Lucas 9

Biblica® ní oore ọ̀fẹ́ láti lo Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde-Òní (YOR) vs AAI

Sair da comparação
AAI TUR GEWASIN O BAIBASIT BOUBUN
1 Ó sì pe àwọn ọmọ-ẹ̀yìn rẹ̀ méjìlá jọ, ó sì fún wọn ní agbára àti àṣẹ lórí àwọn ẹ̀mí èṣù gbogbo, àti láti wo ààrùn sàn.
1 Jesu ana bai’ufununayah etei I2 eaf ayuwih hina hitit, demon kakafih nunih isan, naatu sawow yumatah ta ta bosaisiren isan fair itih, naatu eonowahih.
2 Ó sì rán wọn lọ wàásù ìjọba Ọlọ́run, àti láti mú àwọn ọlọkùnrùn láradá.
2 Imaibo God ana aiwob binan isan naatu sawusawuwih baiyawasih isan iyafarih hitit hin.
3 Ó sì wí fún wọn pé, “Ẹ má ṣe mú nǹkan lọ́wọ́ fún àjò yín, ọ̀pá, tàbí àpò tàbí àkàrà, tàbí owó, bẹ́ẹ̀ ni kí ẹ̀yin má sì ṣe ní ẹ̀wù méjì.
3 Naatu iuwih, “A nanawan isan kwanatitit ana maramaim men sawar afa kwanabow auman kwananamih, men hafoy, tu, kabay, bay, o wanabir.
4 Ní ilékílé tí ẹ̀yin bá sì wọ̀, níbẹ̀ ni kí ẹ̀yin gbé, láti ibẹ̀ ni kí ẹ̀yin sì ti jáde.
4 Kwananan sabuw iyab hina’iti a merar hinay hinabubuwi na’at, nati bar meraramaim kwanama a bowabow kwanisawar imaibo kwanatit.
5 Iye àwọn tí kò bá si gbà yín, nígbà tí ẹ̀yin bá jáde kúrò ní ìlú náà, ẹ gbọn eruku ẹsẹ̀ yín fún ẹ̀rí sí wọn.”
5 Baise sabuw men a merar hinay hinabubuwi na’at, a fofob kwanarutatab nare naatu nati bar merar kwanihamiy kwanatit, baimatnuwen ana orereb na’atube.”
6 Wọ́n sì lọ, wọ́n ń la ìletò kọjá wọ́n sì ń wàásù ìyìnrere, wọ́n sì ń mú ènìyàn láradá níbi gbogbo.
6 Imaibo bai’ufununayah hitit hin bar awan, awan hirun hitit God ana aiwob isan tur gewasin hibinan naatu sawusawuwih hiyayawasih.
7 Herodu tetrarki gbọ́ nǹkan gbogbo èyí tí a ṣe láti ọ̀dọ̀ rẹ̀ wá: ó sì dààmú, nítorí tí àwọn ẹlòmíràn ń wí pé, Johanu ni ó jíǹde kúrò nínú òkú,
7 Herod, Galilee sabuw hai aiwob orot, sawar iti himamatar hai tur nonowar ana veya ana kasiy ra’at, anayabin sabuw afa hio John Baptist morobone matabir maiye,
8 Àwọn ẹlòmíràn sì wí pé Elijah ni ó farahàn; àwọn ẹlòmíràn sì wí pé, ọ̀kan nínú àwọn wòlíì àtijọ́ ni ó jíǹde.
8 sabuw afa hio, Elijah marane ra’iy, sabuw afa hio, “Dinab orot ta marasika momorob i yawas maiye matabir na.”
9 Herodu sì wí pé, “Johanu ni mo ti bẹ́ lórí, ṣùgbọ́n ta ni èyí tí èmi ń gbọ́ irú nǹkan wọ̀nyí sí?” Ó sì ń fẹ́ láti rí i.
9 Baise Herod eo, “Ayu taiyuwu aso’ob John i ayu sikan ao hi’afuw, naatu iti orot i yait iti bowabow sinaf ana tur anonowar?” Iti na’atube eo naatu kok i orot ana yumat itinamih nuwih.
10 Nígbà tí àwọn aposteli sì padà dé, wọ́n ròyìn ohun gbogbo fún un tí wọ́n ti ṣe. Ó sì mú wọn, lọ sí apá kan níbi tí a ń pè ní Betisaida.
10 Jesu ana tur abarayah himatabir hina hitit, sawar abisa’awat hisisinaf ana tur hi’owen. Naatu nawiyih hitit akisihimo hin tafaram wabin Bethsaida imaim hima.
11 Nígbà tí ọ̀pọ̀ ènìyàn sì mọ̀, wọ́n tẹ̀lé e: ó sì gbà wọ́n, ó sì sọ̀rọ̀ ìjọba Ọlọ́run fún wọn; àwọn tí ó fẹ́ ìmúláradá, ni ó sì mú láradá.
11 Baise sabuw maumurih na’in Jesu au Bethsaida inan ana tur hinowar, naatu hi’ufunun hin biyan hitit. Hai merar yi God ana aiwob isan binan hinowar naatu sawusawuwih iyawasih.
12 Nígbà tí ọjọ́ bẹ̀rẹ̀ sí rọlẹ̀, àwọn méjìlá wá, wọ́n sì wí fún un pé, “Tú ìjọ ènìyàn ká, kí wọn lè lọ sí ìletò àti sí ìlú yíká, kí wọn lè wò, àti kí wọn lè wá oúnjẹ: nítorí ijù ni àwa sá wà níhìn-ín.”
12 Veya re birabirab auman bai’ufununayah 12 hin Jesu hiu, “Sabuw kwiyafarih ten bar iti yubinamaim naatu masawabar iti yubinamaim taituwah tema’am biyah bay hinanuwet hinabow hinaa, naatu efan auman hinanuwet fai hina’in, anayabin iti efan i owararin.”
13 Ṣùgbọ́n ó wí fún wọn pé, “Ẹ fi oúnjẹ fún wọn jẹ!”
13 Baise Jesu iuwih, “Bay i boro kwa kwanitih hinaa.” Bai’ufununayah hiya’afut, “Rafiy fafar umat roun naatu siy rou’abamo efanamaim ti’inu’in. Kukokok aki anan sabuw etei’imak isah bay anatobon?”
14 Nítorí àwọn ọkùnrin náà tó ìwọ̀n ẹgbẹ̀rún márùn-ún (5,000) ènìyàn.
14 Sabuw nati’imaim hiru’ay hima tur hinonowar nah etei i 5,000 na’atube. Jesu ana bai’ufununayah iuwih, “Sabuw kwa’uwih nah 50 na’atube kou’ay tata’amaim timarir.”
15 Wọ́n sì ṣe bẹ́ẹ̀, wọ́n sì mú gbogbo wọn jókòó.
15 Bai’ufununayah Jesu eo na’atube sabuw hi’uwih himarir.
16 Nígbà náà ni ó mú ìṣù àkàrà márùn-ún, àti ẹja méjì náà, nígbà tí ó gbé ojú sókè ọ̀run, ó súre sí i, ó sì bù ú, ó sì fi fún àwọn ọmọ-ẹ̀yìn rẹ̀, kí wọn gbé e kalẹ̀ níwájú àwọn ènìyàn.
16 Imaibo Jesu rafiy fafar umat roun bow, naatu siy rou’ab bow, au mar nuw ra’at, God ana merar yi igegewasin sawar, im seseb ana bai’ufununayah itih hibow sabuw hifaramih hi’aa.
17 Wọ́n sì jẹ, gbogbo wọn sì yó: wọ́n ṣa agbọ̀n méjìlá jọ nínú àjẹkù tí ó kù.
17 Sabuw etei hi’aa yah iw naatu bai’ufununayah kaifet etei 12 hibow sabuw bay hi’aau turih hibihamiyen hiwan awah hikufoten.
18 Ó sì ṣe, nígbà tí ó ku òun nìkan ó gbàdúrà, àwọn ọmọ-ẹ̀yìn rẹ̀ sì wà lọ́dọ̀ rẹ̀: ó sì bi wọ́n pé, “Ta ni àwọn ènìyàn ń fi mí pè?”
18 Ana veya ta Jesu akisinamo ma yoyoyoban ana bai’ufununayah hina biyan hitit ibatiyih eo, “Sabuw ayu isau mi’itube’ewat teo kwanonowar?”
19 Wọ́n sì dáhùn wí pé, “Johanu Onítẹ̀bọmi; ṣùgbọ́n ẹlòmíràn ní Elijah ni, àti àwọn ẹlòmíràn wí pé, ọ̀kan nínú àwọn wòlíì àtijọ́ ni ó jíǹde.”
19 Hiya’afut hio, “Sabuw afa teo o i John Baptist, afa teo o i Elijah, naatu afa teo o i God ana dinab oro’orot marasika himomorob i ta morobone yawas maiye na.”
20 Ó sì bi wọ́n pé, “Ṣùgbọ́n ta ni ẹ̀yin ń fi èmi pè?”
20 Naatu ana bai’ufununayah ibatiyih, “Bo kwa ayu isou mi’itube kwanotanot?” Peter iya’afut eo, “O i God ana Roubininenayan.”
21 Ó sì kìlọ̀ fún wọn, pé, kí wọn má ṣe sọ èyí fún ẹnìkan.
21 Imaibo Jesu eofafarih eo, “Men yait ta ana tur kwana’owenamih.”
22 Ó sì wí pé, “Ọmọ ènìyàn yóò jìyà ohun púpọ̀, a ó sì kọ̀ ọ́ láti ọ̀dọ̀ àwọn alàgbà, olórí àlùfáà àti láti ọ̀dọ̀ àwọn akọ̀wé, a ó sì pa á, ní ọjọ́ kẹta a ó sì jí i dìde.”
22 Naatu Jesu iuwih eo, “Jew hai orot gagamih, firis hai ukwarih na’atube Ofafar Bai’obaiyenayah boro Orot Natun hinakwahir, biyababan gagamin na’in nab, hina’asabun namorob, baise veya baitounin ufunamaim boro morobone namisir maiye.”
23 Ó sì wí fún gbogbo wọn pé, “Bí ẹnìkan bá ń fẹ́ láti máa tọ̀ mí lẹ́yìn, kí ó sẹ́ ara rẹ̀, kí ó sì gbé àgbélébùú rẹ̀ ní ọjọ́ gbogbo, kí ó sì máa tọ̀ mí lẹ́yìn.
23 Naatu etei’imak iuwih eo, “Orot yait ayu bai’ufnunu’umih nakokok na’at, taiyuwin ana yawas i nakwahir, mar etei ana onaf na’abar ayu ni’uf nunu.
24 Nítorí ẹnikẹ́ni tí ó bá fẹ́ gba ọkàn rẹ̀ là, yóò sọ ọ́ nù: ṣùgbọ́n ẹnikẹ́ni tí ó bá sọ ọkàn rẹ̀ nù nítorí mi, òun náà ni yóò sì gbà á là.
24 Anayabin orot yait ana yawas i taiyuwin isan eo’oharihar boro nikasiy, baise orot yait ana yawas nakwahir ayu nabi’ufnunu, ma’ama wanatowan boro natita’ur.
25 Nítorí pé èrè kín ni fún ènìyàn, bí ó jèrè gbogbo ayé, tí ó sì sọ ara rẹ̀ nù tàbí kí ó fi ṣòfò.
25 Tafaram wanawanan orot ta sawar tutufin etei i bow karam, baise i taiyuwin ana yawas nabi’afiy, o hina bigegesair na’at, iti sawar bow ya ma tototo boro hinibais?
26 Nítorí ẹnikẹ́ni tí ó bá tijú mi, àti ọ̀rọ̀ mi, òun ni Ọmọ Ènìyàn yóò tijú rẹ̀ nígbà tí ó bá dé inú ògo tirẹ̀, àti ti baba rẹ̀, àti ti àwọn angẹli mímọ́.
26 Orot yait ayu isou biyan eo’ohow, naatu au tur isan biyan nao’ohow na’at, Orot Natun ana bonamanamarinamaim na’atube Tamah God ana bonamanamarinamaim naatu ana tounamatar kakafiyih auman hai bonamanamarinamaim namatabir maiye nanan ana veya, boro ibo isan biyan na’ohow.
27 “Ṣùgbọ́n èmi wí fún yín nítòótọ́, ẹlòmíràn dúró níhìn-ín yìí, tí kì yóò rí ikú, títí wọn ó fi rí ìjọba Ọlọ́run.”
27 Anababatun a tur ao’owen, kwa iyab iti kwama’am boro yawas kwanama’am God ana aiwob kwana’itin.”
28 Ó sì ṣe bí ìwọ̀n ọjọ́ mẹ́jọ lẹ́yìn ọ̀rọ̀ wọ̀nyí, ó mú Peteru àti Johanu àti Jakọbu, ó gun orí òkè lọ láti lọ gbàdúrà.
28 Tur iti eo hima fur ta’imon sasawar ufunamaim, Peter, John, naatu James buwih bairi hiyen hin oyaw wan yoyoban isan.
29 Bí ó sì ti ń gbàdúrà, àwọ̀ ojú rẹ̀ yípadà, aṣọ rẹ̀ sì funfun gbòò,
29 Naatu hiyen hin yoyoyoban ana maramaim yumatan botabir, ana faifuw hikwes anababatun namanamar ebowabow emamarakaw na’atube.
30 Sì kíyèsi i, àwọn ọkùnrin méjì, Mose àti Elijah, wọ́n ń bá a sọ̀rọ̀,
30 Nati ana maramaim naniyan meyemeye orot rou’ab, Moses, Elijah hairi hirerereb,
31 tí wọ́n fi ara hàn nínú ògo, wọ́n sì ń sọ̀rọ̀ ikú rẹ̀, tí òun yóò ṣe parí ní Jerusalẹmu.
31 mar ana marakaw bonamanamarin auman hira’iy Jesu ana bowabow iti tafaramamaim baisawarin matabir maiye isan, naatu God ana kok abisa Jesu Jerusalemamaim sinaf baiturobe isan bairi hio.
32 Ṣùgbọ́n ojú Peteru àti ti àwọn tí ń bẹ lọ́dọ̀ rẹ̀ wúwo fún oorun. Nígbà tí wọ́n sì tají, wọ́n rí ògo rẹ̀, àti ti àwọn ọkùnrin méjèèjì tí ó bá a dúró.
32 Peter ana ofonah bairi i nuhih bur hi’inu’in ufut iti sawar himatar, baise matah nuw himimisir auman Jesu biyanamaim bobonamanamar hi’itin naatu orot rou’ab bairi hibatabat hi’itih.
33 Ó sì ṣe, nígbà tí wọ́n lọ kúrò lọ́dọ̀ rẹ̀, Peteru wí fún Jesu pé, “Olùkọ́, ó dára fún wa kí a máa gbé ìhín yìí, jẹ́ kí àwa pa àgọ́ mẹ́ta, ọ̀kan fún ìwọ, àti ọ̀kan fún Mose, àti ọ̀kan fún Elijah.” (Kò mọ èyí tí òun ń wí.)
33 Naatu orot rou’ab Jesu hibihamiy auman, Peter Jesu isan eo, “Regah igewasin aki iti ama’amamaim sis tounu ana wowab, ta o isa ta Moses isan naatu Elijah isan!” Iti na’atube eo anayabin i men so’ob abisa eo.
34 Bí ó ti ń sọ báyìí, ìkùùkuu kan wá, ó síji bò wọ́n: ẹ̀rù sì bà wọ́n nígbà tí wọ́n ń wọ inú ìkùùkuu lọ.
34 Peter iti na’at bat eo auman sakusakuk ra’iy ana youninamaim tar sumih, naatu wanawanan hirur auman, bai’ufununayah yah birubir fafar.
35 Ohùn kan sì ti inú ìkùùkuu wá wí pé, “Èyí yìí ni àyànfẹ́ ọmọ mi: ẹ máa gbọ́ tirẹ̀.”
35 Sakukuw wanawanan God eafatait eo, Iti Orot i Ayu Natu, ayu arubin imih nao’o kwananowar.”
36 Nígbà tí ohùn náà sì dákẹ́, Jesu nìkan ṣoṣo ni a rí. Wọ́n sì pa á mọ́, wọn kò sì sọ ohunkóhun tí wọ́n rí fún ẹnikẹ́ni ní ọjọ́ wọ̀nyí.
36 Iti tur hinowar in sasawar ufunamaim Jesu akisinamo batabat hi’itin. Naatu bai’ufununayah sawar abisa nati ana veya’amaim hi’itin men yait ta ana tur hi’owen awah hibofot hima.
37 Ó sì ṣe, ní ọjọ́ kejì, nígbà tí wọ́n sọ̀kalẹ̀ wá láti orí òkè, ọ̀pọ̀ àwọn ènìyàn wá pàdé rẹ̀.
37 Marto Jesu ana bai’ufununayah bairi hire hina oyaw an hitit, naatu nati’imaim sabuw hima’am hina biyah hitit.
38 Sì kíyèsi i, ọkùnrin kan nínú ìjọ ènìyàn kígbe sókè pé, “Olùkọ́ mo bẹ̀ ọ́, wo ọmọ mi: nítorí ọmọ mi kan ṣoṣo náà ni.
38 Orot ta sabuw rau’ay wanawanahimaim batabat e’af eo, “Bai’obaiyenayan, abifefeyani kunuw natu ku’itin, natu ta’imon maiyow!
39 Sì kíyèsi i, ẹ̀mí èṣù a máa mú un, a sì máa kígbe lójijì; a sì máa nà án tàntàn títí yóò fi yọ ìfófó lẹ́nu, a máa pa á lára, kì í tilẹ̀ ń fẹ́ fi í sílẹ̀ lọ.
39 Demon kakafih kaun teyey ana veya eororsair iwow ere erab awan fusifusin ekubar in erabirab biyan riririr ebiwa’an. Naatu iti na’atube i mar etei esisinaf men kafa’imo ebihamiyimih.
40 Mo sì bẹ àwọn ọmọ-ẹ̀yìn rẹ láti lé e jáde: wọn kò sì lè ṣe é.”
40 A bai’ufununayah ai fefeyanih, demon nuninamih auwih, baise men karam.”
41 Jesu sì dáhùn pé, “Ìran aláìgbàgbọ́ àti àrékérekè, èmi ó ti bá yín gbé pẹ́ tó? Èmi yóò sì ti ṣe sùúrù fún yín pẹ́ tó? Fa ọmọ rẹ wá níhìn-ín yìí.”
41 Jesu iyafutih eo, “Kwa sabuw iti boun ana veya aur baitumatum naatu ayawas etei i hibibir. Kwanotanot ayu boro bairit manin tanama abit ana’abar? A kek kubai kuna aitin.”
42 Bí ó sì ti ń bọ̀, ẹ̀mí èṣù náà gbé e ṣánlẹ̀, ó sì nà án tàntàn. Jesu sì bá ẹ̀mí àìmọ́ náà wí, ó sì mú ọmọ náà láradá, ó sì fà á lé baba rẹ̀ lọ́wọ́.
42 Kek nan auman demon kakafin kek bai rab rouw me yan re naatu ifiruruw in hub itaiy re. Baise Jesu demon kakafin kwarar tatab nun tit kek iyawas bai tamah itin.
43 Ẹnu sì ya gbogbo wọn sí iṣẹ́ títóbi Ọlọ́run, ṣùgbọ́n nígbà tí hà sì ń ṣe gbogbo wọn sí ohun gbogbo tí Jesu ṣe, ó wí fún àwọn ọmọ-ẹ̀yìn rẹ̀ pé,
43 Sabuw etei’imak God ana fair hi’itin hifofofor men kafaita. Sabuw Jesu abisa sisinaf isan, hibat hibifofofor wanawanan Jesu ana bai’ufununayah isah eo,
44 “Ẹ jẹ́ kí ọ̀rọ̀ wọ̀nyí wọ̀ yín létí, nítorí a ó fi Ọmọ Ènìyàn lé àwọn ènìyàn lọ́wọ́.”
44 “Tain kwanarub gewas tur iti anao kwananowar. Orot Natun i boro baban hinao naatu hinab sabuw umahimaim hinayai.”
45 Ṣùgbọ́n ọ̀rọ̀ náà kò yé wọn, ó sì ṣú wọn lójú, bẹ́ẹ̀ ni wọn kò sì mọ̀ ọ́n: ẹ̀rù sì ń bà wọ́n láti béèrè ìdí ọ̀rọ̀ náà.
45 Baise bai’ufununayah iti tur naniyan men hibai, tur anayabin hai notamaim ibun, naatu baibatiyin tur anayabin o nowar isan hibir.
46 Iyàn kan sì dìde láàrín wọn, ní ti ẹni tí yóò ṣe olórí nínú wọn.
46 Bai’ufununayah taiyuwih wanawanahimaim, yait orot gagamin isan hio hinan gamin matar.
47 Nígbà tí Jesu sì mọ èrò ọkàn wọn, ó mú ọmọdé kan, ó gbé e jókòó lọ́dọ̀ rẹ̀.
47 Jesu abisa hinotanot itin, basit kek kafa’i ta bai na sisibinamaim iu bat.
48 Ó sì wí fún wọn pé, “Ẹnikẹ́ni tí ó bá gba ọmọdé yìí nítorí orúkọ mi, ó gbà mí: àti ẹnikẹ́ni tí ó bá gbà mí, ó gba ẹni tí ó rán mi: nítorí ẹni tí ó bá kéré jù nínú gbogbo yín, òun náà ni yóò pọ̀jù.”
48 Imaibo iuwih, “Orot yait kek kafai iti na’atube nab ayu wabu’umaim ana merar nayiy, i ayu au merar eyiy. Naatu orot yait ayu au merar eyiy i orot yait ayu iyunu anan i ana merar eyiy. Anayabin orot yait kwa wanawanamaim wabin en kek kikimin na’atube ema’am, nati orot i gagamin.”
49 Johanu sì dáhùn ó sì wí fún un pé, “Olùkọ́, àwa rí ẹnìkan ó ń fi orúkọ rẹ lé àwọn ẹ̀mí èṣù jáde; àwa sì dá a lẹ́kun, nítorí tí kò bá wa tọ̀ ọ́ lẹ́yìn.”
49 John misir eo, “Regah, orot ta o wabimaim demon kakafih nununih a’itin naatu a’otan. Anayabin nati orot i men it ata kou’ayomaim ema’ama.”
50 Jesu sì wí fún un, pé, “Má ṣe dá a lẹ́kun mọ́: nítorí ẹni tí kò bá lòdì sí i yín, ó wà fún yín.”
50 Jesu iya’afut eo, “Men ina’otanimih, anayabin orot yait kwa isa men ebirakit i kwa isa ebatabat.”
51 Nígbà tí ọjọ́ àti gbà á sókè ń súnmọ́, ó pinnu láti lọ sí Jerusalẹmu.
51 Jesu au mar yen isan ana veya na kakabom auman, ana not bogaigiwas yen in au Jerusalem.
52 Ó sì rán àwọn ìránṣẹ́ lọ sí iwájú rẹ̀. Nígbà tí wọ́n sì lọ wọ́n wọ ìletò kan tí í ṣe ti ará Samaria láti pèsè sílẹ̀ dè é.
52 Naatu kob wan iyafarih hin Samaria bar merar hitit ana efan hitayabuna tanan imaim ta’in isan.
53 Wọn kò sì gbà á, nítorí pé ó ń lọ sí Jerusalẹmu.
53 Baise Samaria sabuw men ana merar hiyi hibai efan hitinimih, anayabin hiso’ob Jesu i au Jerusalem yey.
54 Nígbà tí àwọn ọmọ-ẹ̀yìn rẹ̀ Jakọbu àti Johanu sì rí i, wọ́n ní, “Olúwa wa, jẹ́ kí a pe iná láti ọ̀run wá, kí a sì pa wọ́n run, bí Elijah ti ṣe?”
54 Naatu bai’ufununayah orot rou’ab James John hairi iti na’atube hi’i’itin yah so’ar hio, “Regah, kukokok wairaf marane anao nara’iy iti sabuw nagurusih?”
55 Ṣùgbọ́n Jesu yípadà, ó sì bá wọn wí.
55 Baise Jesu tatabir hairi’ika kwararih.
56 Lẹ́yìn náà Jesu àti àwọn ọmọ-ẹ̀yìn rẹ̀ sì lọ sí ìletò mìíràn.
56 Naatu Jesu ana bai’ufununayah bairi hin bar merar ta hitit.
57 Bí wọ́n ti ń lọ lọ́nà, ọkùnrin kan wí fún un pé, “Olúwa, Èmi ń fẹ́ láti máa tọ̀ ọ́ lẹ́yìn ní ibikíbi tí ìwọ bá ń lọ.”
57 Ef hiyen hinan naiwanamaim orot ta Jesu ana tur eowen eo, “Ayu boro ani’ufnuni o menamaim kwenan boro imaim tanan.”
58 Jesu sì wí fún un pé, “Àwọn kọ̀lọ̀kọ̀lọ̀ ní ihò, àwọn ẹyẹ ojú ọ̀run sì ní ìtẹ́; ṣùgbọ́n Ọmọ Ènìyàn kò ní ibi tí yóò fi orí rẹ̀ lé.”
58 Jesu orot iya’afut iu, “Haruharu hai sau tema’am, naatu mamu hai batar tema’am, baise Orot Natun mare ma biyan tubaiwa’an isan aurin efan i en.”
59 Ó sì wí fún ẹlòmíràn pé, “Máa tọ̀ mí lẹ́yìn.”
59 Naatu Jesu tatabir orot ta isan eo, “Kwi’ufnunu airit tan.” Baise orot eo, “Regah akokok wan i boro inihamiyu anan tamai morob inu’in anab anan ana yai imaibo ani’ufnuni?”
60 Jesu sì wí fún un pé, “Jẹ́ kí àwọn òkú máa sìnkú ara wọn, ṣùgbọ́n ìwọ lọ kí o sì máa wàásù ìjọba Ọlọ́run.”
60 Baise Jesu orot iya’afut eo, “Murubih kwaihamiyih boro murubih taiyuwih hinaya’ih. Baise o i kwen, God ana aiwob isan kubinan.”
61 Ẹlòmíràn sì wí fún un pé, “Olúwa, èmi yóò tọ̀ ọ́ lẹ́yìn ṣùgbọ́n jẹ́ kí n kọ́kọ́ lọ dágbére fún àwọn ará ilé mi.”
61 Naatu orot ta na maiye eo, “Regah ayu i boro o ani’ufnuni, baise wan i boro anan hinai tamai naatu taitu tuwai’inah anao tuturih.”
62 Jesu sì wí fún un pé, “Kò sí ẹni, tí ó fi ọwọ́ rẹ̀ lé ohun èlò ìtulẹ̀, tí ó sì wo ẹ̀yìn, tí ó yẹ fún ìjọba Ọlọ́run.”
62 Jesu iya’afut iu, “Orot yait busuruf ana me bifufubiy, naatu misir maiye bat au’uf enunutabitabir, God ana aiwobomaim boro men karam nabow.”

Ler em outra tradução

Comparar com outra

Estude este capítulo no WhatsApp

Peça à IA da Bíblia Fala para explicar Lucas 9, comparar traduções ou montar um estudo — tudo direto pelo WhatsApp.