Levítico 14

Biblica® ní oore ọ̀fẹ́ láti lo Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde-Òní (YOR) vs BKJ

Sair da comparação
1 Olúwa sọ fún Mose pé,
1 E o SENHOR falou a Moisés, dizendo:
2 “Èyí ni àwọn ìlànà fún ẹni tí ààrùn ẹ̀tẹ̀ bá mú ní àkókò ìwẹ̀nùmọ́ rẹ̀, bí a bá mú un tọ àlùfáà wá.
2 Esta será a lei do leproso no dia da sua purificação: ele será trazido ao sacerdote;
3 Kí àlùfáà yẹ̀ ẹ́ wò ní ẹ̀yìn ibùdó bí ara rẹ̀ bá ti yá kúrò nínú ààrùn ẹ̀tẹ̀ náà.
3 e o sacerdote sairá do acampamento, e o sacerdote o examinará; e eis que, se a praga de lepra estiver curada no leproso,
4 Kí àlùfáà pàṣẹ pé kí a mú ààyè ẹyẹ mímọ́ méjì, igi kedari, òdòdó àti ẹ̀ka hísópù wá fún ẹni tí a fẹ́ wẹ̀mọ́.
4 então o sacerdote ordenará que se tome para aquele que se houver de purificar duas aves vivas e limpas, e madeira de cedro, e escarlate, e hissopo;
5 Kí àlùfáà pàṣẹ pé kí wọn pa ọ̀kan nínú àwọn ẹyẹ náà sórí omi tí ó mọ́ tó wà nínú ìkòkò amọ̀.
5 e o sacerdote ordenará que se mate uma das aves num vaso de barro sobre águas correntes;
6 Lẹ́yìn náà kí ó ri ààyè ẹyẹ pẹ̀lú igi kedari, òdòdó àti ẹ̀ka hísópù bọ inú ẹ̀jẹ̀ ẹyẹ tí a ti pa sínú omi náà.
6 e quanto a ave viva, ele a tomará, e a madeira de cedro, e a escarlate, e o hissopo e os molhará com a ave viva no sangue da ave que foi morta sobre as águas correntes;
7 Ìgbà méje ni kí o wọ́n omi yìí sí ara ẹni tí a fẹ́ wẹ̀mọ́ kúrò nínú ààrùn ara náà kí ó ju ààyè ẹyẹ náà sílẹ̀ ní ìta gbangba.
7 e ele espargirá sobre aquele que há de purificar-se da lepra sete vezes; e o declarará limpo, e soltará a ave viva em campo aberto.
8 “Ẹni tí a fẹ́ wẹ̀mọ́ náà gbọdọ̀ fọ aṣọ rẹ̀, fá gbogbo irun rẹ̀, kí ó sì wẹ̀, lẹ́yìn èyí ó ti di mímọ́. Lẹ́yìn náà ó le wá sínú ibùdó ṣùgbọ́n kí ó wà lẹ́yìn àgọ́ rẹ̀ ní ọjọ́ méje.
8 E aquele que tem de purificar-se lavará as suas vestes, e rapará todo o seu cabelo, e se lavará com água, para que ele possa ser limpo; e depois ele entrará no acampamento, e ficará fora da sua tenda por sete dias.
9 Kí ó fá gbogbo irun rẹ̀ ní ọjọ́ keje: irun orí rẹ̀, irùngbọ̀n rẹ̀, irun ìpéǹpéjú rẹ̀, àti gbogbo irun rẹ̀ tókù. Kí ó fọ aṣọ rẹ̀, kí ó sì wẹ̀, yóò sì mọ́.
9 Mas será que, ao sétimo dia, ele raspará todo o seu cabelo de sua cabeça, e sua barba, e as sobrancelhas; e ele rapará todo o cabelo, e lavará as suas vestes, e ele também lavará a sua carne com água, e será limpo.
10 “Ní ọjọ́ kẹjọ kí ó mú àgbò aláìlábùkù méjì àti abo ọ̀dọ́-àgùntàn ọlọ́dún kan tí wọn kò ní àlébù wá, pẹ̀lú ìdámẹ́wàá nínú mẹ́wàá òsùwọ̀n ìyẹ̀fun tí à pòpọ̀ mọ́ òróró fún ọrẹ ohun jíjẹ àti òsùwọ̀n lógù òróró kan.
10 E no oitavo dia ele tomará dois cordeiros sem defeito, e uma cordeira de um ano sem defeito, e três dízimas de farinha fina para oferta de alimentos, misturada com óleo, e um logue de óleo.
11 Àlùfáà tí ó pè é ní mímọ́, yóò mú ẹni náà tí a ó sọ di mímọ́ àti ọrẹ rẹ̀ wá síwájú Olúwa ní ẹnu-ọ̀nà àgọ́ ìpàdé.
11 E o sacerdote que faz sua purificação apresentará o homem que houver de purificar-se com estas coisas perante o SENHOR, à porta do tabernáculo da congregação;
12 “Kí àlùfáà mú ọ̀kan nínú àwọn àgbò àti lógù òróró kí ó sì fi rú ẹbọ ẹ̀bi. Kí ó sì fì wọ́n níwájú Olúwa gẹ́gẹ́ bí ẹbọ fífì.
12 e o sacerdote tomará um dos cordeiros, e o oferecerá por oferta pela transgressão, e o logue de óleo, e os moverá por oferta movida perante o SENHOR;
13 Kí ó pa àgbò náà ní ibi mímọ́ níbi tí wọ́n ti ń pa ẹran ẹbọ ẹ̀ṣẹ̀ àti ọrẹ ẹbọ sísun. Bí ẹbọ ẹ̀ṣẹ̀, ẹbọ ẹ̀bi náà jẹ́ ti àlùfáà: ó jẹ́ mímọ́ jùlọ.
13 e ele matará o cordeiro no lugar onde ele mata a oferta pelo pecado e a oferta queimada, no santo lugar; porque assim como a oferta pelo pecado é do sacerdote, também é a oferta pela transgressão; é coisa santíssima.
14 Kí àlùfáà mú nínú ẹ̀jẹ̀ ẹbọ ẹ̀bi náà kí ó fi sí etí ọ̀tún ẹni náà tí a ó wẹ̀mọ́, kí ó tún fi sí àtàǹpàkò ọwọ́ ọ̀tún rẹ̀ àti orí àtàǹpàkò ẹsẹ̀ ọ̀tún rẹ̀.
14 E o sacerdote tomará um pouco do sangue da oferta pela transgressão, e o sacerdote o colocará sobre a ponta da orelha direita daquele que tem de purificar-se, e sobre o dedo polegar da sua mão direita, e sobre o dedo grande do seu pé direito;
15 Àlùfáà yóò sì mú díẹ̀ nínú lógù òróró, yóò sì dà á sí àtẹ́lẹwọ́ òsì ara rẹ̀.
15 e o sacerdote tomará um pouco do logue de óleo, e o derramará na palma da sua própria mão esquerda;
16 Yóò sì ti ìka ìfábẹ̀lá ọ̀tún rẹ̀ bọ inú òróró àtẹ́lẹwọ́ rẹ̀, yóò sì wọ́n díẹ̀ nínú rẹ̀ níwájú Olúwa nígbà méje.
16 e o sacerdote molhará o seu dedo direito no óleo que está na sua mão esquerda, e espargirá do óleo com o seu dedo, sete vezes perante o SENHOR;
17 Àlùfáà yóò mú lára òróró tí ó kù ní àtẹ́lẹwọ́ rẹ̀ yóò fi sí etí ọ̀tún, àtàǹpàkò ọwọ́ ọ̀tún àti àtàǹpàkò ẹsẹ̀ ọ̀tún ẹni tí à ó wẹ̀mọ́, lórí ẹ̀jẹ̀ ẹbọ ẹ̀bi.
17 e o restante de óleo que está na sua mão o sacerdote colocará sobre a ponta da orelha direita daquele que tem de purificar-se, e sobre o dedo polegar da sua mão direita, e sobre o dedo grande do seu pé direito, em cima do sangue da oferta pela transgressão;
18 Àlùfáà yóò fi òróró tí ó kù ní àtẹ́lẹwọ́ rẹ̀ ra orí ẹni tí a ó wẹ̀mọ́, yóò sì ṣe ètùtù fún un níwájú Olúwa.
18 e o restante do óleo que está na mão do sacerdote, ele o derramará sobre a cabeça daquele que tem de purificar-se; e o sacerdote fará expiação por ele perante o SENHOR.
19 “Àlùfáà yóò sì rú ẹbọ ẹ̀ṣẹ̀, yóò ṣe ètùtù fún ẹni tí a ó wẹ̀ kúrò nínú àìmọ́ rẹ̀, lẹ́yìn náà àlùfáà yóò pa ẹran ọrẹ ẹbọ sísun.
19 E o sacerdote oferecerá a oferta pelo pecado, e fará expiação por aquele que tem de purificar-se da sua impureza; e depois ele matará a oferta queimada;
20 Kí àlùfáà kí ó sì rú ẹbọ sísun, àti ẹbọ ohun jíjẹ lórí pẹpẹ, kí àlùfáà kí ó sì ṣe ètùtù fún un, òun yóò sì di mímọ́.
20 e o sacerdote oferecerá a oferta queimada e a oferta de alimentos sobre o altar; e o sacerdote fará expiação por ele, e este será limpo.
21 “Bí ẹni náà bá jẹ́ tálákà tí kò sì le è kó gbogbo nǹkan wọ̀nyí wá, kí ó mú ọ̀dọ́ àgbò kan bí ẹbọ ẹ̀bi, tí yóò fì, láti ṣe ètùtù fún un, pẹ̀lú ìdámẹ́wàá òsùwọ̀n ìyẹ̀fun dídára, a pò mọ́ òróró fún ọrẹ ohun jíjẹ òsùwọ̀n lógù òróró
21 E se ele for pobre, e não conseguir tanto, então ele tomará um cordeiro para expiação da culpa em oferta movida, para fazer expiação por ele, e a dízima de farinha fina, misturada com óleo, para oferta de alimentos, e um logue de óleo,
22 àti àdàbà méjì tàbí ẹyẹlé méjì èyí tí agbára rẹ̀ ká, ọ̀kan fún ẹbọ ẹ̀ṣẹ̀ àti èkejì fún ẹbọ sísun.
22 e duas rolas ou dois pombinhos, conforme for capaz de alcançar, dos quais um será uma oferta pelo pecado, e o outro uma oferta queimada.
23 “Kí ó mú wọn wá ní ọjọ́ kẹjọ fún ìwẹ̀nùmọ́ rẹ̀ síwájú àlùfáà ní ẹnu-ọ̀nà àgọ́ ìpàdé níwájú Olúwa.
23 E ele os trará ao oitavo dia da sua purificação ao sacerdote, à porta do tabernáculo da congregação, perante o SENHOR.
24 Àlùfáà náà yóò sì mú ọ̀dọ́-àgùntàn ẹbọ ẹ̀bi pẹ̀lú lógù òróró yóò sì fì wọ́n níwájú Olúwa bí ẹbọ fífì.
24 E o sacerdote tomará o cordeiro da oferta pela transgressão, e o logue de óleo, e o sacerdote os moverá por oferta movida perante o SENHOR;
25 Kí ó pa ọ̀dọ́-àgùntàn ẹbọ ẹ̀bi kí ó sì mú lára ẹ̀jẹ̀ rẹ̀. Kí ó fi sí etí ọ̀tún, àtàǹpàkò ọwọ́ ọ̀tún àti àtàǹpàkò ẹsẹ̀ ọ̀tún ẹni tí a ó ṣe ìwẹ̀nùmọ́ fún.
25 e ele matará o cordeiro da oferta pela transgressão, e o sacerdote tomará um pouco do sangue da oferta pela transgressão, e o colocará sobre a ponta da orelha direita daquele que se há de purificar, e sobre o dedo polegar da sua mão direita, e sobre o dedo grande do seu pé direito;
26 Àlùfáà yóò sì da díẹ̀ lára òróró náà sí àtẹ́lẹwọ́ òsì ara rẹ̀.
26 e o sacerdote derramará do óleo na palma da sua própria mão esquerda;
27 Yóò sì fi ìka ìfábẹ̀lá ọ̀tún rẹ̀ wọ́n òróró tí ó wà ní àtẹ́lẹwọ́ òsì rẹ̀ nígbà méje níwájú Olúwa.
27 e o sacerdote espargirá com o seu dedo direito um pouco do óleo que está na sua mão esquerda, sete vezes perante o SENHOR;
28 Àlùfáà yóò sì mú lára òróró ọwọ́ rẹ̀ sí etí ọ̀tún, àtàǹpàkò ọwọ́ ọ̀tún àti àtàǹpàkò ẹsẹ̀ ọ̀tún ẹni tí a ń ṣe ìwẹ̀nùmọ́ fún ní ibi kan náà tí wọ́n ta ẹ̀jẹ̀ ẹbọ ẹ̀bi sí.
28 e o sacerdote colocará do óleo que está na sua mão na ponta da orelha direita daquele que se há de purificar, e no dedo polegar da sua mão direita, e no dedo grande do seu pé direito, no lugar do sangue da oferta pela transgressão;
29 Kí àlùfáà fi ìyókù nínú òróró ọwọ́ rẹ̀ sí orí ẹni náà tí a ń ṣe ìwẹ̀nùmọ́ fún, láti ṣe ètùtù fún un ní iwájú Olúwa.
29 e o restante do óleo que está na mão do sacerdote ele colocará sobre a cabeça do que se há de purificar, para fazer expiação por ele perante o SENHOR.
30 Lẹ́yìn náà kí ó fi àdàbà tàbí ọmọ ẹyẹlé rú ẹbọ níwọ̀n tí agbára rẹ̀ mọ.
30 E ele oferecerá uma das rolas ou um dos pombinhos, conforme suas condições.
31 Ọ̀kan fún ẹbọ ẹ̀ṣẹ̀ àti èkejì fún ẹbọ sísun pẹ̀lú ẹbọ ohun jíjẹ, àlùfáà yóò sì ṣe ètùtù níwájú Olúwa ní ipò ẹni tí a fẹ́ wẹ̀mọ́.”
31 Do que for capaz de alcançar, será um para oferta pelo pecado, e o outro para oferta queimada com a oferta de alimentos; e o sacerdote fará expiação por aquele que se há de purificar perante o SENHOR.
32 Òfin nìyí fún ẹnikẹ́ni tí ó bá ní ààrùn ara tí ó le ran tí kò sì lágbára láti rú ẹbọ tí ó yẹ fún ìwẹ̀nùmọ́ bí a ti fi lélẹ̀.
32 Esta é a lei daquele em quem estiver a praga da lepra, cuja mão não é capaz de alcançar o que pertence à sua purificação.
33 Olúwa sọ fún Mose àti Aaroni pé.
33 E o SENHOR falou a Moisés e Arão, dizendo:
34 “Nígbà tí ẹ bá dé ilẹ̀ Kenaani tí mo fi fún yín ní ìní, tí mo sì fi ààrùn ẹ̀tẹ̀ sínú ilé kan ní ilẹ̀ ìní yín.
34 Quando tiverdes entrado na terra de Canaã, que eu vos dou por possessão, e eu colocar a praga da lepra em uma casa da terra da vossa possessão,
35 Kí ẹni tí ó ní ilé náà lọ sọ fún àlùfáà pé, ‘Èmi tí rí ohun tí ó jọ ààrùn ẹ̀tẹ̀ ní ilé mi.’
35 e quem possuir a casa fará saber ao sacerdote, dizendo: Parece-me que há algo como praga em minha casa;
36 Àlùfáà yóò pàṣẹ kí ẹnikẹ́ni tàbí ohunkóhun má ṣe wà nínú ilé náà, kí ó tó lọ yẹ ẹ̀tẹ̀ náà wò, kí ohunkóhun nínú ilé náà má bá à di àìmọ́. Lẹ́yìn èyí àlùfáà yóò wọlé lọ láti yẹ ilé náà wò.
36 então o sacerdote ordenará que esvaziem a casa, antes que o sacerdote entre para examinar a praga, para que tudo o que está na casa não seja feito impuro; e depois entrará o sacerdote para examinar a casa;
37 Yóò yẹ ààrùn náà wò, bí ààrùn náà bá ti wà lára ògiri ilé náà nípa àmì àwọ̀ ewé tàbí àmì pupa tí ó sì jinlẹ̀, ju ara ògiri lọ.
37 e ele examinará a praga, e eis que se a praga que estiver nas paredes da casa tiver cavidades verdes ou avermelhadas, e parecer mais fundas do que a parede,
38 Àlùfáà yóò jáde kúrò nínú ilé náà, yóò sì ti ìlẹ̀kùn ilé náà pa fún ọjọ́ méje.
38 então o sacerdote sairá daquela casa pela porta da casa, e fechará a casa por sete dias;
39 Àlùfáà yóò padà wá yẹ ilé náà wò ní ọjọ́ keje. Bí ààrùn náà bá ti tàn ká ara ògiri.
39 e o sacerdote virá novamente no sétimo dia e examinará; e eis que se a praga estiver espalhada nas paredes da casa;
40 Àlùfáà yóò pàṣẹ kí a yọ àwọn òkúta tí ààrùn náà ti bàjẹ́ kúrò kí a sì kó wọn dànù sí ibi tí a kà sí àìmọ́ lẹ́yìn ìlú.
40 então, o sacerdote ordenará que eles arranquem as pedras em que estiver a praga, e que as lancem em um lugar impuro fora da cidade;
41 Yóò sì mú kí wọ́n ha ògiri inú ilé náà yíká. Gbogbo ohun tí wọ́n fi rẹ́ ilé náà tí ó ti ha ni kí wọ́n kó dànù sí ibi tí a kà sí àìmọ́ lẹ́yìn ìlú náà.
41 e ele fará com que a casa seja raspada por dentro e ao redor, e eles derramarão o pó que houverem raspado fora da cidade em um lugar impuro.
42 Òkúta mìíràn ni kí wọ́n fi dípò àwọn tí a ti yọ dànù, kí wọ́n sì rẹ́ ilé náà pẹ̀lú àwọn ohun ìrẹ́lé tuntun.
42 E eles tomarão outras pedras e as porão no lugar daquelas pedras; e ele tomará outra argamassa, e rebocará a casa.
43 “Bí ààrùn yìí bá tún farahàn lẹ́yìn tí a ti yọ àwọn òkúta wọ̀nyí tí a sì ti ha ilé náà ti a sì tún rẹ́ ẹ.
43 E se a praga retornar, e brotar na casa, depois dele ter arrancado as pedras, e depois da casa ter sido raspada, e depois de ser rebocada,
44 Àlùfáà yóò tún lọ yẹ̀ ẹ́ wò bí ààrùn náà bá tún gbilẹ̀ sí i nínú ilé náà: ẹ̀tẹ̀ apanirun ni èyí, ilé náà jẹ́ aláìmọ́.
44 então, o sacerdote entrará, e a examinará; eis que, se a praga estiver se estendido na casa, e houver lepra roedora na casa; isto é impuro.
45 Wíwó ni kí a wó o, gbogbo òkúta ilé náà, àwọn igi àti gbogbo ohun tí a fi rẹ́ ẹ ni kí a kó jáde nínú ìlú sí ibi tí a kà sí àìmọ́.
45 E ele derrubará a casa, as suas pedras e a sua madeira, e também todo o barro da casa; e ele levará para fora da cidade, a um lugar impuro.
46 “Ẹni tí ó bá wọ inú ilé náà lẹ́yìn tí a ti tì í, yóò di aláìmọ́ títí ìrọ̀lẹ́.
46 E o que entrar naquela casa, em qualquer dia em que estiver fechada, será impuro até a tarde.
47 Ẹni tí ó bá sùn nínú ilé náà tàbí tí ó bá jẹun nínú rẹ̀ gbọdọ̀ fọ aṣọ rẹ̀.
47 E aquele que se deitar na casa lavará as suas vestes; e o que comer na casa lavará as suas vestes.
48 “Bí àlùfáà bá wá yẹ̀ ẹ́ wò tí ààrùn náà kò gbilẹ̀ mọ́ lẹ́yìn tí a ti rẹ́ ilé náà: kí àlùfáà pe ilé náà ní mímọ́, torí pé ààrùn náà ti lọ.
48 E se o sacerdote entrar, e examinar; e eis que, se a praga não houver se espalhado na casa, após a casa ter sido rebocada, então o sacerdote declarará a casa limpa, porque a praga está curada.
49 Láti sọ ilé yìí di mímọ́. Àlùfáà yóò mú ẹyẹ méjì àti igi kedari òdòdó àti hísópù.
49 E ele tomará para expiar a casa duas aves, e madeira de cedro, e escarlate, e hissopo;
50 Yóò sì pa ọ̀kan nínú àwọn ẹyẹ náà sórí omi tí ó mọ́ nínú ìkòkò amọ̀.
50 e ele matará uma das aves num vaso de barro sobre águas correntes;
51 Kí ó ri igi kedari, hísópù, òdòdó àti ààyè ẹyẹ náà bọ inú ẹ̀jẹ̀ òkú ẹyẹ àti omi tí ó mọ́ náà kí ó fi wọ́n ilẹ̀ náà lẹ́ẹ̀méje.
51 e ele tomará a madeira de cedro, e o hissopo, e a escarlate, e a ave viva, e os molhará no sangue da ave morta, e nas águas correntes, e espargirá a casa sete vezes;
52 Yóò fi ẹ̀jẹ̀ ẹyẹ náà, omi tí ó mọ́, ààyè ẹyẹ, igi kedari, hísópù àti òdòdó sọ ilé náà di mímọ́.
52 e ele purificará a casa com o sangue da ave, e com a água corrente, e com a ave viva, e com a madeira de cedro, e com o hissopo, e com a escarlate;
53 Kí àlùfáà ju ààyè ẹyẹ náà sílẹ̀ lẹ́yìn ìlú. Báyìí ni yóò ṣe ètùtù fún ilé náà. Ilé náà yóò sì mọ́.”
53 mas ele deixará ir a ave viva para fora da cidade sobre campo aberto; e fará expiação pela casa, e será limpa.
54 Àwọn wọ̀nyí ni ìlànà fún èyíkéyìí ààrùn àwọ̀ ara tí ó le è ràn ká, fún làpálàpá,
54 Esta é a lei de todo tipo de praga da lepra e da tinha;
55 àti fún ẹ̀tẹ̀ nínú aṣọ, àti ti ilé,
55 e da lepra das vestes, e das casas,
56 fún ara wíwú, fún èélá àti ibi ara tí ó ń dán yàtọ̀.
56 e da inchação, e da sarna, e da mancha clara;
57 Láti mú kí a mọ̀ bóyá nǹkan mọ́ tàbí kò mọ́.
57 para ensinar quando algo é impuro, e quando algo está limpo; esta é a lei da lepra.

Ler em outra tradução

Comparar com outra

Estude este capítulo no WhatsApp

Peça à IA da Bíblia Fala para explicar Levítico 14, comparar traduções ou montar um estudo — tudo direto pelo WhatsApp.