Lucas 11
Biblica® ní oore ọ̀fẹ́ láti lo Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde-Òní (YOR) vs AAI
1 Bí ó ti ń gbàdúrà ní ibi kan, bí ó ti dákẹ́, ọ̀kan nínú àwọn ọmọ-ẹ̀yìn rẹ̀ wí fún un pé, “Olúwa, kọ́ wa bí a ti ń gbàdúrà, bí Johanu ti kọ́ àwọn ọmọ-ẹ̀yìn rẹ̀.”
1 Veya ta Jesu efan ta’amaim ma yoyoban inan, ana yoyoban sasawar ufunamaim ana bai’ufununayah orot ta natit eo, “Regah, kwi’obaiyi ana yoyoban, John ana bai’ufununayah bi’obaiyih na’atube.”
2 Ó sì wí fún wọn pé, “Nígbà tí ẹ̀yin bá ń gbàdúrà, ẹ máa wí pé:
2 Jesu iuwih eo, “Yoyobanamih iti na’atube kwanayoyoban.
3 Fún wa ní oúnjẹ òòjọ́ wa lójoojúmọ́.
3 Mar etei ana fofonin ai bay initi.
4 Kí o sì dárí ẹ̀ṣẹ̀ wa jì wá;
4 Ai bowabow kakafih kunotawiyen,
5 Ó sì wí fún wọn pé, “Ta ni nínú yín tí yóò ní ọ̀rẹ́ kan, tí yóò sì tọ̀ ọ́ lọ láàrín ọ̀gànjọ́, tí yóò sì wí fún un pé, ‘Ọ̀rẹ́, yá mi ní ìṣù àkàrà mẹ́ta.
5 Imaibo Jesu ana bai’ufununayah iuwih eo, “O yait a of auman boro fainaiwan itan itafefeyan itao, “Au of akokok rafiy fafar tounu inibaisu,
6 Nítorí ọ̀rẹ́ mi kan ti àjò dé sọ́dọ̀ mi, èmi kò sì ní nǹkan tí èmi ó gbé kalẹ̀ níwájú rẹ̀.’
6 anayabin ayu au of ta bai’esegamih inan na au bar tit naatu ayu auru bay en, imih o isa abifefeyan inibaisu.’
7 Tí òun ó sì gbé inú ilé dáhùn wí fún un pé, ‘Má yọ mí lẹ́nu, a ti sé ìlẹ̀kùn, àwọn ọmọ mi si ń bẹ lórí ẹní pẹ̀lú mi: èmi kò lè dìde fi fún ọ!’
7 Naatu a of bar wanawanan boro na’afatit nao, ‘Men akokok au in ini’afiy, etawan i atufatan, naatu ayu natunatu bairi i a’inu’in, imih men karam boro ana misir bay anit.’
8 Mo wí fún yín, bí òun kò tilẹ̀ ti fẹ́ dìde kí ó fi fún un nítorí tí í ṣe ọ̀rẹ́ rẹ̀, ṣùgbọ́n nítorí àwíìyánnu rẹ̀, yóò dìde, yóò sì fún un tó bí ó ti ń fẹ́.
8 Naatu kwanotanot nati orot boro namisir ana of bay nitin? Ai, boro namisir ana of bay nitin, baise a tur ao’owen orot namisir ana of bay nabitin i men i ana of imih bay ebitin, baise anayabin, nati orot i ana fefeyanamaim ana of ihahar imih misir bay itin.
9 “Èmí sì wí fún yín, ẹ béèrè, a ó sì fi fún un yín; ẹ wá kiri, ẹ̀yin ó sì rí; ẹ kànkùn, a ó sì ṣí i sílẹ̀ fún yín.
9 Imih a tur ao’owen. Inafefeyan boro inab, inanuwet boro inatitau’ur, inarukikitar etawan boro nabotawiy.
10 Nítorí ẹnikẹ́ni tí ó bá béèrè, ó rí gbà; ẹni tí ó sì ń wá kiri, ó rí; àti ẹni tí ó kànkùn ni a ó ṣí i sílẹ̀ fún.
10 Anayabin Orot yait efefeyan boro nab, orot yait enunuwet boro natita’ur; naatu orot yait erurukikitar etawan boro nabotawiy.
11 “Ta ni baba nínú yín tí ọmọ rẹ̀ yóò béèrè àkàrà lọ́dọ̀ rẹ̀, tí yóò fún un ní òkúta? Tàbí bí ó béèrè ẹja, tí yóò fún un ní ejò?
11 Kwa kek tamahinah natunat siyamih hitarererey na’at boro siy efanin kok kwatitih hita’an?
12 Tàbí bí ó sì béèrè ẹ̀yin, tí yóò fún un ní àkéekèe?
12 O mamu foufunamih hitarererey na’at boro kafukafus kwatitih hita’an?
13 Ǹjẹ́ bí ẹ̀yin tí ó jẹ́ ènìyàn búburú bá mọ bí a ti í fi ẹ̀bùn dáradára fún àwọn ọmọ yín, mélòó mélòó ha ni Baba yín tí ń bẹ ní ọ̀run yóò fi Ẹ̀mí Mímọ́ rẹ̀ fún àwọn tí ó béèrè lọ́dọ̀ rẹ̀!”
13 Kwa kek tamahinah, kwa i sawar kakafih moumurih maiyow kwasisinaf, baise natunat isah boro men nuhi naburumih, abisa isan hikokok tibiyababan boro kwanab kwanan kwanitih. Imih kwanaso’ob, Tamat maramaim baitinin isan i igewasin kwanekwan, imih sabuw iyab Anun Kakafiyin isan tefefefeyan boro nitih!”
14 Ó sì ń lé ẹ̀mí èṣù kan jáde, tí ó sì yadi. Nígbà tí ẹ̀mí èṣù náà jáde, odi sọ̀rọ̀; ẹnu sì ya ìjọ ènìyàn.
14 Jesu demon awan bey nun tit; naatu demon bihir tit orot bihamiy ana veya’amaim orot busuruf tur eo, sabuw hai tur sawar hifofofor men kafaita.
15 Ṣùgbọ́n àwọn ẹlòmíràn nínú wọn wí pé, “Nípa Beelsebulu olórí àwọn ẹ̀mí èṣù ni ó fi ń lé àwọn ẹ̀mí èṣù jáde.”
15 Baise sabuw afa hio, “Nati i demon hai ukwarin wabin Beelzebul ana fair itin imih enununih.”
16 Àwọn ẹlòmíràn sì ń dán an wò, wọ́n ń fẹ́ àmì lọ́dọ̀ rẹ̀ láti ọ̀run wá.
16 Naatu sabuw afa hikok i marane ina’inan ta tiwa’an hita’itin, imih hikubibiruw.
17 Ṣùgbọ́n òun mọ èrò inú wọn, ó wí fún wọn pé, “Gbogbo ìjọba tí ó ya ara rẹ̀ ní ipá, ni a ń sọ di ahoro; ilé tí ó sì ya ara rẹ̀ nípá yóò wó.
17 Baise abisa hinotanot Jesu so’ob naatu iuwih, “Tafaram ta’imon hinakusib rou’ab namatar hinabiyow, hai fair boro hina gurus, na’atube orot aawan natunatun aawat bairi hinakusib hinabiyow boro hinama kakaf.
18 Bí Satani ba yapa sí ara rẹ̀, ìjọba rẹ̀ yóò ha ṣe dúró? Nítorí ẹ̀yin wí pé, nípa Beelsebulu ni èmi fi ń lé àwọn ẹ̀mí èṣù jáde.
18 Imih Satan an aiwob wanawananamaim hina kusisib hinabiyow, ana aiwob boro mi’itube fair nab nabat? Ayu iti tur ao anayabin i kwa a turamaim, ayu Beelzebul hai ukwarin fair baitu demon nunih kwarouw kwa’o.
19 Bí ó ba ṣe pé nípa Beelsebulu ni èmi fi ń lé àwọn ẹ̀mí èṣù jáde, nípa ta ni àwọn ọmọ yín fi ń lé wọn jáde, nítorí náà àwọn ni yóò ṣe onídàájọ́ yín.
19 Baise ayu Beelzebul ana fairamaim demon ana nununih na’at, bo kwa a bai’ufununayah fair yait itih demon tinununih? Imih kwa taiyuw a bai’ufununayah iti kwa’o isan hinabi’obaiyi kwa a tur i men turobe!
20 Ṣùgbọ́n bí ó bá ṣe pé nípa ìka ọwọ́ Ọlọ́run ni èmi fi ń lé àwọn ẹ̀mí èṣù jáde, ǹjẹ́ ìjọba Ọlọ́run dé bá yín tán.
20 Baise ayu God ana fairamaim demon ana nunih hinatitit na’at, nati ebi’obaiyi God ana aiwob i natitaka.
21 “Nígbà tí alágbára ọkùnrin tí ó ni ìhámọ́ra bá ń ṣọ́ ààfin rẹ̀, ẹrù rẹ̀ yóò wà ní àlàáfíà.
21 Orot fairin aurin ahay waf karam ma ana bar ekakaif, ana sawar etei boro natafafar hina’in.
22 Ṣùgbọ́n nígbà tí ẹni tí ó ní agbára jù ú bá kọlù ú, tí ó sì ṣẹ́gun rẹ̀ a gba gbogbo ìhámọ́ra rẹ̀ tí ó gbẹ́kẹ̀lé lọ́wọ́ rẹ̀, a sì pín ìkógun rẹ̀.
22 Baise orot fairin anababatun nati orot boro nawasfufur narun ana ahay ana waf tafahimaim ema’am boro niteten nan ana ofonah nafaramih bairi hinabow.
23 “Ẹni tí kò bá wà pẹ̀lú mi, ó lòdì sí mi, ẹni tí kò bá sì bá mi kójọpọ̀, ó fọ́nká.
23 Orot yait ayu ananamaim men enan, i ayu isou ebiwosai, naatu orot yait men ibaisu airi sabuw abita’ay, i was geyayan.
24 “Nígbà tí ẹ̀mí àìmọ́ bá jáde kúrò lára ènìyàn, a máa rìn kiri ní ibi gbígbẹ, a máa wá ibi ìsinmi; nígbà tí kò bá sì rí, a wí pé, ‘Èmi yóò padà lọ sí ilé mi ní ibi tí mo gbé ti jáde wá.’
24 Demon kakafin orot biyanamaim titit ana veya i efan gewasin ta imaim ma baiyarir isan nuwet in, baise nuwet inan efan men ta tita’ur, naatu eo, “Ayu i boro ana matabir maiye au bar abihamiy ana’itin.”
25 Nígbà tí ó bá sì dé, tí ó sì rí tí a gbá a, tí a sì ṣe é ní ọ̀ṣọ́.
25 Basit matabir maiye na ana bar titit, hirereb hina yabuna inu’in itin.
26 Nígbà náà ni yóò lọ, yóò sì mú ẹ̀mí méje mìíràn tí ó burú ju òun tìkára rẹ̀ lọ wá, wọn yóò wọlé, wọn yóò sì máa gbé níbẹ̀, ìgbẹ̀yìn ọkùnrin náà yóò sì burú ju ìṣáájú rẹ̀ lọ.”
26 Naatu tit in demon kakafih anababatun etei seven nawiyih bairi hina nati’imaim hisusuw hima. Yomaninamaim orot ana itinin botabir kakafin anababatun matar men marasika ma’am na’atube.”
27 Bí ó ti ń sọ nǹkan wọ̀nyí, obìnrin kan gbóhùn rẹ̀ sókè nínú ìjọ, ó sì wí fún un pé, “Ìbùkún ni fún inú tí ó bí ọ, àti ọmú tí ìwọ mu!”
27 Jesu iti na’atube bat binan sabuw hai tur eo’owen auman, babin ta sabuw wanawanahimaim ma’am, Jesu isan eo, “Babin yait taub o ya’i bitoman i ebiyasisir.”
28 Ṣùgbọ́n òun wí pé, nítòótọ́, kí ó kúkú wí pé, “Ìbùkún ni fún àwọn tí ń gbọ́ ọ̀rọ̀ Ọlọ́run, tí wọ́n sì pa á mọ́!”
28 Baise Jesu eo, “Sabuw iyab God ana tur hinowar tibi’ufunun i turobe anababatun tibiyasisir.”
29 Nígbà tí ìjọ ènìyàn sì ṣùjọ sí ọ̀dọ̀ rẹ̀, ó bẹ̀rẹ̀ sí wí pé, “Ìran búburú ni èyí, wọ́n ń wá àmì; a kì yóò sì fi àmì kan fún un bí kò ṣe àmì Jona wòlíì!
29 Sabuw moumurih maiyow hiru’ay Jesu hi’ar bebera’uh, naatu Jesu iuwih eo, “Boun ana veya’amaim sabuw hai yawas etei i eaf, ina’inan matar itah isan tefefefeyan, baise ina’inan ta boro men anitih, ina’inan ta’imon i Jonah isan mamatar i hiso’obaka.
30 Nítorí bí Jona ti jẹ́ àmì fún àwọn ará Ninefe, gẹ́gẹ́ bẹ́ẹ̀ ni Ọmọ Ènìyàn yóò ṣe jẹ́ àmì fún ìran yìí.
30 Anayabin Jonah biyanamaim ina’inan mamatar i Nineveh sabuw isah. Imih Orot Natun i sabuw iti boun tema’am hai i’inanen.
31 Ọbabìnrin gúúsù yóò dìde ní ọjọ́ ìdájọ́ pẹ̀lú àwọn ènìyàn ìran yìí, yóò sì dá wọn lẹ́bi: nítorí tí ó ti ìhà ìpẹ̀kun ayé wá láti gbọ́ ọgbọ́n Solomoni: sì kíyèsi i, ẹni tí ó pọ̀jù Solomoni lọ ń bẹ níhìn-ín yìí.
31 Baibatebat ana veya tafaram Sheba hai aiwob babin boro namisir. Sabuw iti boun tema’ama boro tur fokarin maiyow na’uwih, anayabin ef yok na’in tafaram yomaninaka aiwob orot Solomon ana binan gewasin nowaramih natit, baise a tur ao’owen, sawar ta iti boun kwa’i’itin i Solomon natabir.
32 Àwọn ará Ninefe yóò dìde ní ọjọ́ ìdájọ́ pẹ̀lú ìran yìí, wọn ó sì dá a lẹ́bi: nítorí tí wọn ronúpìwàdà nípa ìwàásù Jona; sì kíyèsi i, ẹni tí ó pọ̀jù Jona lọ ń bẹ níhìn-ín yìí.
32 Naatu a tur ao’owen maiye, Baibatebat ana veya Nineveh sabuw boro hinamisir kwa iti kwama’am boro tur fokarin maiyow hina’uwi, anayabin Jonah binan hinonowar ufunamaim hai bowabow kakafih etei hihamiyen dogor baikitabir hibai, naatu boun i a tur ao’owen, orot ta Jonah tafanamaim i natit iti wanawanamaim ema’am.
33 “Kò sí ẹnìkan, nígbà tí ó bá tan fìtílà tan, tí gbé e sí ìkọ̀kọ̀, tàbí sábẹ́ òsùwọ̀n, bí kò ṣe sórí ọ̀pá fìtílà, kí àwọn tí ń wọlé ba à lè máa rí ìmọ́lẹ̀.
33 Orot men ta ramef ito’ab naatu bai run ibunimih, o noukwat wanawanan tarafutimih. Baise ana sisikofamaim sikof, saise sabuw hinanan ana marakawin hina’itin boro hinarun.
34 Ojú ni fìtílà ara: bí ojú rẹ bá mọ́lẹ̀ kedere, gbogbo ara rẹ a mọ́lẹ̀; ṣùgbọ́n bí ojú rẹ bá ṣókùnkùn, ara rẹ pẹ̀lú a kún fún òkùnkùn.
34 Mata i biya ana hinow, mata gewasin biya etei boro marakawin. Baise mata kakafin biya etei boro nagugum.
35 Nítorí náà kíyèsi i, kí ìmọ́lẹ̀ tí ń bẹ nínú rẹ má ṣe di òkùnkùn.
35 Isan imih kwanakaifi gewas a marakaw biyamaim men kwaniwa’an nagugum.
36 Ǹjẹ́ bí gbogbo ara rẹ bá kún fún ìmọ́lẹ̀, tí kò ní apá kan tí ó ṣókùnkùn, gbogbo rẹ̀ ni yóò ní ìmọ́lẹ̀, gẹ́gẹ́ bí ìgbà tí fìtílà bá fi ìtànṣán rẹ̀ fún ọ ní ìmọ́lẹ̀.”
36 Biya tutufin etei namamarakaw na’at, biya turin boro men nagugum. Baise na biya wanawanan tutufin etei namarakaw, ramef ana marakaw tafamaim in ekukusisiyar na’atube.”
37 Bí ó sì ti ń wí, Farisi kan bẹ̀ ẹ́ kí ó bá òun jẹun: ó sì wọlé, ó jókòó láti jẹun.
37 Jesu iti tur eo in sasawar ufunamaim, Pharisee orot ta kok i boro Jesu hairi hitan ana baremaim bay hitaa. Imih Jesu ifefeyan hairi hina ana bar hitit naatu bay aa ana efanamaim mare.
38 Nígbà tí Farisi náà sì rí i, ẹnu yà á nítorí tí kò kọ́kọ́ wẹ ọwọ́ kí ó tó jẹun.
38 Baise Pharisee orot Jesu i’itin i men ofafar i’ufunun an souwibo na bay aa ana efanamaim mare, imih Pharisee orot ana kasiy ra’at.
39 Olúwa sì wí fún un pé, “Ẹ̀yin Farisi a máa ń fọ òde ago àti àwopọ̀kọ́: ṣùgbọ́n, inú yín kún fún ìwà búburú àti ìrẹ́jẹ.
39 Naatu Jesu iu, “Kwa Pharisee i a kerowas naatu a tew ufuhine kwa sasouwen, baise kwa dogor wanawanan i baribar kakafin naatu rougoy rabirabin.
40 Ẹ̀yin aṣiwèrè, ẹni tí ó ṣe èyí tí ń bẹ lóde, òun kò ha ṣe èyí tí ń bẹ nínú pẹ̀lú?
40 Kwabikoko’aw! God biya ufunane wowowab na’atube biya wanawanan auman wowowab men kwaso’ob?
41 Nípa ohun ti inú yin, ki ẹ̀yin kúkú máa ṣe ìtọrẹ àánú nínú ohun tí ẹ̀yin ní, sì kíyèsi i, ohun gbogbo ni ó di mímọ́ fún yín.
41 Imih a kerowas naatu a tew wanawanah abisa’awat tema’am yababan wairafih kwanitih hinaa, saise kwa a sawar etei boro hinigewasin.
42 “Ṣùgbọ́n ègbé ni fún yín, ẹ̀yin Farisi, nítorí tí ẹ̀yin a máa san ìdámẹ́wàá minti àti irúgbìn, àti gbogbo ewébẹ̀, ṣùgbọ́n ẹ̀yin kọ ìdájọ́ àti ìfẹ́ Ọlọ́run: wọ̀nyí jẹ́ ohun tí ẹ gbọdọ̀ ṣe, láìsí fi àwọn ìyókù sílẹ̀ láìṣe.
42 Yababan boro gagamin maiyow kwanab, kwa Pharisee sabuw! Anayabin kwa iti mint, rue, naatu adanafur afa God baitinin isan i men nuhi eburubur, mar etei ana mumusin God kwabitin, baise ma gewas naatu God ana yabow isan i nuhi eburubur, gewasin nati sawar i kwati’a’ait sawar afa auman kwatasinaf.
43 “Ègbé ni fún yín, ẹ̀yin Farisi, àgàbàgebè! Nítorí tí ẹ̀yin fẹ́ ipò ọlá nínú Sinagọgu, àti ìkíni ní ọjà.
43 Yababan boro kwanab, kwa Pharisee sabuw! Anayabin kwa a kok gagamin i Kou’ay Bar wanawanah efan gewasih kwanabow kwanamare kwanama, naatu ahar hai efanamaim a kok gagamin i sabuw a merar hinay naatu hinakakaf.
44 “Ègbé ni fún un yín,nítorí ẹ̀yin dàbí ibojì tí kò farahàn, tí àwọn ènìyàn sì ń rìn lórí rẹ̀ láìmọ̀.”
44 Yababan boro kwanab! Anayabin kwa i rah atamanih hai i’inanen en sabuw so’oba’e tafah hibat tereremor na’atube.”
45 Nígbà náà ni ọ̀kan nínú àwọn amòfin dáhùn, ó sì wí fún un pé, “Olùkọ́, nínú èyí tí ìwọ ń wí yìí ìwọ ń gan àwa pẹ̀lú.”
45 Ofafar so’obayan orot ta Jesu ibatiy, “Bai’obaiyenayan iti tur i’o i aki auman irabi.”
46 Ó sì wí pé, “Ègbé ni fún ẹ̀yin amòfin pẹ̀lú, nítorí tí ẹ̀yin di ẹrù tí ó wúwo láti rù lé ènìyàn lórí, bẹ́ẹ̀ ni ẹ̀yin tìkára yín kò jẹ́ fi ìka yín kan ẹrù náà.
46 Jesu iya’afut eo, “Kwa Ofafar Bai’obaiyenayah so’ob wairafi auman boro yababan kwanab. Anayabin bit gagamin na’in sabuw tuwabuh kwayara’ah hi’abar tun erarabih, naatu kwa i men kafa’imo uma ta baibais isan kwabitihimih.
47 “Ègbé ni fún yín, nítorí tí ẹ̀yin kọ́ ibojì àwọn wòlíì, tí àwọn baba yín pa.
47 Yababan boro kwanab! Anayabin dinab oro’orot kwa a’agir hirouw himomorob i hai rah kwama kwawowowab gaigiwas.
48 Ǹjẹ́ ẹ̀yin jẹ́ ẹlẹ́rìí, ẹ sì ní inú dídùn sí iṣẹ́ àwọn baba yín, nítorí tí wọn pa wọ́n, ẹ̀yin sì kọ́ ibojì wọn.
48 Imih kwa i taiyuw kwakukubuna, abisa a’agir hisisinaf a baibasit kwabitin, dinab oro’orot a’agir hirouw himorob naatu kwa i hai rah kwawowowab.
49 Nítorí èyí ni ọgbọ́n Ọlọ́run sì ṣe wí pé, ‘Èmi ni ó rán àwọn wòlíì àti àwọn aposteli sí wọn, wọn ó sì ṣe inúnibíni sí wọn.’
49 Anayabin iti isan, God ana so’obamaim eo ‘Ayu boro dinab oro’orot naatu kob abarayah aniyafarih, afa boro hina rouw hina morob, afa boro bai’akir kakafin hinab.’
50 Kí a lè béèrè ẹ̀jẹ̀ àwọn wòlíì gbogbo, tí a ti ta sílẹ̀ láti ìgbà ìpilẹ̀ṣẹ̀ ayé wá, lọ́wọ́ ìran yìí;
50 Isan imih kwa sabuw iti boun kwama’am, God ana dinab oro’orot tafaram aneika hirouw himomorob ana baimakiy i boro kwa kwanab.
51 láti ẹ̀jẹ̀ Abeli wá, títí ó sì fi dé ẹ̀jẹ̀ Sekariah, tí ó ṣègbé láàrín pẹpẹ àti tẹmpili. Lóòótọ́ ni mo wí fún yín ìran yìí ni yóò ru gbogbo ẹ̀bi àwọn nǹkan wọ̀nyí.
51 Abel ana rara’ika busuruf na Zechariah ana rara’amaim tit. Zechariah i Tafaror Baremaim iti sibor ana gem naatu Regah ana Bar Kakafiyin hairi hai founamaim hi’asabun morob. Imih anababatun a tur ao’owen kwa iti boun kwama’am iti sabuw hai baimakiy boro kwa kwanab.
52 “Ègbé ni fún yín, ẹ̀yin amòfin, nítorí tí ẹ̀yin ti mú kọ́kọ́rọ́ ìmọ̀ kúrò; ẹ̀yin tìkára yín kò wọlé, àwọn tí sì ń wọlé, ni ẹ̀yin ń dí lọ́wọ́.”
52 Kwa Ofafar Bai’obaiyenayah so’ob wairafi. Yababan boro kwanab. Anayabin etawan botawiyin run so’ob bain ana tufatan i kwa kwabobotan, naatu kwa iti bar i men kwakokok boro kwarun so’ob kwanab, baise sabuw afa run so’ob bainamih tisisinaftobon kwa i hai ef kwahirihir.”
53 Bí ó ti ń lọ kúrò níbẹ̀, àwọn akọ̀wé àti àwọn Farisi bẹ̀rẹ̀ sí bi í lọ́rọ̀ gidigidi, wọ́n sì ń yọ ọ́ lẹ́nu láti wí nǹkan púpọ̀.
53 Jesu efan nati bihamiy ana veya’amaim Ofafar Bai’obaiyenayah naatu Pharisee yah so’ar hiu kwanikwaniy naatu baibatebat moumurih na’in hibow hitit hibabatiy,
54 Wọ́n ń ṣọ́ ọ, wọ́n ń wá ọ̀nà láti rí nǹkan gbámú lẹ́nu kí wọn bá à lè fi ẹ̀sùn kàn án.
54 naatu hikubibiruw na’atube abisa tao kakaf na’at saise ubar hititin hitafatum isan.
Atalhos do teclado
- Capítulo anterior←
- Próximo capítulo→
- Versículo anteriork
- Próximo versículoj
- Limpar seleçãoEsc
- Esta ajuda?
Estude este capítulo no WhatsApp
Peça à IA da Bíblia Fala para explicar Lucas 11, comparar traduções ou montar um estudo — tudo direto pelo WhatsApp.