’i anayabin ayu isou, baise orot yait nabatabatkikin yomaninamaim boro yawas nab.
14 “Ṣùgbọ́n nígbà tí ẹ̀yin bá rí ìríra ìsọdahoro, tí ó dúró níbí tí kò yẹ (ẹnikẹ́ni tí ó bá kà á kí ó yé e), nígbà náà ni kí àwọn tí ń bẹ ni Judea sálọ sí orí òkè.
14 “Gurugurusen ana sawar itinin birubir kakafin marasika nati’imaim men batabat boro nabatabat kwana’i’itin ana veya, sabuw iyab Judea tema’am boro hinabihir hin oyawamaim hinatit, o yait kubiyab iti tur anayabin i naso’ob.
15 Kí ẹni ti ń bẹ lórí ilé má ṣe sọ̀kalẹ̀ lọ sínú ilé, bẹ́ẹ̀ ni kí ó má sì ṣe wọ inú rẹ̀, láti mú ohunkóhun jáde nínú ilé rẹ̀.
15 Orot yait ana bar afe’en ema’am men narubir o nare ana bar wanawanan narun ana sawar nabow.
16 Kí ẹni tí ó wà lóko má ṣe padà sẹ́yìn láti wá mú aṣọ rẹ̀.
16 Orot yait ma masaw ebob men namatabir bar ana faifuw nabaimih,
17 Ègbé ní fún àwọn tí ó lóyún, àti fún obìnrin tí ń fún ọ́mọ lọ́mú ní ọjọ́ wọ̀nyí.
17 Nati ana veya’amaim baibin iyab yah auman naatu kek tibitotomanen boro yababan gagamin maiyow hinab!
18 Kí ẹ sì máa gbàdúrà pé èyí ṣẹlẹ̀ ní àkókò òtútù.
18 Kwanayoyoban saise iti sawar men yakukur ana veya namatar.
19 Nítorí ọjọ́ wọ̀n-ọn-nì yóò jẹ́ àkókò ìpọ́njú, irú èyí tí kò ì ṣẹlẹ̀ láti ìbẹ̀rẹ̀ ẹ̀dá Ọlọ́run. Irú rẹ̀ kò sì ni ṣẹlẹ̀ mọ́.
19 Anayabin iti bai’akir kakafin boun emamatar i aneika God tafaram bimatar iti na’atube men matar naatu boro men namatar maiye.
20 “Àfi tí Olúwa bá gé àkókò ìjìyà náà kúrú, ẹyọ ẹ̀mí kan ní ayé kì yóò là. Ṣùgbọ́n nítorí àwọn tí Ọlọ́run yàn, ni yóò ṣe dín àwọn ọjọ́ náà kù.
20 Baise Regah nati veya men tayayakabum na’at, sabuw boro men yawas hitab, baise i ana sabuw rurubiniyih isah iti veya yakabum.
21 Nígbà náà, bí ẹnikẹ́ni bá sọ fún un yín pé, ‘Ẹ wò ó, Kristi wa níbi yìí!’ tàbí, sọ fún un yín pé, ‘Ẹ wò ó, ó wà lọ́hùn ún nì!’ Ẹ má ṣe gbà wọ́n gbọ́.
21 Naatu nati ana veya orot yait isa nao, ‘Kwanuw Keriso enan kwa’itin’, o iban ‘Iti ema’am!’ Men kwanitumitum.
22 Nítorí àwọn èké Kristi àti àwọn wòlíì èké ni yóò wá, wọn yóò sì fi iṣẹ́ ìyanu tí yóò tan ènìyàn jẹ hàn. Bí ó bá ṣe é ṣe, wọn yóò tan àwọn àyànfẹ́ pàápàá jẹ.
22 Anayabin Keriso na’atube naatu dinab orot na’atube boro hinatit ina’inan ta ta, naatu baifofofor fairih hinasinaf sabuw hinabonawiyih hai ef hinasair, naatu hai ef nama’am na’at God ana roubinen sabuw auman boro hai ef hinawasa’ir.
23 Nítorí náà, ẹ ṣọ́ra. Mo ti kìlọ̀ fún un yín ṣáájú tó!
23 Sawar iti etei isah ao kwanonowarabo namatar, imih kwanakaifi gewas!
24 “Ṣùgbọ́n ni ọjọ́ wọ̀nyí lẹ́yìn ìpọ́njú tí mo sọ yìí,
24 Baise nati bai’akir hinamamatar ana veya,
25 Àwọn ìràwọ̀ pẹ̀lú yóò já lulẹ̀ láti ojú ọ̀run,
25 daman auyomane boro hinihururuw hinare,
26 “Nígbà náà ni gbogbo ayé yóò sì rí i tí èmi Ọmọ Ènìyàn yóò máa bọ̀ wá láti inú àwọsánmọ̀ pẹ̀lú agbára àti ògo ńlá.
26 “Nati ana veya’amaim Orot Natun boro kasakasaw wanawananamaim nanan kwana’itin ana fair bonamanamarin auman.
27 Nígbà náà ni yóò sì rán àwọn angẹli rẹ̀ láti kó àwọn àyànfẹ́ ní gbogbo ayé jọ láti orígun mẹ́rẹ̀ẹ̀rin ayé láti ìkangun ayé títí dé ìkangun ọ̀run.
27 I boro ana tounamatar niyafarih hinatit tafaram tutufin wanawanan ana huhun etei kwafe’en imaim hinarun hinatit God ana roubiniyen sabuw hinabow hinan yomanin hinatit.
28 “Nísinsin yìí, ẹ kọ́ òwe lára igi ọ̀pọ̀tọ́, nígbà tí ẹ̀ka rẹ bá ń yọ tuntun, tí ó bá sì ń rú ewé, èyí fihàn pé àkókò ẹ̀rùn ti dé.
28 “Ai fofou rourinamaim ebi’obaiyi kwana’itin, ai famefamenamaim rourin narusasar kwana’i’itin kwa boro kwanao ai abeb ana veya tit,
29 Bẹ́ẹ̀ gẹ́gẹ́, nígbà tí ẹ ba ri àwọn ohun wọ̀nyí ti n ṣẹlẹ̀, kí ẹ mọ̀ pé ó súnmọ́ etílé tán, bi ìgbà tí ó wà lẹ́yìn ìlẹ̀kùn.
29 ef i nati ta’imon sawar iti hinamatar kwana’i’itin, kwa i kwanaso’ob veya i nakabom, iyubin etawan awan ebatabat.
30 Lóòótọ́ ni mo wí fún un yín, ìran yìí kì yóò rékọjá títí a ó fi mú gbogbo nǹkan wọ̀nyí ṣẹ.
30 Anababatun a tur ao’owen, sabuw iti tema’am boro hinama’am sawar namatar hina’itinibo hinamorob.
31 Ọ̀run àti ayé yóò kọjá lọ, ṣùgbọ́n àwọn ọ̀rọ̀ mi dúró dájú títí ayé àìnípẹ̀kun.
31 Mar tafaram boro nasawar, baise ayu au tur boro men nasawar.”
32 “Ṣùgbọ́n kò sí ẹni tí ó mọ ọjọ́ tàbí wákàtí tí nǹkan wọ̀nyí yóò ṣẹlẹ̀. Àwọn angẹli ọ̀run pàápàá kò mọ̀. Àní, èmi pẹ̀lú kò mọ̀ ọ́n, bí kò ṣe baba nìkan.
32 “Men yait ta veya o fur so’obamih, tounamatar no maramaim na’atube i Natun, baise Tamah akisinamo so’ob.
33 Ẹ máa ṣọ́ra, ẹ dúró wámú, kí ẹ sì máa gbàdúrà, nítorí ẹ̀yin kò mọ ìgbà tí àkókò ná yóò dé.
33 Mata toniwa’an kwanabat yewayew, anayabin veya men kwaso’ob mar biy boro namatar.
34 Ó dà bí ọkùnrin kan tí ó lọ sí ìrìnàjò tí ó jìnnà rere, ẹni tí ó fi ilé rẹ̀ sílẹ̀, tí ó sì fi àṣẹ fún àwọn ọmọ ọ̀dọ̀ rẹ̀, àti iṣẹ́ tí ẹnìkọ̀ọ̀kan yóò ṣe, ó sì fi àṣẹ fún ẹni tó dúró lẹ́nu-ọ̀nà láti máa ṣọ́nà.
34 Ana itinin i nanawan orot na’atube, orot bainanawanamih ana’akir wairafih boro ta’ita’imon bowabow nitih. Naatu orot etawan kaifin isan ya’iyai boro nau, matan toniwa’an etawan nakaif nama.
35 “Bẹ́ẹ̀ gẹ́gẹ́, ẹ̀yin pẹ̀lú ní láti máa fi ìrètí ṣọ́nà, nítorí pé ẹ kò mọ àkókò tí baálé ilé yóò dé. Bóyá ní ìrọ̀lẹ́ ni o, tàbí ní ọ̀gànjọ́ òru, tàbí nígbà tí àkùkọ máa ń kọ, tàbí ní òwúrọ̀.
35 Imih mata toniwa’an, anayabin kwa men kwaso’ob orot bar matuwan i boro biy namatabir, rabirab nan, o fai inusabobor, kwasiy hinao ana veya, o yasi’uw,
36 Àti wí pé nígbà tí ó bá dé lójijì, kó má ṣe bá yín lójú oorun.
36 naniyan meyemeye natitit na’at men kwana’inu’in natitamih.
37 Ohun tí mo wí fún un yín, mo wí fun gbogbo ènìyàn: ‘Ẹ máa ṣọ́nà!’ ”
37 Abisa au’uwi, i sabuw etei isah ao’o, ‘Mata toniwa’an!’”

Ler em outra tradução

Comparar com outra

Estude este capítulo no WhatsApp

Peça à IA da Bíblia Fala para explicar Marcos 13, comparar traduções ou montar um estudo — tudo direto pelo WhatsApp.