Lucas 14
Biblica® ní oore ọ̀fẹ́ láti lo Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde-Òní (YOR) vs AAI
1 Nígbà tí ó wọ ilé ọ̀kan nínú àwọn olórí Farisi lọ ní ọjọ́ ìsinmi láti jẹun, wọ́n sì ń ṣọ́ ọ.
1 Baiyarir ana veya ta, Pharisee hai ukwarin ana baremaim Jesu bay aamih na, baise sabuw nati’imaim hima’ama i Jesu hibimtitiy.
2 Sì kíyèsi i, ọkùnrin kan tí ó ní ara wíwú níwájú rẹ̀.
2 Naatu nati’imaim orot ta an uman hikurut ma’am yawas isan na Jesu nanamaim tit.
3 Jesu sì dáhùn ó wí fún àwọn amòfin àti àwọn Farisi pé, “Ǹjẹ́ ó tọ́ láti mú ni láradá ní ọjọ́ ìsinmi, tàbí kò tọ́?”
3 Baise Jesu Pharisee naatu ofafar so’ob wairafih ibatiyih, “Baiyarir ana veya’amaim ata ofafar ebibasit boro orot babin taniyawas ai en?”
4 Wọ́n sì dákẹ́. Ó sì mú un, ó mú un láradá, ó sì jẹ́ kí ó lọ.
4 Baise men tur ta hio. Basit Jesu orot bai iyawas naatu iu ana ubar in.
5 Ó sì dáhùn ó sì wí fún wọn pé, “Ta ni nínú yín tí kẹ́tẹ́kẹ́tẹ́ tàbí màlúù rẹ̀ yóò bọ́ sínú ihò, tí kì yóò sì fà á sókè lójúkan náà ní ọjọ́ ìsinmi?”
5 Imaibo ibatiyih, “O orot ta natu o a bobaituw Baiyarir ana veya hub tare’er na’at boro itihamiy ta’in tamorob, o boro mata takabiy itarowen ra’ah tayen?”
6 Wọn kò sì lè dá a lóhùn mọ́ sí nǹkan wọ̀nyí.
6 Sabuw baiyafutinamih hikasiy hima kwanekwan.
7 Ó sì pa òwe kan fún àwọn tí ó pè é wá jẹun, nígbà tí ó ṣàkíyèsí bí wọ́n ti ń yan ipò ọlá; ó sì wí fún wọn pé,
7 Nanawan sabuw afa bay aa ana efanamaim efan gewasih hirurubinen Jesu itih, basit oroubonamaim sabuw iuwih eo,
8 “Nígbà tí ẹnìkan bá pè ọ́ wá sí ibi ìyàwó, má ṣe jókòó ní ipò ọlá; kí ó má ba à jẹ́ pé, a ó pe ẹni tí ó lọ́lá jù ọ́ lọ.
8 “Orot ta, tabin ana hiyuw isan a kob nan na’uwi inanan men inayen efan gewasinamaim inamare’emih, anayabin orot gagamin ta auman ana kob hinan boro enan.
9 Nígbà tí ẹni tí ó pè ọ́ bá dé, a sì wí fún ọ pé, ‘Fún ọkùnrin yìí ní ààyè!’ Ìwọ á sì wá fi ìtìjú mú ipò ẹ̀yìn.
9 Imih orot hiyuw matuwan airi a kob na uwi kwanan boro nayen na’uwi, ‘Aro o kumisir haw kure, tura eyen iti’imaim emare,’ o boro biya’ohow auman inamisir haw inare.
10 Ṣùgbọ́n nígbà tí a bá pè ọ́, lọ kí o sì jókòó ní ipò ẹ̀yìn; nígbà tí ẹni tí ó pè ọ́ bá dé, kí ó lè wí fún ọ pé, ‘Ọ̀rẹ́, bọ́ sókè!’ Nígbà náà ni ìwọ ó ní ìyìn lójú àwọn tí ó bá ọ jókòó ti oúnjẹ.
10 Imih a kob hinan hina’uwi inanan, haw inamare, saise orot hiyuw matuwan a kob nan boro na’uwi, ‘Au begon kuyen seb ir yan kumare,’ o boro yasisir auman ina misir seb inayen efan gewasin inab nanawan afa bairi ir yan kwanama.
11 Nítorí ẹnikẹ́ni tí ó bá gbé ara rẹ̀ ga, ni a ó rẹ̀ sílẹ̀; ẹnikẹ́ni tí ó bá sì rẹ ara rẹ̀ sílẹ̀, ni a ó sì gbéga.”
11 Anayabin orot yait taiyuwin i’itin ra’ah, God boro nab haw nayare, baise orot yait taiyuwin i’itin furuw God boro nayara’ah orot gagamin namatar.”
12 Nígbà náà ni ó sì wí fún alásè tí ó pè é pé, “Nígbà tí ìwọ bá ṣe àsè má ṣe pe àwọn arákùnrin rẹ tàbí àwọn ìbátan rẹ, tàbí àwọn ọlọ́rọ̀ aládùúgbò rẹ̀; nítorí kí wọn má ṣe pè ọ́ padà láti san ẹ̀san padà.
12 Imaibo Jesu bar matuwan hairi bay aamih iu nan isan eo, “Auyit o rabirab ana bay inabitab, men o a of, tait bairi a rara ta’imon, taituwa o isusu’ubih, naatu a’ofonah guguw wairafih ina’uwih hinan bairi kwana’aamih. Anayabin o nati na’atube inasinaf, i boro a bay wan hitab hinit inaa.
13 Ṣùgbọ́n nígbà tí ìwọ bá ṣe àsè, pe àwọn tálákà, àwọn alábùkún ara, àwọn amúnkùn ún, àti àwọn afọ́jú:
13 Baise hiyuw inabowabow ana veya, yababan wairafih, ah umah kurut, ah umah duboh, matah fim, ina’uwih hinan bairi bay kwanaa,
14 Ìwọ ó sì jẹ́ alábùkún fún; nítorí wọn kò ní ohun tí wọn ó fi san án fún ọ, ṣùgbọ́n a ó san án fún ọ ní àjíǹde, àwọn olóòtítọ́.”
14 saise God boro baigegewasin nit. Anayabin sabuw nati boro men a hiyuw wan hinay hinit, baise sabuw gewasih morobone hinamimisir ana veya’amaim, abisa isisinaf isan God boro imaim a wayow nit.”
15 Nígbà tí ọ̀kan nínú àwọn tí wọ́n jọ jókòó gbọ́ nǹkan wọ̀nyí, ó wí fún Jesu pé, “Alábùkún ni fún ẹni tí yóò jẹ oúnjẹ àsè ní ìjọba Ọlọ́run!”
15 Orot ta nati bay ana gemamaim hairi hima’am iti tur nowar, basit Jesu isan eo, “Orot yait God ana aiwobomaim hiyuw isan namamare boro yasisir gagamin maiyow nab.”
16 Jesu dá a lóhùn pé, “Ọkùnrin kan ṣe àsè alẹ́ ńlá, ó sì pe ènìyàn púpọ̀.
16 Baise Jesu oroubonamaim orot iu, “Veya ta orot ana hiyuw bogaigiwas, naatu sabuw maumurih na’in hai kob in.
17 Ó sì rán ọmọ ọ̀dọ̀ rẹ̀ ní wákàtí àsè alẹ́ náà láti sọ fún àwọn tí a ti pè pé, ‘Ẹ wá; nítorí ohun gbogbo ṣetán!’
17 Naatu hiyuw aanin isan ana veya natit, tur iyafar ana ofonah isah eo, ‘Kwanan hiyuw tanaa, sawar etei ai moyab sawar.’
18 “Gbogbo wọn sì bẹ̀rẹ̀ sí ṣe àwáwí ohun kan. ‘Èkínní wí fún un pé, mo ra ilẹ̀ kan, mo sì fẹ́ lọ wò ó wò, mo bẹ̀ ọ́ ṣe gáfárà fún mi.’
18 Baise etei hikwahir tur ta ta hibow hitit, orot ta eo, ‘Ayu au me boubun atubun ananutitiyimih anan, a tur ao’owen men karam boro anan.’
19 “Èkejì sì wí pé, ‘Mo ra àjàgà màlúù márùn-ún, mo sì ń lọ wò wọ́n wò: mo bẹ̀ ọ́ ṣe gáfárà fún mi.’
19 Orot ta eo, ‘Ayu au cow baubuh etei ten atobon, imih baimanamen isan anan, a tur ao’owen men karam boro anan.’
20 “Ẹ̀kẹta sì wí pé, ‘Mo ṣẹ̀ṣẹ̀ gbéyàwó, nítorí náà ni èmi kò fi lè wá.’
20 Naatu orot ta eo, ‘Ayu i boubun atabin, imih men karam boro aawau anihamiy nama airit tanan.’
21 “Ọmọ ọ̀dọ̀ náà sì padà dé, ó sọ nǹkan wọ̀nyí fún olúwa rẹ̀. Nígbà náà ni baálé ilé bínú, ó wí fún ọmọ ọ̀dọ̀ rẹ̀ pé, ‘Jáde lọ sí ìgboro, àti sí òpópó ọ̀nà, kí o sì mú àwọn tálákà, àti àwọn amúnkùn ún, àti àwọn arọ, àti àwọn afọ́jú wá sí ìhín yìí.’
21 Akir wairafin matabir maiye na orot gagamin ana tur eowen. Bar matuwan yan so’ar ana akir wairafin iu, ‘Saife kutit kwen ef gagamih yahimaim naatu bar merar hai ef yahimaim sabuw kakafih, yababan wairafih, ah umah kurut, ah umah murubih, matan fim initeten inan hiyuw tanaa.’
22 “Ọmọ ọ̀dọ̀ náà sì wí pé, ‘Olúwa a ti ṣe bí o ti pàṣẹ, ààyè sì ń bẹ síbẹ̀.’
22 Naatu akir wairafin eo, Regah, io na’atube i asinaf, baise bar awan i men karatan.’
23 “Olúwa náà sì wí fún ọmọ ọ̀dọ̀ náà pé, ‘Jáde lọ sí òpópó, àti sí ọ̀nà ọgbà, kí o sì rọ̀ wọ́n láti wọlé wá, kí ilé mi lè kún.
23 Imaibo orot ana akir wairafin iu, ‘Kutit kwen bar merar hai ef gagamih yahimaim, naatu ef gidigidih rewahimaim, sabuw iyab nati’imaim ina’i’itih inabuwih kwanan, saise au bar awan nakaratan.’
24 Nítorí mo wí fún yín, ẹnikẹ́ni nínú àwọn ènìyàn wọ̀nyí tí a ti pè, kì yóò tọ́wò nínú àsè ńlá mi!’ ”
24 A tur ao’owen sabuw iyab wan hai kob anan i men hikok imih boro men yait ta au hiyuw nakatubunimih!”
25 Àwọn ọ̀pọ̀ ìjọ ènìyàn ń bá a lọ; ó sì yípadà, ó sì wí fún wọn pé,
25 Ana veya ta sabuw rau’ay gagamin na’in Jesu hi’ufunun bairi hinan tatabir iuwih eo,
26 “Bí ẹnìkan bá tọ̀ mí wá, tí kò sì kórìíra baba àti ìyá, àti aya, àti ọmọ, àti arákùnrin, àti arábìnrin, àní àti ọkàn ara rẹ̀ pẹ̀lú, kò lè ṣe ọmọ-ẹ̀yìn mi.
26 “Orot yait ayu ebi’ufnunu, baise hinah, tamah, aawan natunatun, taitin, ruburubun isah ebiyabow naatu i taiyuwin auman ana yawas isan ebiyabow, nati orot i men karam boro ayu ni’ufnunu.
27 Ẹnikẹ́ni tí kò bá ru àgbélébùú rẹ̀, kí ó sì máa tọ̀ mí lẹ́yìn, kò lè ṣe ọmọ-ẹ̀yìn mi.
27 Orot yait ana onaf na’abar ayu ananamaim ni’ufnunu airi ananan i ayu au bai’ufununayan.
28 “Nítorí ta ni nínú yín tí ń pète láti kọ́ ilé ìṣọ́, tí kì yóò kọ́kọ́ jókòó kí ó ṣírò iye owó rẹ̀, bí òun ní tó tí yóò fi parí rẹ̀.
28 Orot ta ana bar wowabinamih boro men asir nawowab kwaniyimih, baise wan i boro namare ana bar ayubin nayakitifuw, ana baiyan boro bai’ab naatu ana kabay karam boro iti bar nawowab nisawar ai en.
29 Kí ó má ba à jẹ́ pé nígbà tí ó bá fi ìpìlẹ̀ ilé sọlẹ̀ tan, tí kò lè parí rẹ̀ mọ́, gbogbo àwọn tí ó rí i a bẹ̀rẹ̀ sí í fi í ṣe ẹlẹ́yà.
29 Anayabin ana kabay men nakakaram na’at boro tafah nararauwen ufunamaim wowabina’e nabat, naatu sabuw afa tafawat hinabatabat hina’itin boro hini’iyab hinamarib,
30 Wí pé, ‘Ọkùnrin yìí bẹ̀rẹ̀ sí kọ́ ilé, kò sì lè parí rẹ̀.’
30 hinao, ‘Iti orot bar wowabinamihibe busuruf tafawat rauwen naatu ihamiy ebatabat.’
31 “Tàbí ọba wo ni ó ń lọ bá ọba mìíràn jà, tí kì yóò kọ́kọ́ jókòó, kí ó sì gbèrò bí yóò lè fi ẹgbẹ̀rún mẹ́wàá (10,000) pàdé ẹni tí ń mú ogún ẹgbẹ̀rún (20,000) bọ̀ wá ko òun lójú?
31 Itinin tabo iti, aiwob orot ta ana baiyowayah etei 10,000 tabow, aiwob orot ta hairi baiyowamih tan, baise aiwob orot ta ana baiyowayah etei i 20,000 imih nati aiwob ta i boro tamare tama tanot, ‘Ayu karam boro nati aiwob orot airi aniyow?’
32 Bí bẹ́ẹ̀ kọ́, nígbà tí onítọ̀hún bá sì wà ní òkèrè, òun a rán ikọ̀ sí i, a sì bẹ̀rẹ̀ àdéhùn àlàáfíà.
32 Naatu tanotanot men takakaram na’at, i boro ef yok tama tur tiyafar aiwob turan hairi hitao tufuw hita’afuw.
33 Gẹ́gẹ́ bẹ́ẹ̀ ni, ẹnikẹ́ni tí ó wù kí ó ṣe nínú yín, tí kò kọ ohun gbogbo tí ó ní sílẹ̀, kò lè ṣe ọmọ-ẹ̀yìn mi.
33 Ef i nati ta’imon, orot yait nakok ayu bai’ufnunu’umih mat i ana sawar etei nakwahir nayaraiyen.
34 “Iyọ̀ dára: ṣùgbọ́n bí iyọ̀ bá di òbu, kín ni a ó fi mú un dùn?
34 Riy i gewasin, baise naniyan nabi’en boro hinisaroun, anayabin men karam boro hiniwa’an riy namatar maiye.
35 Kò yẹ fún ilẹ̀, bẹ́ẹ̀ ni kò yẹ fún ààtàn; bí kò ṣe pé kí a kó o dànù.
35 Naatu me yan ub yen gewas isan hinayayare boro men ana gewasin ta namatar, imih boro hinisaroun. Imih o yait tain ema’am inarub tur iti inanowar gewas!”
Atalhos do teclado
- Capítulo anterior←
- Próximo capítulo→
- Versículo anteriork
- Próximo versículoj
- Limpar seleçãoEsc
- Esta ajuda?
Estude este capítulo no WhatsApp
Peça à IA da Bíblia Fala para explicar Lucas 14, comparar traduções ou montar um estudo — tudo direto pelo WhatsApp.