Josué 3
Biblica® ní oore ọ̀fẹ́ láti lo Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde-Òní (YOR) vs BKJ
1 Ní kùtùkùtù òwúrọ̀, Joṣua àti gbogbo àwọn Israẹli sí kúrò ní Ṣittimu, wọ́n sì lọ sí etí odò Jordani, wọ́n sì pa ibùdó síbẹ̀ kí wọn tó kọjá.
1 E Josué se levantou de manhã cedo; e eles saíram de Sitim e vieram ao Jordão, ele e todos os filhos de Israel, e ali se alojaram antes de atravessarem.
2 Lẹ́yìn ọjọ́ kẹta àwọn olórí la àárín ibùdó já.
2 E sucedeu que, depois de três dias, os oficiais foram pelo meio do acampamento;
3 Wọ́n sì pàṣẹ fún àwọn ènìyàn pé, “Nígbà tí ẹ bá rí àpótí ẹ̀rí Olúwa Ọlọ́run yín, tí àwọn àlùfáà tí wọ́n jẹ́ ọmọ Lefi rù ú, nígbà náà ni ẹ̀yin yóò sí kúrò ní ipò yín, ẹ̀yin yóò sì máa tẹ̀lé e.
3 e eles ordenaram ao povo, dizendo: Quando virdes a arca do pacto do SENHOR, vosso Deus, e os sacerdotes, os levitas carregando-a, então saireis do vosso lugar e a seguireis.
4 Ẹyin yóò lè mọ ọ̀nà tí ẹ ó gbà, torí pé ẹ̀yin kò gba ọ̀nà yìí tẹ́lẹ̀ rí. Ṣùgbọ́n àlàfo gbọdọ̀ wà ní àárín yín àti àpótí náà, tó bí ìwọ̀n ẹgbẹ̀rún méjì (2,000) ìgbọ̀nwọ́.”
4 Contudo, haverá um espaço entre vós e ela, cerca de dois mil côvados de medida; não venhais próximo a ela, para que possais saber o caminho pelo qual deveis ir, pois não passastes por este caminho até então.
5 Joṣua sì sọ fún àwọn ènìyàn pé, “Ẹ ya ara yín sí mímọ́, nítorí ní ọ̀la, Olúwa yóò ṣe ohun ìyanu ní àárín yín.”
5 E Josué disse ao povo: Santificai-vos, porque amanhã o SENHOR fará maravilhas no meio de vós.
6 Joṣua sọ fún àwọn àlùfáà pé, “Ẹ̀yin, ẹ gbé àpótí ẹ̀rí náà kí ẹ̀yin kí ó sì máa lọ ṣáájú àwọn ènìyàn.” Bẹ́ẹ̀ ni wọ́n gbé e sókè, wọ́n sì ń lọ ní iwájú u wọn.
6 E Josué falou aos sacerdotes, dizendo: Tomai a arca do pacto, e passai adiante do povo. E eles tomaram a arca do pacto, e foram antes do povo.
7 Olúwa sì sọ fún Joṣua pé, “Òní yìí ni Èmi yóò bẹ̀rẹ̀ sí í gbé ọ ga ní ojú u gbogbo àwọn ará Israẹli, kí wọn lè mọ̀ pé Èmi wà pẹ̀lú rẹ gẹ́gẹ́ bí mo ṣe wà pẹ̀lú Mose.
7 E o SENHOR disse a Josué: Neste dia começarei a te exaltar à vista de todo Israel, para que eles possam saber que, assim como eu estava com Moisés, também estarei contigo.
8 Sọ fún àwọn àlùfáà tí ó ru àpótí ẹ̀rí náà, ‘Nígbà tí ẹ bá dé etí omi Jordani, ẹ lọ kí ẹ sì dúró nínú odò náà.’ ”
8 E tu ordenarás aos sacerdotes que carregam a arca do pacto, dizendo: Quando chegardes à beira das águas do Jordão, permanecereis de pé e parados no Jordão.
9 Joṣua sì sọ fún àwọn ọmọ Israẹli pé, “Ẹ súnmọ́ ibí kí ẹ̀yin kí ó sì fetí sí ọ̀rọ̀ Olúwa Ọlọ́run yín.
9 E Josué disse aos filhos de Israel: Vinde para cá e ouvi as palavras do SENHOR, vosso Deus.
10 Èyí ni ẹ̀yin yóò fi mọ̀ pé Ọlọ́run alààyè wà ní àárín yín àti pé dájúdájú yóò lé àwọn ará Kenaani, àwọn ará Hiti, Hifi, Peresi, Girgaṣi, Amori àti Jebusi jáde níwájú u yín.
10 E Josué disse: Por meio disto sabereis que o Deus vivo está no meio de vós, e que ele, sem falta, expulsará de diante de vós os cananeus, os heteus, os heveus, os ferezeus, os girgaseus, os amorreus e os jebuseus.
11 Àpótí májẹ̀mú Olúwa gbogbo ayé ń gòkè lọ sí Jordani ṣáájú u yín.
11 Eis que a arca do pacto do Senhor de toda a terra passa adiante de vós, para dentro do Jordão.
12 Ǹjẹ́ nísinsin yìí, ẹ mú ọkùnrin méjìlá nínú àwọn ẹ̀yà Israẹli, ẹnìkan nínú ẹ̀yà kọ̀ọ̀kan.
12 Portanto, agora, tomai doze homens das tribos de Israel, de cada tribo um homem.
13 Bí àwọn àlùfáà tí ó ru àpótí Olúwa, Olúwa gbogbo ayé bá ti ẹsẹ̀ bọ odò Jordani, omi tí ń ti òkè sàn wá yóò gé kúrò yóò sì gbá jọ bí òkìtì kan.”
13 E sucederá que, tão logo as solas dos pés dos sacerdotes que carregam a arca do SENHOR, o Senhor de toda a terra, repousarem nas águas do Jordão, se separarão as águas do Jordão, e as águas, que vêm de cima, pararão amontoadas.
14 Nígbà tí àwọn ènìyàn gbéra láti ibùdó láti kọjá nínú odò Jordani, àwọn àlùfáà tí ó ru àpótí ẹ̀rí náà ń lọ níwájú wọn.
14 E sucedeu, quando o povo saiu das suas tendas, para atravessar o Jordão, e os sacerdotes carregando a arca do pacto diante do povo;
15 Odò Jordani sì máa ń wà ní kíkún ní gbogbo ìgbà ìkórè. Ṣùgbọ́n bí àwọn àlùfáà tí ó ru àpótí ẹ̀rí ti dé odò Jordani tí ẹsẹ̀ wọn sì kan etí omi,
15 e, quando aqueles que carregavam a arca chegaram ao Jordão, e os pés dos sacerdotes que carregavam a arca foram submersos na beira da água, (pois o Jordão transborda todas as suas margens durante todo o tempo da colheita)
16 omi tí ń ti òkè sàn wá dúró. Ó sì gbá jọ bí òkìtì ní òkèèrè, ní ìlú tí a ń pè ní Adamu, tí ó wà ní tòsí Saretani; nígbà tí omi tí ń sàn lọ sínú Òkun aginjù (ti o túmọ̀ sí Òkun Iyọ̀) gé kúrò pátápátá. Bẹ́ẹ̀ ni àwọn ènìyàn kọjá sí òdìkejì ní ìdojúkọ Jeriko.
16 que as águas que desciam de cima permaneceram e se ergueram em um amontoado mui distante da cidade de Adã, que está ao lado de Sartã; e as que desciam em direção ao mar da planície, que é o mar de sal, falharam, e foram separadas; e o povo atravessou direto em direção a Jericó.
17 Àwọn àlùfáà tí ó ru àpótí ẹ̀rí Olúwa sì dúró ṣinṣin lórí ilẹ̀ gbígbẹ ní àárín Jordani, nígbà tí gbogbo àwọn ọmọ Israẹli ń kọjá títí gbogbo orílẹ̀-èdè náà fi rékọjá nínú odò Jordani lórí ilẹ̀ gbígbẹ.
17 E os sacerdotes que carregavam a arca do pacto do SENHOR permaneceram firmes em terra seca no meio do Jordão, e todos os israelitas atravessaram em terra seca, até que todo o povo terminou de passar pelo Jordão.
Atalhos do teclado
- Capítulo anterior←
- Próximo capítulo→
- Versículo anteriork
- Próximo versículoj
- Limpar seleçãoEsc
- Esta ajuda?
Estude este capítulo no WhatsApp
Peça à IA da Bíblia Fala para explicar Josué 3, comparar traduções ou montar um estudo — tudo direto pelo WhatsApp.