Lucas 24
Biblica® ní oore ọ̀fẹ́ láti lo Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde-Òní (YOR) vs AAI
1 Ní kùtùkùtù òwúrọ̀ ọjọ́ ọ̀sẹ̀, àwọn obìnrin wá sí ibojì, wọ́n sì mú ìkunra olóòórùn dídùn ti wọ́n tí pèsè sílẹ̀ wá.
1 Sunday maraumanika baibin raiy hibogaigiwas hi’inu’in hibow hin rah yan hitit.
2 Òkúta ti yí kúrò ní ẹnu ibojì.
2 Naatu hin rah yan hitit ana veya kabay gagamin Jesu ana hub awan hiya’afut inu’in hifururuw tit hub awan asir inu’in hi’itin.
3 Nígbà tí wọ́n sì wọ inú rẹ̀, wọn kò rí òkú Jesu Olúwa.
3 Basit wanawanan hirun hin, baise Regah Jesu biyan men hitita’urimih.
4 Bí wọ́n ti dààmú kiri níhà ibẹ̀, kíyèsi i, àwọn ọkùnrin méjì aláṣọ dídán dúró tì wọ́n.
4 Nati’imaim hai kasiy ra’at hibat hibinubunibun naniyan meyemeye orot rou’ab hai bonamanamarin auman sisibihimaim himatar hibat.
5 Nígbà tí ẹ̀rù ń bà wọ́n, tí wọ́n sì dojúbolẹ̀, àwọn angẹli náà bi wọ́n pé, “Èéṣe tí ẹ̀yin fi ń wá alààyè láàrín àwọn òkú?
5 Baibin hai bir ra’at nahimaim yumatah au babe me yan hire, baise orot rou’ab hi’uwih hio, “Kwa aisim orot yawasin isan sabuw murubin hai efanamaim kwanunuwih?
6 Kò sí níhìn-ín yìí, ṣùgbọ́n ó jíǹde; ẹ rántí bí ó ti wí fún yín nígbà tí ó wà ní Galili.
6 Iti’imaim boro men kwana’itin, i morobone misir maiye! Galilee imaim bairi kwama’am ana veya tur abisa eo i kwanotanot.
7 Pé, ‘A ó fi Ọmọ Ènìyàn lé àwọn ènìyàn ẹlẹ́ṣẹ̀ lọ́wọ́, a ó sì kàn án mọ́ àgbélébùú, ní ọjọ́ kẹta yóò sì jíǹde.’ ”
7 ‘Orot Natun i boro hinab sabuw kakafih umahimaim hinayai, hina’onaf, naatu veya tounu ufunamaim morobone nayawas maiye.’”
8 Wọ́n sì rántí ọ̀rọ̀ rẹ̀.
8 Imaibo baibin ana tur eo nuhih taseb hinot.
9 Wọ́n sì padà ti ibojì wá, wọ́n sì ròyìn gbogbo nǹkan wọ̀nyí fún àwọn mọ́kànlá, àti fún gbogbo àwọn ìyókù.
9 Naatu rahane himatabir maiye hina bar hitit. Sawar abisa’awat hi’i’itah ana bai’ufununayah nah 11 naatu bai’ufununayah afa nati baremaim hima’am auman hai tur hi’owen.
10 Maria Magdalene, àti Joanna, àti Maria ìyá Jakọbu, àti àwọn mìíràn pẹ̀lú wọn sì ni àwọn tí ó ròyìn nǹkan wọ̀nyí fún àwọn aposteli.
10 Baibin iyabowat sawar hi’itah hina Jesu ana tur abarayah hai tur hio’owen wabih i Mary Magdalin, Joanna naatu Mary, James hinah naatu baibin afa auman.
11 Ọ̀rọ̀ wọ̀nyí sì dàbí ìsọkúsọ lójú wọn, wọn kò sì gbà wọ́n gbọ́.
11 Baise Jesu ana tur abarayah baibin hio men hitumatum, anayabin hai tur hinonowar naniyan i tamim tao kwanekwan na’atube.
12 Nígbà náà ni Peteru dìde, ó súré lọ sí ibojì; nígbà tí ó sì bẹ̀rẹ̀, ó rí aṣọ àlà lọ́tọ̀ fúnra wọn, ó sì padà lọ sí ilé rẹ̀, ẹnu yà á sí ohun tí ó ṣe.
12 Baise Peter misir nunuw in rah yan tit, hub wanawanan kwaf nuwariy faifuwawat hi’inu’in itah, basit abisa mamatar isan erebainotanot auman matabir in.
13 Sì kíyèsi i, àwọn méjì nínú wọn ń lọ ní ọjọ́ náà sí ìletò kan tí a ń pè ní Emmausi, tí ó jìnnà sí Jerusalẹmu níwọ̀n ọgọ́ta ibùsọ̀.
13 Nati veya ta’imon Jesu ana bai’ufununayah orot rou’ab Jerusalemane hin bar merar ta wabin Emmaus imaim hitit. Jerusalem in Emmaus titit ana fofonin i 11 kilometres na’atube.
14 Wọ́n ń bá ara wọn sọ̀rọ̀ gbogbo nǹkan wọ̀nyí tí ó ṣẹlẹ̀.
14 Baise iti orot rou’ab efamaim sawar abisa’awat himamatar isah hairi hio hidudur hinan ana veya,
15 Ó sì ṣe, bí wọ́n ti ń bá ara wọn sọ̀rọ̀, tí wọ́n sì ń bá ara wọn jíròrò, Jesu tìkára rẹ̀ súnmọ́ wọn, ó sì ń bá wọn rìn lọ.
15 Jesu ufuhine natit botanih bairi hita’imon hiremor hin.
16 Ṣùgbọ́n a rú wọn lójú, kí wọn má le mọ̀ ọ́n.
16 Naatu bairi hinan i hi’itin baise men kafa’imo hi’inan.
17 Ó sì bi wọ́n pé, “Ọ̀rọ̀ kín ni ẹ̀yin ń bá ara yín sọ, bí ẹ̀yin ti ń rìn?”
17 Jesu ibatiyih, “Kwa abisa isan tura airi kwaidudur auman kwanan?” Naatu orot rou’ab hinutanub yah rererey yen hibat.
18 Ọ̀kan nínú wọn, tí a ń pè ní Kileopa, sì dáhùn wí fún un pé, “Àlejò sá à ni ìwọ ní Jerusalẹmu, tí ìwọ kò sì mọ ohun tí ó ṣẹ̀ níbẹ̀ ní ọjọ́ wọ̀nyí?”
18 Orot ta wabin Cleopas ibatiy eo, “Jerusalem wanawanan o akisimo nanawan orot, imih sawar abisa fai fur wanawanan mamatar o men iso’obamih?”
19 Ó sì bi wọ́n pé, “Kín ni?”
19 Jesu ibatiyih, “Sawar abistan?”
20 àti bí àwọn olórí àlùfáà àti àwọn alàgbà wa ti fi òun lé wọn lọ́wọ́ láti dá a lẹ́bi ikú, àti bí wọ́n ti kàn án mọ́ àgbélébùú.
20 Baise aki ai firis ukwarih naatu bonawiyenayah orot ukwarih hibai Roman gawan hitin, morobomih eo ibasit naatu hibai hin hi’onaf morob.
21 Bẹ́ẹ̀ ni òun ni àwa ti ní ìrètí pé, òun ni ìbá dá Israẹli ní ìdè. Àti pẹ̀lú gbogbo nǹkan wọ̀nyí, òní ni ó di ọjọ́ kẹta tí nǹkan wọ̀nyí ti ṣẹlẹ̀.
21 Aki anotanot iti orot boro Israel sabuw baiyawasih arouw nuhifot ama’am, baise iti orot hirab momorob i veya boun tounu sawar.
22 Àwọn obìnrin kan pẹ̀lú nínú ẹgbẹ́ wa, tí wọ́n lọ si ibojì ní kùtùkùtù, sì wá yà wá lẹ́nu,
22 Naatu baibin afa aki ai kou’ayomaim boun maraumanika hin rah yan hititit biyan hiboyouw
23 nígbà tí wọn kò sì rí òkú rẹ̀, wọ́n wá wí pé, àwọn rí ìran àwọn angẹli tí wọ́n wí pé, ó wà láààyè.
23 naatu himatabir hina hio, ‘Aki tounamatar ai’itih, naatu tounamatar ai tur hi’owen Jesu i morobone misir maiye.’ Iti na’at hio aki aoror sa’iri ai kasiy ra’at.
24 Àti àwọn kan tí wọ́n wà pẹ̀lú wa lọ sí ibojì, wọ́n sì rí i gẹ́gẹ́ bí àwọn obìnrin náà ti wí, ṣùgbọ́n òun tìkára rẹ̀ ni wọn kò rí.”
24 Basit ai kou’ayomaim sabuw afa hin rah yan hit abisa baibin hio hinowar na’atube hi’itah, baise Jesu men hi’itinimih.”
25 Ó sì wí fún wọn pé, “Ẹ̀yin tí òye kò yé, tí ẹ sì yigbì ní àyà láti gba gbogbo èyí tí àwọn wòlíì ti wí gbọ́,
25 Imaibo Jesu iuwih eo, “Kwa i kwabikoko’aw, aisim dinab oro’orot abisa hio hikikirum men fudir rerekab kwabitumatumamih!
26 kò ha yẹ kí Kristi ó jìyà nǹkan wọ̀nyí kí ó sì wọ inú ògo rẹ̀ lọ.”
26 Keriso iti sawar etei isah ni’akir biyan nababan saise ana aiwob maramaim narun nabi’aiwob isan men kwaso’ob?”
27 Ó sì bẹ̀rẹ̀ láti Mose àti gbogbo àwọn wòlíì wá, ó sì túmọ̀ nǹkan fún wọn nínú ìwé mímọ́ gbogbo nípa ti ara rẹ̀.
27 Imaibo Jesu taiyuwin isan aneika Moses ana Buk kikirum imaim busuruf idudur rena God ana dinab oro’orot hai Buk hikikirum imaim tit.
28 Wọ́n sì súnmọ́ ìletò tí wọ́n ń lọ, ó sì ṣe bí ẹni pé yóò lọ sí iwájú.
28 Naatu bar merar hinuh hinanamaim hititit auman, Jesu bar merar ta namihibe iwa’an hi’itin.
29 Wọ́n sì rọ̀ ọ́, pé, “Bá wa dúró: nítorí ó di ọjọ́ alẹ́, ọjọ́ sì kọjá tán.” Ó sì wọlé lọ, ó bá wọn dúró.
29 Baise hi’otan hio, “Veya sawar naatu mar efof imih tarun bairit ta’in.” Iti na’at hio itin, basit bairi inumih hirun.
30 Ó sì ṣe, bí ó ti bá wọn jókòó ti oúnjẹ, ó mú àkàrà, ó súre sí i, ó sì bù ú, ó sì fi fún wọn.
30 Bay aa isan Jesu bairi himare, eof rafiy bai God ana merar yi sawar imasib itih.
31 Ojú wọn sì là, wọ́n sì mọ̀ ọ́n, ó sì nù mọ́ wọn ní ojú.
31 Imaibo hairi matah to iwa’an hi’inan, baise marta’imon na’am sa’iwa’an.
32 Wọ́n sì bá ara wọn sọ pé, “Ọkàn wa kò ha gbiná nínú wa, nígbà tí ó ń bá wa sọ̀rọ̀ tí ó sì ń túmọ̀ ìwé mímọ́ fún wa!”
32 Hairi himisir hio, “Efamaim tanan Buk Atamaninamaim bidudur dogorot ahayabe yiy naniyan itatam?”
33 Wọ́n sì dìde ní wákàtí kan náà, wọ́n padà lọ sí Jerusalẹmu, wọ́n sì bá àwọn mọ́kànlá péjọ, àti àwọn tí ń bẹ lọ́dọ̀ wọn.
33 Basit himisir himatabir maiye hin Jerusalem hitit, nati’imaim bai’ufununayah nah 11 naatu afa auman hiru’ay hima’am hi’itih,
34 Wọn si wí pé, “Olúwa jíǹde nítòótọ́, ó sì ti fi ara hàn fún Simoni!”
34 hai tur hi’owen hio, “Tur anababatun Regah i morobone misir maiye Simon isan irerereb.
35 Àwọn náà sì ròyìn nǹkan tí ó ṣe ní ọ̀nà, àti bí ó ti di mí mọ̀ fún wọn ní bíbu àkàrà.
35 Orot rou’ab efamaim abisa mamatar naatu mi’itube rafiy imasib bitih ana veya’amaim matah to iwa’an hi’i’inan etei hidudur turahinah hinowar.
36 Bí wọ́n sì ti ń sọ nǹkan wọ̀nyí Jesu tìkára rẹ̀ dúró láàrín wọn, ó sì wí fún wọn pé, “Àlàáfíà fún yín.”
36 Orot rou’ab iti na’atube hima hio hinonowar auman naniyan meyemeye Regah nah yan foun matar bat iuwih eo, “Tufuw isa nama.”
37 Ṣùgbọ́n àyà fò wọ́n, wọ́n sì wárìrì, wọ́n ṣe bí àwọn rí ẹ̀mí kan.
37 Etei hi’oror, hai bir ra’at, hinotanot i yoyom mowan itinin hirouw.
38 Ó sì wí fún wọn pé, “Èéṣe tí ara yín kò lélẹ̀? Èé sì ti ṣe tí èròkerò fi ń sọ nínú ọkàn yín?
38 Baise Jesu iuwih eo, “Aisim kwabirubir naatu aisim a not boro’ika tekakasiy?
39 Ẹ wo ọwọ́ mi àti ẹsẹ̀ mi, pé èmi tìkára mi ni! Ẹ dì mímú kí ẹ wò ó nítorí tí iwin kò ní ẹran àti egungun lára, bí ẹ̀yin ti rí tí èmi ní.”
39 Au umau kwa’itah, naatu biyau kwabutubun finimu au rakit naniyan kwatatam, saise kwanaso’ob iti i anababatun ayu, anayabin yoyom i aurih finimih en.”
40 Nígbà tí ó sì wí bẹ́ẹ̀ tan, ó fi ọwọ́ àti ẹsẹ̀ rẹ̀ hàn wọ́n.
40 Iti ra’at eo sawar basit an uman i’obaiyih hi’itan.
41 Nígbà tí wọn kò sì tí ì gbàgbọ́ fún ayọ̀, àti fún ìyanu, ó wí fún wọn pé, “Ẹ̀yin ní ohunkóhun jíjẹ níhìn-ín yìí?”
41 Baise men kafa’imo hitumatumamih, hai kawasa ra’at hikasiy auman, basit Jesu ibatiyih, “Kwa bay urey ta kwayai inu’in?”
42 Wọ́n sì fún un ní ẹja tí a fi oyin sè.
42 Siy baibitab finimin reban hibai hitin
43 Ó sì gbà á, ó jẹ ẹ́ lójú wọn.
43 naatu nahimaim bat eaan hi’itin.
44 Ó sì wí fún wọn pé, “Wọ̀nyí ni ọ̀rọ̀ tí mo sọ fún yín, nígbà tí èmí ti wà pẹ̀lú yín pé, a ní láti mú ohun gbogbo ṣẹ, tí a ti kọ nínú òfin Mose, àti nínú ìwé àwọn wòlíì, àti nínú Saamu, nípasẹ̀ mi.”
44 Imaibo hai tur eowen eo, “Ayu i sawar iti isah bairit tama’ama ana veya a tur aowen. Sawar abisa ayu isau mataramih Moses ana Bukamaim, dinab hai Bukamaim na’atube Psalms imaim hio hikikirum hina hiturobe.”
45 Nígbà náà ni ó ṣí wọn ní iyè, kí ìwé mímọ́ lè yé wọn.
45 Imaibo hai not botawiy Buk Atamaninamaim abisa isan hio hikikirum naniyan hibai.
46 Ó sì wí fún wọn pé, “Bẹ́ẹ̀ ni a ti kọ̀wé rẹ̀, pé: kí Kristi jìyà, àti kí ó sì jíǹde ní ọjọ́ kẹta kúrò nínú òkú,
46 Naatu iuwih eo, “Abisa hio hikikirum anayabin i iti, Keriso i ni’akir biyan nababan namorob, naatu veya tounu ufunamaim boro nayawas maiye namisir.
47 àti pé kí a wàásù ìrònúpìwàdà àti ìdáríjì ẹ̀ṣẹ̀ lórúkọ rẹ̀, ní orílẹ̀-èdè gbogbo, bẹ̀rẹ̀ láti Jerusalẹmu lọ.
47 Saise i wabinamaim ya baikitabir naatu notawiyen ana tur Jerusalemamaim an hinayai hinabinan hinatit hinan tafaram tutufin etei hinanowar.
48 Ẹ̀yin sì ni ẹlẹ́rìí nǹkan wọ̀nyí.
48 Imih kwa abisa matamaim kwa’i’itin i kwanakubuna sabuw etei hai tur kwana’owen hinanowar.
49 Èmi yóò rán ohun tí Baba mi ṣe ìlérí sí yín, ṣùgbọ́n ẹ jókòó ní ìlú Jerusalẹmu, títí a ó fífi agbára wọ̀ yín, láti òkè ọ̀run wá.”
49 Jerusalemamaim kwanama ayu Tamai abisa baitimih eo’omatani marane aniyafar nare a fair kwanab.”
50 Ó sì mú wọn jáde lọ títí wọ́n fẹ́rẹ̀ dé Betani, nígbà tí ó sì gbé ọwọ́ rẹ̀ sókè, ó súre fún wọn.
50 Imaibo nawiyih bairi Jerusalem hihamiy hitit hin Bethany hitit, nati’imaim uman bora’ah isah yoyoban igegewasinih.
51 Ó sì ṣe, bí ó ti ń súre fún wọn, ó yà kúrò lọ́dọ̀ wọn, a sì gbé e lọ sí ọ̀run.
51 Bigegewasinih auman ihamiyih earura’ah yen in mar wanawanan run.
52 Wọ́n sì foríbalẹ̀ fún un, wọ́n sì padà lọ sí Jerusalẹmu pẹ̀lú ayọ̀ púpọ̀.
52 Hibora’ara’ah yasisir yah awan karatan auman himatabir maiye hin Jerusalem hitit.
53 Wọ́n sì wà ní tẹmpili nígbà gbogbo, wọ́n ń fi ìyìn, àti ìbùkún fún Ọlọ́run.
53 Nati’imaim mar etei hin Tafaror Baremaim God ana merar hiyiy naatu hibobora’ara’ah.
Atalhos do teclado
- Capítulo anterior←
- Próximo capítulo→
- Versículo anteriork
- Próximo versículoj
- Limpar seleçãoEsc
- Esta ajuda?
Estude este capítulo no WhatsApp
Peça à IA da Bíblia Fala para explicar Lucas 24, comparar traduções ou montar um estudo — tudo direto pelo WhatsApp.