Lucas 13

Biblica® ní oore ọ̀fẹ́ láti lo Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde-Òní (YOR) vs AAI

Sair da comparação
AAI TUR GEWASIN O BAIBASIT BOUBUN
1 Àwọn kan sì wá ní àkókò náà tí ó sọ ti àwọn ará Galili fún un, ẹ̀jẹ̀ ẹni tí Pilatu dàpọ̀ mọ́ ẹbọ wọn.
1 Nati ana veya’amaim sabuw afa hina hitit, Galilee sabuw sibor hiya’aya wanawanan Pilate rouw himomorob isan Jesu ana tur hi’owen.
2 Jesu sì dáhùn ó wí fún wọn pé, “Ẹ̀yin ṣe bí àwọn ará Galili wọ̀nyí ṣe ẹlẹ́ṣẹ̀ ju gbogbo àwọn ará Galili lọ, nítorí wọ́n jẹ irú ìyà bá-wọ̀n-ọn-nì?
2 Naatu Jesu iyafutih eo, “Kwanotanot Galilee wanawanan nati sabuw hai bowabow kakafih ra’at sabuw afa hinatabirih imih biyababan nati na’atube hibai himorob?
3 Mo wí fún yín, bí kò ṣe pé ẹ̀yin pẹ̀lú ronúpìwàdà, gbogbo yín ni yóò ṣègbé bẹ́ẹ̀ gẹ́gẹ́.
3 Baise en! A tur ao’owen bowabow kakafihine dogor baikitabir kwanab, baise boro kwanamorob i himomorob na’atube.
4 Tàbí àwọn méjìdínlógún, tí ilé ìṣọ́ ní Siloamu wó lù, tí ó sì pa wọ́n, ẹ̀yin ṣe bí wọ́n ṣe ẹlẹ́ṣẹ̀ ju gbogbo àwọn ènìyàn tí ń bẹ ní Jerusalẹmu lọ?
4 Naatu sabuw 18 Siloam bar gagamin tafan katub re rabih himomorob, kwanotanot Jerusalem wanawanan i akisih hai tafasar ra’at sabuw afa hinatabirih, imih nati na’atube himorob?
5 Mo wí fún yín, bí kò ṣe pé ẹ̀yin ronúpìwàdà, gbogbo yín ni yóò ṣègbé bẹ́ẹ̀ gẹ́gẹ́.”
5 Baise en! A tur ao’owen, bowabow kakafihine dogor baikitabir kwanab, baise boro kwanamorob i himomorob na’atube.”
6 Ó sì pa òwe yìí fún wọn pé, “Ọkùnrin kan ní igi ọ̀pọ̀tọ́ kan tí a gbìn sí ọgbà àjàrà rẹ̀; ó sì dé, ó ń wá èso lórí rẹ̀, kò sì rí nǹkan.
6 Imaibo Jesu oroubon ta iti na’atube eo, “Veya ta orot ana masaw wanawanan ai fafou tanum yen ra’at. Naatu veya ta ro’oh isan tit na nura’at baise men ro’on ta itin.
7 Ó sì wí fún olùṣọ́gbà rẹ̀ pé, ‘Sá à wò ó, láti ọdún mẹ́ta ni èmi ti ń wá í wo èso lórí igi ọ̀pọ̀tọ́ yìí, èmi kò sì rí nǹkan: ké e lulẹ̀; èéṣe tí ó fi ń gbilẹ̀ lásán pẹ̀lú?’
7 Basit nati masaw ana kaifinayan isan eo, ‘Aro, kwamur tounu wanawanan ai iti afe’enamaim ro’on men kafa’imo ta aitin. Akokok inatar nare asir bat ata me ebi’afiy.’
8 “Ó sì dáhùn ó wí fún un pé, ‘Olúwa, jọ̀wọ́ rẹ̀ ní ọdún yìí pẹ̀lú, títí èmi ó fi tu ilẹ̀ ìdí rẹ̀ yíká, títí èmi ó sì fi bu ìlẹ̀dú sí i.
8 Baise orot ai ana kaifinayan eo, ‘Regah inihamiy kwamur ta’imon nabat tana’itin, ayu boro anamaim hub anab hain ana yai tana’itin.
9 Bí ó bá sì so èso, o dara bẹ́ẹ̀: bí kò bá sì so, ǹjẹ́ lẹ́yìn èyí nì kí ìwọ kí ó ké e lulẹ̀.’ ”
9 Maras kwamur ai nabiw na’at basit gewasin, boro tanihamiy nabat, baise men nabiw na’at, imaibo boro inatar nare ina’afun.’”
10 Ó sì ń kọ́ni nínú Sinagọgu kan ní ọjọ́ ìsinmi.
10 Baiyarir ana veya ta Jesu na Kou’ay Baremaim ma sabuw bi’obaiyih.
11 Sì kíyèsi i, obìnrin kan wà níbẹ̀ tí ó ní ẹ̀mí àìlera, láti ọdún méjìdínlógún wá, ẹni tí ó tẹ̀ tán, tí kò le gbé ara rẹ̀ sókè bí ó ti wù kí ó ṣe.
11 Nati’imaim babin ta afiy kakafih hirab kwatut ma kwamur etei 18 sasawar i na run. Nati babin koun ana rarik i kwabibin, baimutufurin isan biwa’an men karam.
12 Nígbà tí Jesu rí i, ó pè é sí ọ̀dọ̀, ó sì wí fún un pé, “Obìnrin yìí, a tú ọ sílẹ̀ lọ́wọ́ àìlera rẹ.”
12 Jesu nuw babin i’itin ana veya, babin eaf na nanamaim bat. Imaibo eo, “Babin, a sawowone abiyawasi.”
13 Ó sì fi ọwọ́ rẹ̀ lé e, Lójúkan náà a sì ti sọ ọ́ di títọ́, ó sì ń yin Ọlọ́run lógo.
13 Naatu uman babin tafan yara’ah isan yoyoyoban ana veya, naniyan meyemeye babin koun ana rarik kwabeb inu’in mutufor misir bat God ana merar yi bora’ara’ah.
14 Olórí Sinagọgu sì kún fún ìrunú, nítorí tí Jesu mú ni láradá ní ọjọ́ ìsinmi, ó sì wí fún ìjọ ènìyàn pé, ọjọ́ mẹ́fà ní ń bẹ tí a fi í ṣiṣẹ́, nínú wọn ni kí ẹ̀yin kí ó wá kí á ṣe dídá ara yín, kí ó má ṣe ní ọjọ́ ìsinmi.
14 Kou’ay bar ana kaifenayan yan so’ar, anayabin Jesu Baiyarir ana veya’amaim babin iyawas, naatu sabuw iuwih, “Veya etei six wanawananamaim i tanabow naatu yawas kwana kokok nati veya’amaim kwanan yawas kwanab, baise men Baiyarir ana veya’amaim.”
15 Nígbà náà ni Olúwa dáhùn, ó sì wí fún un pé, “Ẹ̀yin àgàbàgebè, olúkúlùkù yín kì í tú màlúù tàbí kẹ́tẹ́kẹ́tẹ́ rẹ̀ kúrò ní ibùso, kì í sì í fà á lọ mu omi ní ọjọ́ ìsinmi.
15 Regah orot iya’afut eo, “Wanawanan rerekabih! Baiyarir ana veya kwa taita’imon a donkey o a ox men kwarufamen kwabow kwan harew kwaitih tetomatom?
16 Kò sì yẹ kí a tú obìnrin yìí tí í ṣe ọmọbìnrin Abrahamu sílẹ̀ ní ìdè yìí ní ọjọ́ ìsinmi, ẹni tí Satani ti dè, sá à wò ó láti ọdún méjìdínlógún yìí wá?”
16 Iti babin i Abraham uwan ta, Satan bai fatum wainab kwamur etei 18 sawar, naatu boun ana bai’akirane Baiyarir ana veya abobotait yawas baib isan asinaf kakaf?”
17 Nígbà tí ó sì wí nǹkan wọ̀nyí, ojú ti gbogbo àwọn ọ̀tá rẹ̀, gbogbo ìjọ ènìyàn sì yọ̀ fún ohun ìyanu gbogbo tí ó ṣe.
17 Iti na’atube eo ana veya ana rakit sabuw biyah eohow, baise sabuw moumurih na’in sawar gewasih sinaf hi’i’itan isan hiyasisir.
18 Ó sì wí pé, “Kín ni ìjọba Ọlọ́run jọ? Kín ni èmi ó sì fiwé?
18 Imaibo Jesu ibatiyih, “God ana aiwob itinin i mi’itube? Abisa biyanamaim boro anayai kwana’itin?
19 Ó dàbí hóró musitadi, tí ọkùnrin kan mú, tí ó sì sọ sínú ọgbà rẹ̀; tí ó sì hù, ó sì di igi ńlá; àwọn ẹyẹ ojú ọ̀run sì ń gbé orí ẹ̀ka rẹ̀.”
19 Itinin ta i orot ana ai momor ro’on bai in ana masawamaim tanum, naatu kuboun yen ra’at ai mamatar ana veya’amaim, mamu hina famefamenamaim hibatar hima’am na’atube.”
20 Ó sì tún wí pé, “Kín ni èmi ìbá fi ìjọba Ọlọ́run wé?
20 Jesu iban maiye ibatiyih, “God ana aiwob i boro abisa’amaim ana yai kwana’itin?
21 Ó dàbí ìwúkàrà, tí obìnrin kan mú, tí ó fi sínú òsùwọ̀n ìyẹ̀fun mẹ́ta, títí gbogbo rẹ̀ ó fi di wíwú.”
21 Ana itinin ta i babin ana faraw afuninamih bai tew gagamin wanawanan isuwai re yeast auman wanawanan nayai kamat ra’at yen tew awan kakaratan na’atube.”
22 Ó sì ń la àárín ìlú àti ìletò lọ, ó ń kọ́ni, ó sì ń rìn lọ sí Jerusalẹmu.
22 Imaibo Jesu au Jerusalem yen inan ana maramaim, bar merar gagamih naatu bar merar gidigidih imaim run tit, sabuw i’obaibiyih auman yen in.
23 Ẹnìkan sì bi í pé, Olúwa, díẹ̀ ha kọ ni àwọn tí a ó gbàlà?
23 Orot babin ta na Jesu ibatiy, “Regah o kunotanot boro sabuw matan ta’amo God yawas nitih?”
24 “Ẹ làkàkà láti gba ojú ọ̀nà tóóró wọlé, nítorí mo wí fún yín, ènìyàn púpọ̀ ni yóò wá ọ̀nà láti wọ̀ ọ́, wọn kì yóò sì lè wọlé.
24 “Kwanabow gewas etawan awan kukurinamaim kwanarun, anayabin sabuw moumurih na’in boro nati etawanamaim run isan hinasinaftobon, baise a tur ao’owen boro men nakaram.
25 Nígbà tí baálé ilé bá dìde lẹ́ẹ̀kan fùú, tí ó bá sí ti ìlẹ̀kùn, ẹ̀yin ó sì bẹ̀rẹ̀ sí í dúró lóde, tí ẹ ó máa kan ìlẹ̀kùn, wí pé, ‘Olúwa, Olúwa, ṣí i fún wa!’
25 Regah bar matuwan namisir etawan nahirihir kwa boro ufun kwanabat etawan kwanarukikitar kwanao, ‘Regah etawan kubotawiy arun,’ naatu i boro nao, ‘Ayu men aso’ob kwa iyab, naatu menane kwana.’
26 “Nígbà náà ni ẹ̀yin ó bẹ̀rẹ̀ sí wí pé, ‘Àwa ti jẹ, àwa sì ti mu níwájú rẹ, ìwọ sì kọ́ni ní ìgboro ìlú wa.’
26 Imaibo kwa boro kwaniya’afut kwanao, ‘Aki o bairi taa tatom, naatu ai bar ai meraramaim ibi’obaibiyi iso’ob, aisim kukakasiy.’
27 “Òun ó sì wí pé, ‘Èmi wí fún yín èmi kò mọ̀ ibi tí ẹ̀yin ti wá; ẹ lọ kúrò lọ́dọ̀ mi gbogbo ẹ̀yin tí ń ṣiṣẹ́ ẹ̀ṣẹ̀.’
27 Baise i boro nao maiye, ‘Ayu men aso’ob kwa iyab naatu menane kwana. Biyau’umaim kwatit sa’ab kwan, bowabow kakafin sinafuyah.’
28 “Níbẹ̀ ni ẹkún àti ìpayínkeke yóò wà, nígbà tí ẹ̀yin ó rí Abrahamu, àti Isaaki, àti Jakọbu, àti gbogbo àwọn wòlíì, ní ìjọba Ọlọ́run, tí a ó sì ti ẹ̀yin sóde.
28 Naatu boro narukouwi ufun kwanatit kwanama kwanarerey, wa kwanayob kakikak hiniwa’an, naatu kwananuwanuw boro Abraham, Isaac, Jacob naatu dinab oro’orot God ana aiwobomaim hinabat hinabiyasisir kwana’itih!
29 Wọn ó sì ti ilẹ̀ ìlà-oòrùn, àti ìwọ̀-oòrùn wá, àti láti àríwá, àti gúúsù wá, wọn ó sì jókòó ní ìjọba Ọlọ́run.
29 Sabuw boro veya yeninane, veya ra’iyinane, naatu torene, oyawane etei hinaru’ay God ana aiwobomaim hai efan hinabow hinamare hinama hiyuw hinaa hinabiyasisir boro kwana’itih.
30 Sì wò ó, àwọn ẹni ẹ̀yìn ń bẹ tí yóò di ẹni iwájú, àwọn ẹni iwájú ń bẹ tí yóò di ẹni ẹ̀yìn.”
30 Sabuw iyab boun wan tibi’iyon boro hini’uf, naatu sabuw iyab boun tibi’uf boro wan hini’iyon efan hinab.
31 Ní wákàtí kan náà, díẹ̀ nínú àwọn Farisi tọ̀ ọ́ wá, wọ́n sì wí fún un pé, “Jáde, kí ìwọ sì lọ kúrò níhìn-ín yìí: nítorí Herodu ń fẹ́ pa ọ́.”
31 Nati veya ta’imon, Pharisee afa hina Jesu ana tur hi’owen hio, “O boro efan iti inihamiy inan efan ta, anayabin Herod ekokok o na’asbuni inamorobomih ef enunuwet.”
32 Ó sì wí fún wọn pé, “Ẹ lọ, kí ẹ̀yin sì sọ fún kọ̀lọ̀kọ̀lọ̀ náà pé, ‘Kíyèsi i, èmi ń lé àwọn ẹ̀mí èṣù jáde, èmi ń ṣe ìmúláradá lónìí àti lọ́la, àti ní ọjọ́ mẹ́ta èmi ó ṣe àṣepé.’
32 Jesu iyafutih eo, “Kwan nati haruharu ana tur kwa’owen, ayu boun naatu maras hairi i boro sabuw iyab hisawow tema’am biyahimaim demon boro ana nunih naatu sawusawuwih aniyawasih, naatu veya baitounin i ayu au bowabow abisa bowamih anot anan i yomanin anisawar.
33 Ṣùgbọ́n èmi kò jẹ́ má rìn lónìí, àti lọ́la, àti ní ọ̀túnla: dájúdájú wòlíì kan ki yóò ṣègbé lẹ́yìn odi Jerusalẹmu.
33 Baise boun, maras, naatu mar natot ayu boro au ef anab maiye anayen anan, anayabin ef men ema’am dinab orot boro Jerusalem ufunane namorob.
34 “Jerusalẹmu, Jerusalẹmu, ìwọ tí o pa àwọn wòlíì, tí o sì sọ òkúta lu àwọn tí a rán sí ọ pa; nígbà mélòó ni èmi ń fẹ́ ràgà bo àwọn ọmọ rẹ, bí àgbébọ̀ adìyẹ ti í ràgà bo àwọn ọmọ rẹ̀ lábẹ́ apá rẹ̀, ṣùgbọ́n ẹ̀yin kò fẹ́!
34 O Jerusalem, Jerusalem, dinab oro’orot irouw himorob, naatu kob abarayah God biyafarih kabayamaim irouw himorob. Mar bai’ab a kok a sabuw ataba’afuwih, kokorere natunatun bebenamaim ebaba’afuwih na’atube, baise o men i kok.
35 Sá wò ó, a fi ilé yín sílẹ̀ fún yín ní ahoro. Lóòtítọ́ ni mo sì wí fún yín, ẹ̀yin kì yóò sì rí mi títí yóò fi di àkókò tí ẹ̀yin ó wí pé, ‘Olùbùkún ni ẹni tí ó ń bọ̀ wá ní orúkọ Olúwa.’ ”
35 Imih a bar boro hinihamiy barikokow natuw. A tur ao’owen, ayu boro men kwana’itu, ana veya’amaim boro inao, ‘Yait Regah wabinamaim enan boro baigegewasin nab!’”

Ler em outra tradução

Comparar com outra

Estude este capítulo no WhatsApp

Peça à IA da Bíblia Fala para explicar Lucas 13, comparar traduções ou montar um estudo — tudo direto pelo WhatsApp.