Lucas 12

Biblica® ní oore ọ̀fẹ́ láti lo Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde-Òní (YOR) vs AAI

Sair da comparação
AAI TUR GEWASIN O BAIBASIT BOUBUN
1 Ó sì ṣe, nígbà tí àìníye ìjọ ènìyàn péjọpọ̀, tó bẹ́ẹ̀ tí wọn ń tẹ ara wọn mọ́lẹ̀, ó bẹ̀rẹ̀ sísọ fún àwọn ọmọ-ẹ̀yìn rẹ̀ pé, “Ẹ máa ṣọ́ra yín nítorí ìwúkàrà àwọn Farisi tí í ṣe àgàbàgebè.
1 Nati ana veya’amaim sabuw hiruru’ay ana itinin i sibisib na’atube, naatu sabuw himour kwanekwan efan etei hibai karam hi’a’abinamo hibat. Jesu ana bai’ufununayah iuwih eo, “Pharisee hai yeast isan mata toniwa’an, nati sabuw ufuhine ana itinin i gewasin baise wanawanah i rerekabin, imih a tur ao’owen.
2 Kò sí ohun tí a bò, tí a kì yóò sì fihàn; tàbí tí ó pamọ́, tí a kì yóò mọ̀.
2 Abisa hisabuw inu’in boro sabusabuw hinabosair, naatu abisa wa’iwa’irin inu’in boro nirerereb.
3 Nítorí náà ohunkóhun tí ẹ̀yin sọ ní òkùnkùn, ní gbangba ni a ó ti gbọ́ ọ; àti ohun tí ẹ̀yin bá sọ sí etí ní iyàrá, lórí òrùlé ni a ó ti kéde rẹ̀.
3 Abisa guguminamaim kuo boro natit marakawamaim hinanowar, naatu abisa akisimo bar etawan ihir taituwa taininamaim kubitarasib boro bar faifiy wan hinabat hinao rereb.
4 “Èmi sì wí fún yín ẹ̀yin ọ̀rẹ́ mi, ẹ má ṣe bẹ̀rù àwọn tí ó ń pa ara ènìyàn kú, lẹ́yìn èyí, wọn kò sì ní èyí tí wọ́n lè ṣe mọ́.
4 “Au ofonah a tur ao’owen sabuw iyab biya hina’a’asabun isan men kwanabir, anayabin nati ufunamaim boro men abisa ta hinasinaf.
5 Ṣùgbọ́n èmi ó sì sọ ẹni tí ẹ̀yin ó bẹ̀rù fún yín: Ẹ bẹ̀rù ẹni tí ó lágbára lẹ́yìn tí ó bá pànìyàn tan, láti wọ́ ni lọ sí ọ̀run àpáàdì. Lóòótọ́ ni mo wí fún yín òun ni kí ẹ bẹ̀rù.
5 Orot yait kwana bibiruw i anao kwananowar. God i kwanabiruw, anayabin biya na’a’asabun ufunamaim ana fair ema’am boro baimakiy ana efanamaim nitaiy kwanare. Imih a tur ao’owen God i kwanabiruw.
6 Ológoṣẹ́ márùn-ún sá à ni a ń tà ní owó idẹ wẹ́wẹ́ méjì? A kò sì gbàgbé ọ̀kan nínú wọn níwájú Ọlọ́run?
6 Mamu kwikwik etei five hai biyan i two toea tetotobon, baise God boro men kafa’imo nati mamu kikimin ta isan nuhin eburuburumih.
7 Ṣùgbọ́n gbogbo irun orí yín ni a kà pé ṣánṣán. Nítorí náà kí ẹ má ṣe bẹ̀rù, ẹ̀yin ní iye lórí ju ológoṣẹ́ púpọ̀ lọ.
7 Na’atube ukwarimaim arib eretei bai’ab tebatabat God i so’ob, imih men kwanabir. Kwa a baiyan i ra’at men mamu kwikwik na’atube.
8 “Mo sì wí fún yín pẹ̀lú, Ẹnikẹ́ni tí ó bá jẹ́wọ́ mi níwájú àwọn ènìyàn. Ọmọ Ènìyàn yóò sì jẹ́wọ́ rẹ̀ níwájú àwọn angẹli Ọlọ́run.
8 A tur ao’owen, orot yait ayu isou sabuw etei nahimaim eo’orereb, Orot Natun auman boro God ana tounamatar etei nahimaim nati orot isan naorereb.
9 Ṣùgbọ́n ẹni tí ó bá sẹ́ mi níwájú ènìyàn, a ó sẹ́ ẹ níwájú àwọn angẹli Ọlọ́run.
9 Baise orot yait sabuw etei nahimaim ayu eyayaubu. Orot Natun auman boro na’atube God ana tounamatar etei nahimaim ibo nayaub.
10 Àti ẹnikẹ́ni tí ó bá sọ̀rọ̀-òdì sí Ọmọ Ènìyàn, a ó dárí rẹ̀ jì í; ṣùgbọ́n ẹnikẹ́ni tí ó bá sọ̀rọ̀-òdì sí Ẹ̀mí Mímọ́, a kì yóò dárí rẹ̀ jì í.
10 Yait Orot Natun isan tur nao kakaf na’at boro nanotawiy, baise orot yait Anun Kakafiyin isan tur kakafin nao nabi’ib boro men nanotawiy.
11 “Nígbà tí wọ́n bá sì mú yin wá sí Sinagọgu, àti síwájú àwọn olórí, àti àwọn aláṣẹ, ẹ má ṣe ṣàníyàn pé, báwo tàbí ohun kín ni ẹ̀yin yóò fèsì rẹ̀ tàbí kín ni ẹ̀yin ó wí.
11 Baibabatiyi isan hinabuwi kwanan Kou’ay Baremaim, o gawan sabuw nahimaim, o aiwob sabuw nahimaim, men taiyuw wasfafari isan, o tur mi’itube eo isan kwaniyababanamih.
12 Nítorí Ẹ̀mí Mímọ́ yóò kọ́ yín ní wákàtí kan náà ní ohun tí ó yẹ kí ẹ sọ.”
12 Anayabin God Anun Kakafiyin nati ana veya’amaim boro tur ni’obaiyi kwanao.”
13 Ọ̀kan nínú àwùjọ wí fún un pé, “Olùkọ́, sọ fún arákùnrin mi kí ó pín mi ní ogún.”
13 Rou’ay wanawanahimaim orot ta Jesu iu, “Bai’obaiyenayan, ayu akokok tuwai ana tur ina’owen, tamai momorob ana kwahan nafaram airi ana bow.”
14 Ó sì wí fún un pé, “Ọkùnrin yìí, ta ni ó fi mí jẹ onídàájọ́ tàbí olùpíngún fún yín?”
14 Jesu iya’afut eo, “Aro, ayu au ef men ema’am boro anibasit tuwat airi a sawar kwahan ana faram?”
15 Ó sì wí fún wọn pé, “Kíyèsára kí o sì máa ṣọ́ra nítorí ojúkòkòrò: nítorí ìgbésí ayé ènìyàn kò dúró lé ọ̀pọ̀ ohun tí ó ní.”
15 Naatu Jesu tatabir sabuw etei iuwih eo, “Mata toniwa’an sawar moumurih na’in bow isan men mata nananan niwa’an. Anayabin yawas wanatowan boro men orot ana sawar moumurih imaim hinafufun hinitinimih.”
16 Ó sì pa òwe kan fún wọn pé, “Ilẹ̀ ọkùnrin ọlọ́rọ̀ so ọ̀pọ̀lọpọ̀ èso.
16 Naatu Jesu oroubon ta eo, “Ana veya ta orot sawar wairafin ana masaw bo ana ub hiyen gewas hiw ro’oh moumurih na’in hiya itah,
17 Ó sì rò nínú ara rẹ̀ pé, ‘Èmi ó ti ṣe, nítorí tí èmi kò ní ibi tí èmi ó gbé kó èso mi jọ sí.’
17 basit mare ma not. ‘Ayu boro mi’itube ana sinaf? Anayabin iti bay hinafafour efan i boro en.’
18 “Ó sì wí pé, ‘Èyí ni èmi ó ṣe: èmi ó wó àká mi palẹ̀, èmi ó sì kọ́ èyí tí ó tóbi; níbẹ̀ ni èmi ó gbé to gbogbo èso àti ọrọ̀ mi jọ sí.
18 Naatu ana notamaim eo, ‘Ayu boro iti na’atube ana sinaf, bay hai bar atamanih ana ku’uben hinare naatu gagamih ana wowab. Saise au bay ana ya naatu au sawar afa auman imaim ana ya.’
19 Èmi ó sì wí fún ọkàn mi pé, ọkàn, ìwọ ní ọrọ̀ púpọ̀ tí a tò jọ fún ọ̀pọ̀ ọdún; sinmi, máa jẹ, máa mu, máa yọ̀.’
19 Imaibo anao, ‘Darik orot, anababatun abow, kwamur manin na’in ana fofonin sawar etei abogaigiwas sawar, imih bounabo hamen ana mare anama gewas, anaa anatom taiyuwu aniyasisir!’
20 “Ṣùgbọ́n Ọlọ́run wí fún un pé, ‘Ìwọ aṣiwèrè, lóru yìí ni a ó béèrè ọkàn rẹ lọ́wọ́ rẹ; ǹjẹ́ ti ta ni nǹkan wọ̀nyí yóò ha ṣe, tí ìwọ ti pèsè sílẹ̀?’
20 Baise God iu, ‘Kwikwekwe’aw gewas! Boun gugumin boro inamorob naatu a sawar iti ibobogaigiwas boro yait nabow?’”
21 “Bẹ́ẹ̀ ni ẹni tí ó to ìṣúra jọ fún ara rẹ̀, tí kò sì ní ọrọ̀ lọ́dọ̀ Ọlọ́run.”
21 Naatu Jesu ana tur yomaninamaim eo, “Imih itinin i ta’imon, sabuw iyab aurih sawar karam hiya tetototo God matanamaim i men sawar wairafih.”
22 Jesu sì wí fún àwọn ọmọ-ẹ̀yìn rẹ̀ pé, “Nítorí náà mo wí fún yín pé, ẹ má ṣe ṣe àníyàn nítorí ẹ̀mí yín pé, kín ni ẹ̀yin yóò jẹ tàbí nípa ara yin pe kín ni ẹyin o fi bora.
22 Imaibo Jesu ana bai’ufununayah iuwih eo, “A yawas isan a tur ao’owen men kwaniyababan kwanao, ‘bay boro menamaim anab ana’aan,’ o biya isan kwanao, faifuw boro menamaim anab ana’us.
23 Ẹ̀mí sá à ju oúnjẹ lọ, ara sì ju aṣọ lọ.
23 Anayabin it etei taso’ob yawas i sawar gagamin men bay na’atube naatu biyat i sawar gagamin men ar faifuw na’atube.
24 Ẹ kíyèsi àwọn ẹyẹ ìwò: wọn kì í fúnrúgbìn, bẹ́ẹ̀ ni wọn kì í kórè: wọn kò ní àká, bẹ́ẹ̀ ni wọn kò ní abà, Ọlọ́run sá à ń bọ́ wọn: mélòó mélòó ni tí ẹ̀yin fi sàn ju ẹyẹ lọ!
24 Baise kwanuw mamu awaw kwana’itih, i men me hikwair hitar, masaw hibo, naatu hifour hitab te’aa’umih en, na’atube men bay hai bar hiwowab imaim bay teya’aya’amih en, baise God akisin ebituwih! Imih kwa i God ana sawar gagamin men mamu na’atube!
25 Ta ni nínú yín nípa àníyàn ṣíṣe tí ó lè fi ìgbọ̀nwọ́ kan kún ọjọ́ ayé rẹ̀?
25 Isan imih iti sawar isah kwana biyababan ana gewasin i boro abisa namatar? Kwanotanot nati kwana biyababanamaim boro kwamur tabo ayawas tafan hina yara’ah namanin kwanama? Men karam.
26 Ǹjẹ́ bí ẹ̀yin kò ti lè ṣe èyí tí ó kéré bí eléyìí, èéṣe tí ẹ̀yin fi ń ṣàníyàn nítorí ìyókù?
26 A yababan iti sawar gidigidih isah kwabiyababan men emamatar, aisim sawar gagamih isah kwabiyababan?
27 “Ẹ kíyèsi àwọn lílì bí wọ́n ti ń dàgbà; wọn kì í ṣiṣẹ́, wọn kì í rànwú; ṣùgbọ́n kí èmi wí fún yín, a kò ṣe Solomoni pàápàá lọ́ṣọ̀ọ́ ní gbogbo ògo rẹ̀ tó ọ̀kan nínú ìwọ̀nyí.
27 “Kwanuw rarab bogay ebatabat kwa’itin, men masaw hitar tebob, o ar faifuw tesasakir en, baise a tur ao’owen aiwob orot Solomon ana bar bonamanamarinamaim ma’am ana veya ana faifuw eo’osen hai gewasih i men iti beran ana gewasin na’atube’emih en.
28 Ǹjẹ́ bí Ọlọ́run bá wọ koríko igbó ní aṣọ tó bẹ́ẹ̀ èyí tí ó wà lónìí, tí a sì gbá a sínú iná lọ́la: mélòó mélòó ni yóò wọ̀ yín láṣọ, ẹ̀yin onígbàgbọ́ kékeré.
28 Imih kwana’itin, God ar faifuw kutor fotan ius ana itinin gewasin maiyow boun ina’itin baise maras boro nakimow naha’obow nare hinab hinan wairaf wan hina yara’ah na’arah ni’en. Baise kwa i God ana sawar gagamin fai mar etei boro nakaifi ar faifuw nit kwana’osen, aisim a not ebikikimin!
29 Kí ẹ má sì ṣe lé ohun tí ẹ ó jẹ, tàbí ohun tí ẹ ó mu, kí ẹ má sì ṣe ṣe àníyàn nínú ọkàn.
29 Imih men mar etei aa tom isan kwananot kwaniyababanamih.
30 Nítorí gbogbo nǹkan wọ̀nyí ni àwọn orílẹ̀-èdè ayé ń wá kiri. Baba yín sì mọ̀ pé, ẹ̀yin ń fẹ́ nǹkan wọ̀nyí.
30 Anayabin Eteni Sabuw iti tafaram wanawanan tutufin etei iti sawar isah hinuwet tibiyababan, naatu kwa Tamat iti sawar etei isah kwakok kwabiyababan i so’ob.
31 Ṣùgbọ́n ẹ máa wá ìjọba Ọlọ́run, gbogbo nǹkan wọ̀nyí ni a ó sì fi kún un fún yín.
31 Baise wan i God ana aiwob kwananuwih kwanab dogoromaim nama, imaibo iti sawar isah kwanot kwabiyababan boro etei nit.
32 “Má bẹ̀rù, agbo kékeré, nítorí dídùn inú Baba yín ni láti fi ìjọba fún yín.
32 Kwa i ayu au bobaituw na’atube imih men kwanabir, anayabin Tamat aiwob bait isan i ebiyasisir boro nit.
33 Ẹ ta ohun tí ẹ̀yin ní, kí ẹ sì tọrẹ àánú kí ẹ sì pèsè àpò fún ara yín, tí kì í gbó, ìṣúra ní ọ̀run tí kì í tán, ní ibi tí olè kò lè súnmọ́, àti ibi tí kòkòrò kì í bà á jẹ́.
33 Imih a sawar eretei sabuw kabay wairafih ku’uwih tetobon naatu o kabay kubai yababan wairafih kufaramih, saise a kaukut no maramaim inabaib boro men natakweb; a sawar etei maramaim inaya’ay boro men ta nakasiy, o boro men ta bainowan hinabain naatu boro men ta ganidor hina’aanimih en anababatun.
34 Nítorí ní ibi tí ìṣúra yín gbé wà, níbẹ̀ ni ọkàn yín yóò gbé wà pẹ̀lú.
34 Anayabin o sawar menamaim kuya’aya a not tutufin etei boro imaim na’in.
35 “Ẹ di àmùrè yín, kí fìtílà yín sì máa jó.
35 “Mar etei inabobuna a ar uwakamukamut inarab, a ramef inito’ab namarakaw o mata nuwinuwin inama, anayabin o men iso’ob boro abisa namatar.
36 Kí ẹ̀yin tìkára yín dàbí ẹni tí ń retí olúwa wọn, nígbà tí òun ó padà ti ibi ìgbéyàwó dé, pé nígbà tí ó bá dé, tí ó sì kànkùn, kí wọn lè ṣí i sílẹ̀ fún un lọ́gán.
36 Ana’itin akir wairafih hai orot ukwarin tabin ana hiyuwane matabir maiye nan isan hima hikakaif, hai orot ukwarin matabir na etawan rurukikitar ana veya mar ta’imon hinowar naatu etawan hibotawiy rur na’atube.
37 Ìbùkún ni fún àwọn ọmọ ọ̀dọ̀ náà nígbà tí olúwa náà bá dé tí yóò bá wọn tí wọn ń ṣọ́nà; lóòótọ́ ni mo wí fún yín, yóò di ara rẹ̀ ní àmùrè yóò sì mú wọn jókòó láti jẹun, yóò sì jáde wá láti ṣe ìránṣẹ́ fún wọn.
37 Anababatun a tur ao’owen, akir wairafih iyab matah nuwinuwin hinama’am hai orot ukwarin namatabir nan na’i’itih ana veya, yasisir boro gagamin maiyow hinab! Anayabin i boro ana akir wairafih na’uwih hinamare naatu orot ukwarin boro bay semosemor ana faifuw na’us bay nasemor nitih hinama hinaa.
38 Bí olúwa wọn bá sì dé nígbà ìṣọ́ kejì, tàbí tí ó sì dé nígbà ìṣọ́ kẹta, tí ó sì bá wọn bẹ́ẹ̀, ìbùkún ni fún àwọn ọmọ ọ̀dọ̀ náà.
38 Akirwairafih hina bobuna matah nuwinuwin hina ma’am hai orot ukwarin nan natit, o mar natot auman nan natit na’i’itih na’at, boro yasisir gagamin maiyow hinab!
39 Ṣùgbọ́n ẹ mọ èyí pé, baálé ilé ìbá mọ wákàtí tí olè yóò wá, òun ìbá máa ṣọ́nà, kì bá tí jẹ́ kí a já wọ inú ilé òun.
39 Imih iti tur ao i naniyan kwanab naatu kwananot, orot bar matuwan bainowan mowan bainuwinamih enan ana veya nasoso’ob na’at, ana bar boro men nihamiy bainowan mowan nakwib narun nabainuwimih en.
40 Nítorí náà, kí ẹ̀yin múra pẹ̀lú, nítorí Ọmọ Ènìyàn ń bọ̀ ní wákàtí tí ẹ̀yin kò nírètí.”
40 Imih itinin ta’imon i nati, kwa auman kwana bogewas mata nuwinuwin kwanama, anayabin Orot Natun boro men veya kwa kwanotanotamaim natitamih.”
41 Peteru sì wí pé, “Olúwa, ìwọ pa òwe yìí fún wa, tàbí fún gbogbo ènìyàn?”
41 Peter eo, “Regah, iti oroubon kuo i aki isai, o sabuw eretei isah kuo?”
42 Olúwa sì dáhùn wí pé, “Ta ni olóòtítọ́ àti ọlọ́gbọ́n ìríjú náà, tí olúwa rẹ̀ fi jẹ olórí agbo ilé rẹ̀, láti máa fi ìwọ̀n oúnjẹ wọ́n fún wọn ní àkókò?
42 Regah iya’afut eo, “Anababatun a tur ao’owen Akir wairafin orot gewasin naatu ana not rerekabin, orot ukwarin nati akir wairafin boro nab akir wairafih afa isah ni’ukwarin naatu hai bay baitih isan boro ana veya’amaim nitih hinaa.
43 Ìbùkún ni fún ọmọ ọ̀dọ̀ náà, nígbà tí olúwa rẹ̀ bá dé, tí yóò bá a kí ó máa ṣe bẹ́ẹ̀.
43 Anayabin orot ukwarin matabir nan nati akir wairafin bowabow gewasin maiyow bowabow itin, imih iyasisir ana akir wairafin bai yara’ah bowabow gagamin na’in itin!
44 Lóòótọ́ ni mo wí fún yín yóò fi jẹ olórí ohun gbogbo tí ó ní.
44 Ana bar wanawanan sawar tutufin etei i akisin i’ukwarin kaif.
45 Ṣùgbọ́n bí ọmọ ọ̀dọ̀ náà bá wí ní ọkàn rẹ̀, pé, ‘Olúwa mi fi ìgbà bíbọ̀ rẹ̀ falẹ̀!’ Tí ó sì bẹ̀rẹ̀ sí í lu àwọn ìránṣẹ́kùnrin àti ìránṣẹ́bìnrin tí ó sì bẹ̀rẹ̀ sí í jẹ àti sí mu àmupara:
45 Baise akir wairafin na’at nao, ‘Orot ukwarin bisaise enan, no’om boro ma hamen hamen erurubirabir, imih ayu boro au kokomaim anasinaf.’ Naatu namisir bowabow sabuw, oro’orot baibin nabow narouw kwanekwan ni’a’afiyih, naatu ana kokomaim naa natom kwanekwan nikoko’aw nanan ana veya.
46 Olúwa ọmọ ọ̀dọ̀ náà yóò dé ní ọjọ́ tí kò retí rẹ̀, àti ní wákàtí tí kò dábàá, yóò sì jẹ ẹ́ ní yà gidigidi, yóò sì yan ipò rẹ̀ pẹ̀lú àwọn aláìgbàgbọ́.
46 Imaibo Orot ukwarin boro nan natit, veya men nati akir wairafin so’ob ma ekakaifimaim boro nanamih, naatu na isan ana veya boro baimatnuwina’e nama’am nan natit. Naatu orot ukwarin nan natitit ana veya nati akir wairafin boro nab nabeyah natarsisib nisaroun baifanasairayah hai efanamaim bairi hinama.”
47 “Àti ọmọ ọ̀dọ̀ náà, tí ó mọ ìfẹ́ olúwa rẹ̀, tí kò sì múra sílẹ̀, tí kò sì ṣe gẹ́gẹ́ bí ìfẹ́ rẹ̀, òun ni a ó nà púpọ̀.
47 “Akir wairafin ana orot ukwarin abisa sinafumih kokok i so’ob baise men saife taiyuwin yabuna ana orot ukwarin abisa kok eo’omaim sisinaf, nati orot boro hinawabir biyababan gagamin na’in nab.
48 Ṣùgbọ́n èyí tí kò mọ̀, tí ó ṣe ohun tí ó yẹ sí lílù, òun ni a ó lù níwọ̀n. Nítorí ẹnikẹ́ni tí a fún ní púpọ̀, lọ́dọ̀ rẹ̀ ni a ó gbé béèrè púpọ̀: lọ́dọ̀ ẹni tí a bá gbé fi púpọ̀ sí, lọ́dọ̀ rẹ ni a ó gbé béèrè sí i.
48 Baise akir wairafin ana orot ukwarin abisa sinafumih kokok i men so’ob, naatu isisinaf kwanekwan biyababan enunuwih boro au hamenamo hinawabir biyan nababan. Sabuw iyab sawar gagamin na’in tebaib, i na’atube sawar gagamin na’in boro wan hinay maiye. Orot yait gagamin anababatun tibitin i auman boro gagamin anababatun isan hinafefeyan nitih maiye.
49 “Iná ni èmi wá láti sọ sí ayé; kín ni èmi sì ń fẹ́ bí kò ṣe kí iná náà ti jo!
49 “Ayu i wairaf abai iti tafaram afuninamih ana atit, au kok gagamin na’in i mi’itube iti tafaram marasika tabusuruf ta’arah.
50 Ṣùgbọ́n èmi ní bamitiisi kan tí a ó fi bamitiisi mi; ara ti ń ni mí tó títí yóò fi parí!
50 Ayu i bapataito fokarin maiyow nou’umaim ema’am boro wanawanan ana run anab, imih boun dogorou wanawanan i yababan awan karatan ama anotanot anan yomanin anisawar imaibo nuhunafot!
51 Ẹ̀yin ṣe bí àlàáfíà ni èmi fi sí ayé? Mo wí fún yín, bẹ́ẹ̀ kọ́; ṣùgbọ́n bí kò ṣe ìyapa.
51 Kwa kwanotanot ayu i tufuw abai tafaramamaim ana? En, a tur ao’owen, ayu i men tufuw abai anamih, baise kauseb abai ana.
52 Nítorí láti ìsinsin yìí lọ, ènìyàn márùn-ún yóò wà ní ilé kan náà tí a ó yà ní ipa, mẹ́ta sí méjì, àti méjì sí mẹ́ta.
52 Mar iti boun orot aawan natunatunawat nah etei five boro hinakusib tounu rounane hinabat rou’ab rounane hinabat taiyuwih hinakusib hinigamigam.
53 A ó ya baba nípa sí ọmọ rẹ̀ ọkùnrin, àti ọmọ ọkùnrin sí baba; ìyá sí ọmọbìnrin, àti ọmọbìnrin sí ìyá rẹ̀, ìyá ọkọ sí ìyàwó ọmọ, àti ìyàwó ọmọ sí ìyá ọkọ rẹ̀.”
53 Kek tamah hairi boro taiyuwih hinakusib hinagam. Babitai hinah hairi boro hinakusib hinagam na’atube babine rawan babin hairi boro hinakusib hinagam.”
54 Ó sì wí fún ìjọ ènìyàn pẹ̀lú pé, “Nígbà tí ẹ̀yin bá rí àwọsánmọ̀ tí ó ṣú ní ìhà ìwọ̀-oòrùn, lọ́gán ni ẹ̀yin yóò sọ pé, ‘Ọ̀wààrà òjò ń bọ̀,’ a sì rí bẹ́ẹ̀.
54 Jesu sabuw isah iban eo maiye, “Veya ra’iyinane sakuk nayen nabi’afar badowan kwana’i’itin ana maramaim, kwa boro mar ta’imon kwanao, ‘boun boro toun nayar’, naatu toun eyarayar.
55 Nígbà tí afẹ́fẹ́ gúúsù bá ń fẹ́, ẹ̀yin á ní, ‘Oòrùn yóò mú,’ yóò sì ṣe bẹ́ẹ̀.
55 Naatu gurufune gagub nayen narab kwananowar kwa boro kwanao, Veya boro nararan, naatu veya erararan.
56 Ẹ̀yin àgàbàgebè! Ẹ̀yin le mòye ojú ọ̀run àti ti ayé. Èéha ti ṣe tí ẹ̀yin kò mọ àkókò yìí?
56 Wanawanan rerekabih! Me kamar hai sawar naatu gagub wanawanan hai sawar abisa temamatar i kwa’itah kwa’inanen kwaso’ob kwa’o. Baise aisim sawar abisa iti boun temamatar hai yabih men kwaso’ob?
57 “Èéha ti ṣe tí ẹ̀yin tìkára yín kò fi ro ohun tí ó tọ́?
57 Aisim sawar abisa gewasin sinaf isan men taiyuw kwabibabatiyi?
58 Nígbà tí ìwọ bá bá ọ̀tá rẹ lọ sọ́dọ̀ onídàájọ́, rí i pé o bá a parí ọ̀rọ̀ ní ọ̀nà kí ó má ba à fà ọ́ fún adájọ́, adájọ́ a fi ọ́ lé ẹ̀ṣọ́ lọ́wọ́, òun a sì tì ọ́ sínú túbú.
58 Sabuw baibatiyih isan hinabuwi kwanan inasinaftobon airi kwanayabuna kwanitounuw, imaibo kwananan baibatiyenamaim kwanatit. Baise o men inasisinaf na’at, i boro nabuw narab natain kwekwetar kwanan baibabatiyenayan orot nanamaim kwanatit naatu i boro nabuw furisiman nitih hinabuwi dibur hina yariyi.
59 Kí èmi wí fún ọ, ìwọ kì yóò jáde kúrò níbẹ̀, títí ìwọ ó fi san ẹyọ owó kan tí ó kù!”
59 A tur ao’owen, o boro dibur bar imaim inama agim hio na’atube inibaiyan imaibo boro dibur barene hinabotaiti inatit.”

Ler em outra tradução

Comparar com outra

Estude este capítulo no WhatsApp

Peça à IA da Bíblia Fala para explicar Lucas 12, comparar traduções ou montar um estudo — tudo direto pelo WhatsApp.