Lucas 16
Biblica® ní oore ọ̀fẹ́ láti lo Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde-Òní (YOR) vs AAI
1 Ó sì wí fún àwọn ọmọ-ẹ̀yìn rẹ̀ pẹ̀lú pé, “Ọkùnrin ọlọ́rọ̀ kan wà, tí ó ní ìríjú kan; òun náà ni wọ́n fi sùn ún pé, ó ti ń fi ohun ìní rẹ̀ ṣòfò.
1 Jesu ana bai’ufununayah iuwih eo, “Ana veya ta orot guguw wairafin ana bowayan orot ukwarin sawar kakaifen kakaf isan ana tur nowar.
2 Nígbà tí ó sì pè é, ó wí fún un pé, ‘Èéṣe tí èmi fi ń gbọ́ èyí sí ọ? Ṣírò iṣẹ́ ìríjú rẹ; nítorí ìwọ kò lè ṣe ìríjú mi mọ́.’
2 Basit orot ukwarin eaf na ibatiy, ‘O a bowabow isan tur anonowar i men gewasin. Ayu akokok a bowabow isan inao gewas ananowar? O a bowabowamaim i esasawar.’
3 “Ìríjú náà sì wí nínú ara rẹ̀ pé, ‘Èwo ni èmi ó ṣe? Nítorí tí olúwa mi gba iṣẹ́ ìríjú lọ́wọ́ mi: èmi kò le ṣiṣẹ́ oko, bẹ́ẹ̀ ni ojú ń tì mí láti ṣagbe.
3 Ana bowayan orot ukwarin ma binotanot eo, ‘Ayu au regah i au bowabowamaim ebobotaitu, ayu men fairu boro me anakwair anatar, naatu fefeyan isan boro biyau na’ohow.
4 Mo mọ èyí tí èmi yóò ṣe, nígbà tí a bá mú mi kúrò níbi iṣẹ́ ìríjú, kí àwọn ènìyàn le gbà mí sínú ilé wọn.’
4 Baise aso’ob boro sawar ta anasinaf, saise au bowabow nasawar anatitit au ofonah afa boro au merar hinay hinabuwu bairi anama.’
5 “Ó sì pe àwọn ajigbèsè olúwa rẹ̀ sọ́dọ̀ rẹ̀, ó sì wí fún èkínní pé, ‘Èló ni ìwọ jẹ olúwa mi?’
5 Basit akirwairafih iyabowat orot guguw wairafin ana sawar hibow imaim hima hibowabow eaf hina, orot ta wan run ibatiy, ‘O au regah ana sawar bai’ab kubobotan boro inibaiyan?’
6 “Ó sì wí pé, ‘Ẹ̀ẹ́dẹ́gbẹ̀rún (900) òsùwọ̀n òróró.’
6 Akirwairafin iya’afut eo, ‘Olive iroro’on ana momon etei 3,000 litres ana fofonin kibub wanawanan ebatabat.’ Orot ukwarin fef itin eo, ‘Kumare kibub wanawanan iroro’on 1,500 litres ana fofonin kukirum.’
7 “Nígbà náà ni ó sì bi ẹnìkejì pé, ‘Èló ni ìwọ jẹ?’
7 Orot bairou’abin ibatiy, ‘O au regah ana sawar bai’ab kubobotan boro inibaiyan?’ Akirwairafin iya’afut eo, ‘35,000 litres ana fofonin rafiy abobotan.’ Fef itin eo, ‘Kumare 17,500 kukirum.’
8 “Olúwa rẹ̀ sì yin aláìṣòótọ́ ìríjú náà, nítorí tí ó fi ọgbọ́n ṣe é, àwọn ọmọ ayé yìí sá à gbọ́n ní ìran wọn ju àwọn ọmọ ìmọ́lẹ̀ lọ.
8 Naatu orot guguw wairafin orot ana sawar kaifenayan kirum bisawar ufunamaim ana bowabow i’itin ana maramaim ana merar yi bora’ara’ah. Anayabin sabuw iyab iti tafaram nowan i hai not rerekabin nati na’atube hikirum hifufuwen o tur maiyow kurarouw, baise marakaw ana sabuw men nati na’atube tesisinaf.
9 Èmi sì wí fún yín, ẹ fi ọrọ̀ ayé yìí yan ọ̀rẹ́ fún ara yín pé, nígbà tí o ba lọ, kí wọn kí ó le gbà yín sí ibùjókòó wọn títí ayé.
9 Naatu a tur ao’owen, tafaram ana sawaramaim sabuw kwanibaisih bairi kwani’of, saise nati sawar o biyamaim nabi’en ana veya maramaim boro a merar hinay hinabuwi bairi kwanama.
10 “Ẹni tí ó bá ṣe olóòtítọ́ nínú ohun kínkínní, ó ṣe olóòtítọ́ ní púpọ̀ pẹ̀lú: ẹni tí ó bá sì ṣe aláìṣòótọ́ ní ohun kínkínní, ó ṣe aláìṣòótọ́ ní ohun púpọ̀ pẹ̀lú.
10 “Orot yait sawar gidigidih hitumitum hibitin ekakaifen gewas, sawar gagamih auman boro hinitin nakaifen gewas, naatu orot yait sawar gidigidih hibitin men ekakaifen gewas, sawar gagamih auman boro men nakaifen gewas.
11 Ǹjẹ́ bí ẹ̀yin kò bá ti jẹ́ olóòtítọ́ nínú ọrọ̀ ayé yìí, ta ni yóò fi ọ̀rọ̀ tòótọ́ fún yín?
11 Imih o iti tafaram ana sawar hitutumi hibit men kukakaifen gewas, mar ana sawar gewasih hinabit boro men inakaifen gewasomih.
12 Bí ẹ̀yin kò bá sì ti jẹ́ olóòtítọ́ nínú ohun tí í ṣe ti ẹlòmíràn, ta ni yóò fún yín ní ohun tí í ṣe ti ẹ̀yin tìkára yín?
12 Sabuw afa hai sawar o hitutumi hibit men kukakaifen gewas, o a sawar hinabit boro mi’itube inakaif gewas?
13 “Kò sì í ẹnìkan tí ó lè sin ọ̀gá méjì. Òun yóò yà kórìíra ọ̀kan tí yóò fẹ́ràn èkejì, tàbí kí ó fi ara mọ́ ọ̀kan kí ó sì yan èkejì ní ìpọ̀sí. Ẹ̀yin kò lè sin Ọlọ́run àti owó papọ̀.”
13 Bowayan orot ta’imon men karam boro orot gagamih rou’ab isah nabow, baise nakok bowamih orot ta nab naatu ta nihamiy, o orot ta isan nisnubanub naatu ta isan niskwarakwarab. O men karam boro God naatu Kabay hairi isah inabow.”
14 Àwọn Farisi, tí wọ́n ní ojúkòkòrò sì gbọ́ gbogbo nǹkan wọ̀nyí, wọ́n sì yọ ṣùtì sí i.
14 Pharisee Jesu eo hima hinonowar himisir Jesu hi’i’iyab himarib, anayabin i kabay hai momorob.
15 Ó sì wí fún wọn pé, “Ẹ̀yin ni àwọn tí ń dá àre fún ara yín níwájú ènìyàn; ṣùgbọ́n Ọlọ́run mọ ọkàn yín, nítorí ohun ti a gbéga lójú ènìyàn, ìríra ni níwájú Ọlọ́run.
15 Jesu misir iuwih eo, “Kwa sabuw matahimaim kwasisinaf gewas saise sabuw iti orot gewas rauwamih, baise God kwa dogor wanawanan etei i nuwatet sawar. Anayabin sawar nati na’atube sabuw hi’itah gagamih hirouw teora’ara’at, God matanamaim nati sawar i hai yabih en.
16 “Òfin àti àwọn wòlíì ń bẹ títí di ìgbà Johanu, Láti ìgbà náà wá ni a ti ń wàásù ìròyìn ayọ̀ ìjọba Ọlọ́run, olúkúlùkù sì ń fi ipá wọ inú rẹ̀.
16 Moses ana ofafar naatu dinab oro’orot hai tur imaim hibinan hinan John Baptist ana veya’amaim tit. Baise boun i Tur Gewasin God ana aiwob isan hibusuruf tibibinan, naatu sabuw moumurih na’in hisinaftobon hibusuruf tirur.
17 Ṣùgbọ́n ó rọrùn fún ọ̀run òun ayé láti kọjá lọ, ju kí èyí tí ó kéré jù nínú òfin kí ó yẹ.
17 Mar tafaram hairi i hamehamen maiyow boro sahiniwa’an, baise ofafar Buk Atamaninamaim hikikirum ana kouk yowanen kikimin ta boro men hinakusa’ir.
18 “Ẹnikẹ́ni tí ó bá kọ aya rẹ̀ sílẹ̀, tí ó sì gbé ẹlòmíràn ní ìyàwó, ó ṣe panṣágà: ẹnikẹ́ni tí ó bá sì gbé, ẹni tí ọkọ rẹ̀ kọ̀sílẹ̀ ní ìyàwó náà, ó ṣe panṣágà.
18 Orot yait aawan nakwahir, babin ta nabi’aawan i ana moser takweb, naatu orot yait nati babin hikwahir ma’am bai ebi’aawan i auman ana moser takweb.
19 “Ǹjẹ́ ọkùnrin ọlọ́rọ̀ kan wà, tí ó ń wọ aṣọ elése àlùkò àti aṣọ àlà dáradára, a sì máa jẹ dídùndídùn lójoojúmọ́.
19 “Marasika orot ta sawar wairafin ma’am ana veya, ana sawar etei gewasih, ana bar tot samir wanawanan ma mar etei hiyuw bow nan douduf in re’er.
20 Alágbe kan sì wà tí à ń pè ní Lasaru, tí wọ́n máa ń gbé wá kalẹ̀ lẹ́bàá ọ̀nà ilé rẹ̀, ó kún fún ooju,
20 Naatu ana bar ufunane fur awanamaim i orot wabin Lazarus, yababan wairafin biyan fehefeheriy, mar etei nati’imaim teyare ema efefeyan.
21 Òun a sì máa fẹ́ kí a fi èérún tí ó ti orí tábìlì ọlọ́rọ̀ bọ́ sílẹ̀ bọ́ òun, àwọn ajá sì wá, wọ́n sì fá a ní ooju lá.
21 Ana kok i mi’itube orot ana bay taa momor gem babanamaim hitare’er i tabow taa, bi’akir naatu haru auman tena ana feher teremarem.
22 “Ó sì ṣe, alágbe kú, a sì ti ọwọ́ àwọn angẹli gbé e lọ sí oókan àyà Abrahamu: ọlọ́rọ̀ náà sì kú pẹ̀lú, a sì sin ín;
22 Basit veya ta orot yababan wairafin morob tounamatar hire hinawiy hin maramaim Abraham biyasisir biyan hitit sisibinamaim mare. Naatu orot sawar wairafin morob hibai hire hiyai.
23 Ní ipò òkú ni ó gbé ojú rẹ̀ sókè, ó ń bẹ nínú ìjìyà oró, ó sì rí Abrahamu ní òkèrè, àti Lasaru ní oókan àyà rẹ̀.
23 Ayubin in wairaf wanatowanin wan yen biyababan gagamin maiyow bai, nuwra’at no yate ef yok na’in Abraham itin, sisibinamaim Lazarus batabat.
24 Ó sì ké, ó wí pé, ‘Baba Abrahamu, ṣàánú fún mi, kí o sì rán Lasaru, kí ó tẹ orí ìka rẹ̀ bọ omi, kí ó sì fi tù mí ní ahọ́n; nítorí èmi ń joró nínú ọ̀wọ́n iná yìí.’
24 Basit eaf ra’at, ‘Tamai Abraham! Ayu wairaf e’arahu biyababan gagamin na’in abaib, kukabibiru Lazarus kwiyafar uman harew yan eotore menau inub, menau tobeya!’
25 “Ṣùgbọ́n Abrahamu wí pé, ‘Ọmọ, rántí pé, nígbà ayé rẹ, ìwọ ti gba ohun rere tìrẹ, àti Lasaru ohun búburú, ṣùgbọ́n nísinsin yìí ara rọ̀ ọ́, ìwọ sì ń joró.
25 Baise Abraham eo, ‘Natu inanot o tafaramamaim ima’am ana veya, sawar gewasih etei o isa karam. Lazarus ana sawar i kakafih. Baise boun i Lazarus ana veya tit ebiyasisir naatu o ayababan ana veya tit kubiyababan.
26 Àti pẹ̀lú gbogbo èyí, a gbé ọ̀gbun ńlá kan sí agbede-méjì àwa àti ẹ̀yin, kí àwọn tí ń fẹ́ má ba á le rékọjá láti ìhín lọ sọ́dọ̀ yín, kí ẹnikẹ́ni má sì le ti ọ̀hún rékọjá tọ̀ wá wá.’
26 Naatu ata founamaim i ku’itin, fan gagamin na’in inu’in, imih sabuw iyab aki biyai’ine boro men karam o isa hinarabon, na’atube o biyane aki isai men karam boro hinarabon.’
27 “Ó sì wí pé, ‘Ǹjẹ́ mo bẹ̀ ọ́, baba, kí ìwọ kí ó rán Lasaru lọ sí ilé baba mi,
27 Basit orot sawar wairafin eo, ‘Tamai Abraham abifefeyani, Lazarus iniyafar nan tamai ana bar natit.
28 nítorí mo ní arákùnrin márùn-ún; kí ó lè rò fún wọn kí àwọn kí ó má ba á wá sí ibi oró yìí pẹ̀lú.’
28 Anayabin nati’imaim ayu taitu nah etei five tema’am nimatnuwih, saise i auman men hinan iti biyababan ana efanamaim hinatit biyah nababanamih.’
29 “Abrahamu sì wí fún un pé, ‘Wọ́n ní Mose àti àwọn wòlíì; kí wọn kí ó gbọ́ tiwọn.’
29 Baise Abraham iya’afut eo, ‘Tait i Moses ema’am naatu dinab oro’orot tema’am, boro i hinimatnuwih naatu abisa hinao’o, nowar hina kok tur hinanowar.’
30 “Ó sì wí pé, ‘Bẹ́ẹ̀ kọ́, Abrahamu baba; ṣùgbọ́n bí ẹnìkan bá ti inú òkú tọ̀ wọ́n lọ, wọn ó ronúpìwàdà.’
30 Orot sawar wairafin iya’afut eo, ‘Tamai Abraham, nati i men karam, baise ana gewasin orot ta morobone namatabir maiye nan hai tur na’owen boro hai bowabow kakafih tisisinaf hinihamiyen hina’in tabir yawas gewasin hinab.’
31 “Ó sì wí fún un pé, ‘Bí wọn kò bá gbọ́ ti Mose àti ti àwọn wòlíì, a kì yóò yí wọn ní ọkàn padà bí ẹnìkan tilẹ̀ ti inú òkú dìde.’ ”
31 Baise Abraham iya’afut maiye eo. ‘Moses naatu dinab oro’orot hinao men hinanowar hai yawas hinabobotabir na’at, orot morobone nan nao boro men hai yawas hinabotabir.’”
Atalhos do teclado
- Capítulo anterior←
- Próximo capítulo→
- Versículo anteriork
- Próximo versículoj
- Limpar seleçãoEsc
- Esta ajuda?
Estude este capítulo no WhatsApp
Peça à IA da Bíblia Fala para explicar Lucas 16, comparar traduções ou montar um estudo — tudo direto pelo WhatsApp.