Lucas 15
Biblica® ní oore ọ̀fẹ́ láti lo Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde-Òní (YOR) vs AAI
1 Gbogbo àwọn agbowó òde àti àwọn ẹlẹ́ṣẹ̀ sì súnmọ́ ọn láti gbọ́ ọ̀rọ̀ rẹ̀.
1 Ana veya ta kabay o’onayah naatu sabuw kakafih Jesu ana tur nowaramih hiru’ay.
2 Àti àwọn Farisi àti àwọn akọ̀wé ń kùn pé, “Ọkùnrin yìí ń gba ẹlẹ́ṣẹ̀, ó sì ń bá wọn jẹun.”
2 Baise Pharisee naatu Ofafar Bai’obaiyenayah yah so’ar higam hio, “Iti orot sabuw kakafih hai merar yi buwih bairi hima hi’aa tetomatom kwa’itih.”
3 Ó sì pa òwe yìí fún wọn, pé,
3 Basit Jesu oroubonamaim iuwih eo,
4 “Ọkùnrin wo ni nínú yín, tí ó ní ọgọ́rùn-ún àgùntàn, bí ó bá sọ ọ̀kan nù nínú wọn, tí kì yóò fi mọ́kàndínlọ́gọ́rùn-ún yokù sílẹ̀ ni ijù tí kì yóò sì tọ ipasẹ̀ èyí tí ó nù lọ, títí yóò fi rí i?
4 “O ta a bobaituw sheep etei 100 hitama’am, naatu ta’imon takakasiy boro mi’itube itasinaf? A bobaituw 99 boro raiyarayar yan dihamiyih hitama, naatu a sheep kakasiy boro itanunuwih itatita’uribo nuhi tafot.
5 Nígbà tí ó bá sì rí i tán, yóò gbé e lé èjìká rẹ̀ pẹ̀lú ayọ̀.
5 Naatu itabaib ana veya boro itiyasisir gagamin maiyow, ita’abar itan.
6 Nígbà tí ó bá sì dé ilé yóò pe àwọn ọ̀rẹ́ àti aládùúgbò rẹ̀ jọ, yóò sì wí fún wọn pé, ‘Ẹ bá mí yọ̀; nítorí tí mo ti rí àgùntàn mi tí ó nù.’
6 A bar taituwa, a ofonah etei ita’af ayuwih hai tur ita’owen, ‘Kwana bairit taniyasisir, anayabin ayu au sheep kakasiy i abaika.’
7 Mo wí fún yín, gẹ́gẹ́ bẹ́ẹ̀ ni ayọ̀ yóò wà ní ọ̀run lórí ẹlẹ́ṣẹ̀ kan tí ó ronúpìwàdà, ju lórí olóòtítọ́ mọ́kàndínlọ́gọ́rùn-ún lọ, tí kò nílò ìrònúpìwàdà.
7 A tur ao’owen, ef i nati na’atube, orot ta’imon bowabow kakafinane dogor baikitabir ebaib isan maramaim i tibiyasisir gagamin maiyow, men sabuw 99 gewas hirouw kakafih auman tema’am na’atube’emih.
8 “Tàbí obìnrin wo ni ó ní owó fàdákà mẹ́wàá bí ó bá sọ ọ̀kan nù, tí kì yóò tan fìtílà, kí ó fi gbá ilé, kí ó sì wá a gidigidi títí yóò fi rí i?
8 Itinin tabo iti na’atube, babin ana kabay ten kina ana fofonin yai inu’in one kina kasiy, naatu babin notanot men karam misir ramef ito’ab bar wanawanan yahib, huhun etei nuwet inan ana kabay tita’ur.
9 Nígbà tí ó sì rí i, ó pe àwọn ọ̀rẹ́ àti àwọn aládùúgbò rẹ̀ jọ, ó wí pé, ‘Ẹ bá mi yọ̀; nítorí mo rí owó fàdákà tí mo ti sọnù.’
9 Naatu ana kabay baib ana veya ana ofonah naatu tain tuwan etei e’af ayuwih eo, ‘Kwanan bairit taniyasisir, anayabin au kabay kakasiy i abaika.’
10 Mo wí fún yín, gẹ́gẹ́ bẹ́ẹ̀ ni ayọ̀ ń bẹ níwájú àwọn angẹli Ọlọ́run lórí ẹlẹ́ṣẹ̀ kan tí ó ronúpìwàdà.”
10 Imih a tur ao’owen, ef i nati na’atube, God ana tounamatar maramaim orot ta’imon bowabow kakafin wairafin ana kakafihine dogor baikitabir baib isan boro yasisir gagamin na’in hinab.”
11 Ó sì wí pé ọkùnrin kan ní ọmọ méjì:
11 Jesu iban maiye oroubon ta eo, “Ana veya ta orot natunatun rou’ab bairi hima’am.
12 “Èyí àbúrò nínú wọn wí fún baba rẹ̀ pé, ‘Baba, fún mi ní ìní tí ó kàn mí.’ Ó sì pín ohun ìní rẹ̀ fún wọn.
12 Natun uf misir tamah isan eo, ‘Tamai ayu akokok au nowau sawar inakusib initu.’ Tamah misir sawar etei bai natunatun hairi isah ana fofonin kusib faramih.
13 “Kò sì tó ọjọ́ mélòó kan lẹ́yìn náà, èyí àbúrò kó ohun gbogbo tí ó ní jọ, ó sì mú ọ̀nà àjò rẹ̀ pọ̀n lọ sí ilẹ̀ òkèrè, níbẹ̀ ni ó sì gbé fi ìwà wọ̀bìà ná ohun ìní rẹ̀ ní ìnákúnàá.
13 Naatu veya bai’ab na’atube sasawar ufunamaim kek uf ana sawar bobuna misir tafaram ta ef yok na’in imaim remor in. Naatu nati’imaim ma ana kabay etei asir isaroun kwanikwaniy sawar.
14 Nígbà tí ó sì ba gbogbo rẹ̀ jẹ́ tan, ìyàn ńlá wá mú ní ilẹ̀ náà; ó sì bẹ̀rẹ̀ sí di aláìní.
14 Ana kabay isaroun kwanikwaniy in sasawar ufunamaim, baimar kakafin nati tafaramamaim tit, kek busuruf aa morob.
15 Ó sì fi ara rẹ sọfà fun ọ̀kan lára àwọn ọmọ ìlú náà; òun sì rán an lọ sí oko rẹ̀ láti tọ́jú ẹlẹ́dẹ̀.
15 Naatu misir in nati’imaim tafaram matuwan orot ta biyan tit, naatu nati orot bai iyafar in for baibituw ana efanamaim tit ma for ituw. Orot natun kasikasiyin for hai dam ana efanamaim|alt="prodigal son in pig pen" src="cn01759B.tif" size="col" loc="Luk 15.15" copy="©1978 David C. Cook Publishing Co." ref="15.15"
16 Ayọ̀ ni ìbá fi jẹ oúnjẹ tí àwọn ẹlẹ́dẹ̀ ń jẹ ní àjẹyó, ṣùgbọ́n ẹnikẹ́ni kò sì fi fún un.
16 Aa morob kok kwanekwan for hai bay hi’aa turih taa, baise men yait ta abisa itin eaanimih.
17 “Ṣùgbọ́n nígbà tí ojú rẹ̀ wálẹ̀, ó ní ‘Mélòó mélòó àwọn alágbàṣe baba mí ni ó ní oúnjẹ àjẹyó, àti àjẹtì, èmi sì ń kú fún ebi níhìn-ín.
17 “Veya ta ma binotanot ana notamaim nuhin taseb eo, ‘Tamai ana bowayah moumurih na’in i aurih bay karam hi’aa hitom yah iw tema’am, baise ayu iti’imaim aa amomorob.
18 Èmi ó dìde, èmi ó sì tọ baba mi lọ, èmi ó sì wí fún un pé, Baba, èmí ti dẹ́ṣẹ̀ sí ọ̀run, àti níwájú rẹ,
18 Gewasin ayu boro ana misir anan tamai biyan anatit ana tur ana’owen anao. Tamai ayu i bowabow kakafin maiyow asinaf God matanamaim, naatu o auman matamaim.
19 èmi kò sì yẹ, ní ẹni tí à bá pè ní ọmọ rẹ mọ́; fi mí ṣe ọ̀kan nínú àwọn alágbàṣe rẹ.’
19 Isan imih ayu i men karam boro o natumih inabuwu maiye, baise a bowayah sabuw ibaiyanih isa tebowabow na’atube ayu isou inasinaf.’
20 Ó sì dìde, ó sì tọ baba rẹ̀ lọ.
20 Iti na’atube eo, basit misir tamah isan matabir maiye remor na bar ariyan titit auman, tamah bat nuwanuw natun nan itin, dogoron wanawanan yababan awan karatan, nunuw in natun bai rouh mamay. Regah natun mamatabir ana merar yi ebaib|alt="father meeting returning son" src="CN01761B.TIF" size="col" loc="Luk 15.20" copy="©1978 David C. Cook Publishing Co." ref="15.20-21"
21 “Ọmọ náà sì wí fún un pé, Baba, èmi ti dẹ́ṣẹ̀ sí ọ̀run, àti níwájú rẹ, èmi kò yẹ ní ẹni tí à bá pè ní ọmọ rẹ mọ́!
21 Baise kek eo, ‘Tamai ayu i bowabow kakafin maiyow God isan asinaf kakaf na’atube o isa asinaf kakaf, isan imih ayu i men karam o natumih inabuwu.’
22 “Ṣùgbọ́n baba náà wí fún àwọn ọmọ ọ̀dọ̀ rẹ̀ pé, Ẹ mú ààyò aṣọ wá kánkán, kí ẹ sì fi wọ̀ ọ́; ẹ sì fi òrùka bọ̀ ọ́ lọ́wọ́, àti bàtà sí ẹsẹ̀ rẹ̀:
22 Baise regah ana bowayah iuwih eo, ‘Saise kwan faifuw boubun gewasin kwabai natu kwai’us, uman ring kwaiyoun naatu a baibiyon boubun kwabai kwana an kwaiyoun.
23 Ẹ sì mú ẹgbọrọ màlúù àbọ́pa wá, kí ẹ sì pa á, kí a máa ṣe àríyá.
23 Naatu for biyan kabinitut kwarab kwaitab tana’aan taniyasisir.
24 Nítorí ọmọ mi yìí ti kú, ó sì tún yè, ó ti nù, a sì rí i. Wọ́n sì bẹ̀rẹ̀ sí í ṣe àríyá.
24 Anayabin ayu natu i morob na’atube ma’am, boun i yawas maiye, naatu kasiy na’atube ma’am boun i tatita’ur maiye.’ Naatu douduf hitaiy re.
25 “Ṣùgbọ́n ọmọ rẹ̀ èyí ẹ̀gbọ́n ti wà ní oko: bí ó sì ti ń bọ̀, tí ó súnmọ́ etí ilé, ó gbọ́ orin àti ijó.
25 Baise nati ana veya’amaim regah natun ain ma sheep kakaifen matabir na bar biyubin auman hiyasisir hibenaben douduf nidun nowar.
26 Ó sì pe ọ̀kan nínú àwọn ọmọ ọ̀dọ̀ wọn, ó béèrè, kín ni a mọ nǹkan wọ̀nyí sí?
26 Naatu bowayah orot ta eaf na ibatiy, ‘Abisa emamatar?’
27 Ó sì wí fún un pé, ‘Arákùnrin rẹ dé, baba rẹ sì pa ẹgbọrọ màlúù àbọ́pa, nítorí tí ó rí i padà ní àlàáfíà àti ní ìlera.’
27 Orot eo, ‘O tai matabir maiye na bar tit, imih tamat for biyan kabinitut rab abiyasisir, anayabin gewasinamaim matabir maiye na bar tamat biyan tit.’
28 “Ó sì bínú, ó sì kọ̀ láti wọlé; baba rẹ̀ sì jáde, ó sì wá í ṣìpẹ̀ fún un.
28 Basit orot ain yan so’ar kwanekwan, men kok boro bar wanawanan tarun. Naatu tamah tit natun ain eobaibinub runamih iu.
29 Ó sì dáhùn ó wí fún baba rẹ̀ pé, ‘Wò ó, láti ọdún mélòó wọ̀nyí ni èmi ti ń sìn ọ́, èmi kò sì rú òfin rẹ rí, ìwọ kò sì tí ì fi ọmọ ewúrẹ́ kan fún mi, láti fi bá àwọn ọ̀rẹ́ mi ṣe àríyá.
29 Baise orot ain eo, ‘Tamai kwamur manin maiyow akirwairafih na’atube isa abow men kafa’imo fana asair. Naatu au yasisir isan abisa itu? En anababatun! Men kafa’imo goat ta itu au ofonah bairi ai yasisiramih. Aiyab!
30 Ṣùgbọ́n nígbà tí ọmọ rẹ yìí dé, ẹni tí ó fi panṣágà fi ọrọ̀ rẹ̀ ṣòfò, ìwọ sì ti pa ẹgbọrọ màlúù àbọ́pa fún un.’
30 Baise o natu kabay etei baibin baiwa’an kwanekwaneyah biyahimaim isaroun kwanikwaniy sawar, naatu matabir na bar titit, o isan for biyan kabinitut irab kwabiyasisir.’
31 “Ó sì wí fún un pé, ‘Ọmọ, nígbà gbogbo ni ìwọ ń bẹ lọ́dọ̀ mi, ohun gbogbo tí mo sì ní, tìrẹ ni.
31 Regah natun ain iya’afut eo, ‘Natu o i airit mar etei iti’imaim tama’am, naatu ayu au sawar tutufin etei iti baremaim tema’am i o nowa, men yait ta nowanamih.
32 Ó yẹ kí a ṣe àríyá kí a sì yọ̀: nítorí arákùnrin rẹ yìí ti kú, ó sì tún yè; ó ti nù, a sì rí i.’ ”
32 Baise tanaben taniyasisir, anayabin tai morobobe yumatan taboyauw tama’am boun yawas maiye, naatu kasiyobe ma’am boun tatita’ur maiye.’”
Atalhos do teclado
- Capítulo anterior←
- Próximo capítulo→
- Versículo anteriork
- Próximo versículoj
- Limpar seleçãoEsc
- Esta ajuda?
Estude este capítulo no WhatsApp
Peça à IA da Bíblia Fala para explicar Lucas 15, comparar traduções ou montar um estudo — tudo direto pelo WhatsApp.