Josué 21
Biblica® ní oore ọ̀fẹ́ láti lo Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde-Òní (YOR) vs BKJ
1 Báyìí ni olórí ìdílé àwọn ọmọ Lefi lọ bá Eleasari àlùfáà, Joṣua ọmọ Nuni àti olórí ẹ̀yà àwọn ìdílé ẹ̀yà Israẹli.
1 Então, os cabeças dos pais dos levitas se aproximaram de Eleazar, o sacerdote, e de Josué, o filho de Num, e dos cabeças dos pais das tribos dos filhos de Israel;
2 Ní Ṣilo, ní Kenaani, wọn sọ fún wọn pé, “Olúwa pàṣẹ nípasẹ̀ Mose pé kí wọn fún wa ní ìlú láti máa gbé àti ilẹ̀ pápá oko tútù fún ẹran ọ̀sìn wa.”
2 e eles lhes falaram em Siló, na terra de Canaã, dizendo: O SENHOR ordenou, pela mão de Moisés, que nos dessem cidades para habitar, com os seus arredores para o nosso gado.
3 Àwọn ọmọ Israẹli sì fún àwọn ọmọ Lefi ní àwọn ìlú wọ̀nyí, àti ilẹ̀ pápá oko tútù lára ilẹ̀ ìní tiwọn gẹ́gẹ́ bí Olúwa ti pàṣẹ fún Mose.
3 E os filhos de Israel deram da sua herança aos levitas, diante do mandamento do SENHOR, estas cidades e os seus arredores.
4 Ìpín kìn-ín-ní wà fún àwọn ọmọ Kohati, ní agbo ilé, agbo ilé. Àwọn ọmọ Lefi tí wọ́n jẹ́ ọmọ Aaroni àlùfáà ni a pín ìlú mẹ́tàlá fún láti ara ẹ̀yà Juda, Simeoni àti Benjamini.
4 E a sorte surgiu para as famílias dos coatitas; e os filhos de Arão, o sacerdote, que eram dos levitas, receberam por sorte da tribo de Judá, e da tribo de Simeão, e da tribo de Benjamim, treze cidades.
5 Ìyókù àwọn ọmọ Kohati ni a pín ìlú mẹ́wàá fún láti ara ẹ̀yà Efraimu, Dani àti ìdajì Manase.
5 E o restante dos filhos de Coate receberam, por sorte, das famílias da tribo de Efraim, e da tribo de Dã, e da meia tribo de Manassés, dez cidades.
6 Àwọn ẹ̀yà Gerṣoni ni a pín ìlú mẹ́tàlá fún láti ara ẹ̀yà Isakari, Aṣeri, Naftali àti ìdajì ẹ̀yà Manase ní Baṣani.
6 E os filhos de Gérson receberam, por sorte, das famílias da tribo de Issacar, e da tribo de Aser, e da tribo de Naftali, e da meia tribo de Manassés, em Basã, treze cidades.
7 Àwọn ọmọ Merari ní agbo ilé, agbo ilé ni wọ́n fún ní ìlú méjìlá láti ara ẹ̀yà Reubeni, Gadi àti Sebuluni.
7 Os filhos de Merari, pelas suas famílias, receberam da tribo de Rúben, e da tribo de Gade, e da tribo de Zebulom, doze cidades.
8 Báyìí ni àwọn ọmọ Israẹli pín ìlú wọ̀nyí àti ilẹ̀ pápá oko tútù fún àwọn ọmọ Lefi gẹ́gẹ́ bí Olúwa ti pàṣẹ láti ẹnu Mose.
8 E os filhos de Israel deram por sorte aos levitas, estas cidades com os seus arredores, como o SENHOR ordenou pela mão de Moisés.
9 Láti ara ẹ̀yà Juda àti ẹ̀yà Simeoni ni wọ́n ti pín àwọn ìlú tí a dárúkọ wọ̀nyí,
9 E eles entregaram da tribo dos filhos de Judá, e da tribo dos filhos de Simeão, estas cidades que aqui são mencionadas por nome,
10 (ìlú wọ̀nyí ni a fún àwọn ọmọ Aaroni tí ó jẹ́ ọ̀kan nínú ìdílé Kohati tí í ṣe ọmọ Lefi, nítorí tí ìpín àkọ́kọ́ jẹ́ tiwọn).
10 e que pertenceram aos filhos de Arão, das famílias dos coatitas, que eram dos filhos de Levi; pois a eles caiu a primeira sorte.
11 Wọ́n fún wọn ní Kiriati-Arba (tí í ṣe, Hebroni), pẹ̀lú ilẹ̀ pápá oko tútù tí ó yí wọn ká, ní ilẹ̀ òkè Juda. (Arba ni baba ńlá Anaki.)
11 E eles lhes deram a cidade de Arba, do pai de Anaque, que é Hebrom, na região montanhosa de Judá, com os seus arredores.
12 Ṣùgbọ́n àwọn oko àti àwọn abúlé ní agbègbè ìlú náà ni wọ́n ti fi fún Kalebu ọmọ Jefunne gẹ́gẹ́ bí ohun ìní rẹ̀.
12 Porém, os campos da cidade, e as suas aldeias, deram a Calebe, filho de Jefoné, para a sua posse.
13 Ní àfikún wọ́n sì fún àwọn ọmọ Aaroni tí í ṣe àlùfáà ní Hebroni (ọ̀kan nínú ìlú ààbò fún àwọn apànìyàn) pẹ̀lú ilẹ̀ pápá oko tútù rẹ̀, Libina,
13 Então, eles deram aos filhos de Arão, o sacerdote, Hebrom com os seus arredores, para ser uma cidade de refúgio para o homicida; e Libna, com os seus arredores,
14 Jattiri, Eṣitemoa,
14 e Jatir, com os seus arredores, e Estemoa, com os seus arredores,
15 Holoni àti Debiri,
15 e Holom, com os seus arredores, e Debir, com os seus arredores,
16 Aini, Jutta àti Beti-Ṣemeṣi, pẹ̀lú ilẹ̀ pápá oko wọn. Ìlú mẹ́sàn-án láti ara ẹ̀yà méjì wọ̀nyí.
16 e Aim, com os seus arredores, e Jutá, com os seus arredores, e Bete-Semes, com os seus arredores: nove cidades destas duas tribos.
17 Láti ara ẹ̀yà Benjamini ni wọ́n ti fún wọn ní:
17 E da tribo de Benjamim, Gibeão com os seus arredores, Geba com os seus arredores,
18 Anatoti àti Almoni, pẹ̀lú ilẹ̀ pápá oko wọn, wọ́n jẹ́ ìlú mẹ́rin.
18 Anatote com os seus arredores, e Almom com os seus arredores: quatro cidades.
19 Gbogbo ìlú àwọn àlùfáà, ìran Aaroni jẹ́ mẹ́tàlá pẹ̀lú ilẹ̀ pápá wọn.
19 Todas as cidades dos sacerdotes, filhos de Arão, eram treze cidades, com os seus arredores.
20 Ìyókù ìdílé Kohati tí ó jẹ́ ọmọ Lefi ní a pín ìlú fún láti ara ẹ̀yà Efraimu.
20 E as famílias dos filhos de Coate, os levitas que restaram dos filhos de Coate, eles receberam as cidades da sua sorte da tribo de Efraim.
21 Ní ilẹ̀ òkè Efraimu wọ́n fún wọn ní:
21 Pois eles lhes deram Siquém, com os seus arredores, no monte Efraim, para ser uma cidade de refúgio para o homicida, e Gezer com os seus arredores,
22 Kibasaimu àti Beti-Horoni, pẹ̀lú ilẹ̀ pápá oko wọn jẹ́ ìlú mẹ́rin.
22 e Quibzaim com os seus arredores, e Bete-Horom com os seus arredores: quatro cidades.
23 Láti ara ẹ̀yà Dani ni wọ́n ti fún wọn ní:
23 E da tribo de Dã, Elteque com os seus arredores, Gibetom com os seus arredores,
24 Aijaloni àti Gati-Rimoni, pẹ̀lú ilẹ̀ pápá oko tútù wọn jẹ́ ìlú mẹ́rin.
24 Aijalom com os seus arredores, Gate-Rimom com os seus arredores: quatro cidades.
25 Láti ara ìdajì ẹ̀yà Manase ni wọ́n ti fún wọn ní:
25 E da meia tribo de Manassés, Taanaque com os seus arredores, e Gate-Rimom com os seus arredores: duas cidades.
26 Gbogbo ìlú mẹ́wẹ̀ẹ̀wá yìí àti ilẹ̀ pápá wọn ni a fi fún ìyókù ìdílé Kohati.
26 Eram dez, todas as cidades com seus arredores, para as famílias dos filhos que restaram de Coate.
27 Àwọn ọmọ Gerṣoni ìdílé àwọn ọmọ Lefi ni wọ́n fún lára:
27 E aos filhos de Gérson, das famílias dos levitas, da outra metade da tribo de Manassés eles deram Golã, em Basã, com os seus arredores, para ser uma cidade de refúgio para o homicida, e Beesterá com os seus arredores: duas cidades.
28 Láti ara ẹ̀yà Isakari ni wọ́n ti fún wọn ní,
28 E da tribo de Issacar, Quisião com os seus arredores, Daberate com os seus arredores,
29 Jarmatu àti Eni-Gannimu, pẹ̀lú ilẹ̀ pápá oko wọ́n jẹ́ ìlú mẹ́rin.
29 Jarmute com os seus arredores, En-Ganim com os seus arredores: quatro cidades.
30 Láti ara ẹ̀yà Aṣeri ni wọ́n ti fún wọn ní
30 E da tribo de Aser, Misal com os seus arredores, Abdom com os seus arredores,
31 Helikati àti Rehobu, pẹ̀lú ilẹ̀ pápá oko wọ́n jẹ́ ìlú mẹ́rin.
31 Helcate com os seus arredores, e Reobe com os seus arredores: quatro cidades.
32 Láti ara ẹ̀yà Naftali ni a ti fún wọn ní:
32 E da tribo de Naftali, Quedes, na Galileia, com os seus arredores, para ser uma cidade de refúgio para o homicida; e Hamote-Dor com os seus arredores, e Cartã com os seus arredores: três cidades.
33 Gbogbo ìlú tí ó jẹ́ ti ọmọ Gerṣoni jẹ́ mẹ́tàlá, pẹ̀lú ilẹ̀ pápá oko wọn.
33 Todas as cidades dos gersonitas, segundo as suas famílias eram treze cidades com os seus arredores.
34 Láti ara ẹ̀yà Sebuluni ni a ti fún ìdílé Merari (tí í ṣe ìyókù ọmọ Lefi) ní:
34 E para as famílias dos filhos de Merari, o restante dos levitas, da tribo de Zebulom, Jocneão com os seus arredores, e Cartá com os seus arredores,
35 Dimina àti Nahalali, pẹ̀lú ilẹ̀ pápá oko wọn, wọ́n jẹ́ ìlú mẹ́rin.
35 Dimna com os seus arredores, Naalal com os seus arredores: quatro cidades.
36 Láti ara ẹ̀yà Reubeni ni wọ́n ti fún wọn ní
36 E da tribo de Rúben, Bezer com os seus arredores, e Jaza com os seus arredores,
37 Kedemoti àti Mefaati, pẹ̀lú ilẹ̀ pápá oko wọ́n jẹ́ ìlú mẹ́rin.
37 Quedemote com os seus arredores, e Mefaate com os seus arredores: quatro cidades.
38 Láti ara ẹ̀yà Gadi ni wọ́n ti fún wọn ní
38 E da tribo de Gade, Ramote, em Gileade, com os seus arredores, para ser uma cidade de refúgio para o homicida; e Maanaim com os seus arredores,
39 Heṣboni àti Jaseri, e pẹ̀lú ilẹ̀ pápá oko wọ́n jẹ́ ìlú mẹ́rin.
39 Hesbom com os seus arredores, Jazer com os seus arredores: ao todo quatro cidades.
40 Gbogbo ìlú tí wọ́n pín fún àwọn ọmọ Merari tí wọ́n jẹ́ ìyókù àwọn ọmọ Lefi jẹ́ méjìlá.
40 Então, todas as cidades para os filhos de Merari, por suas famílias, que eram remanescentes das famílias dos Levitas, eram por sua sorte, doze cidades.
41 Gbogbo ìlú àwọn ọmọ Lefi tó wà láàrín ara ilẹ̀ àwọn ọmọ Israẹli jẹ́ méjìdínláàádọ́ta lápapọ̀ pẹ̀lú pápá oko wọn.
41 Todas as cidades dos levitas, dentro da possessão dos filhos de Israel, eram quarenta e oito cidades com os seus arredores.
42 Ọ̀kọ̀ọ̀kan ìlú wọ̀nyí ni ó ni ilẹ̀ pápá oko tí ó yí ì ká, bẹ́ẹ̀ náà ló rí fún gbogbo ìlú wọ̀nyí.
42 Estas cidades eram, cada qual, com os seus arredores ao redor: assim eram todas estas cidades.
43 Báyìí ni Olúwa fún Israẹli ní gbogbo ilẹ̀ tí ó ṣèlérí láti fi fún àwọn baba ńlá wọn. Nígbà tí wọ́n sì gbà á tan wọ́n sì tẹ̀dó síbẹ̀.
43 E o SENHOR deu a Israel toda a terra que jurou dar aos seus pais; e eles a possuíram, e nela habitaram.
44 Olúwa sì fún wọn ní ìsinmi ní gbogbo ọ̀nà, gẹ́gẹ́ bí ó ti ṣèlérí fún baba ńlá wọn. Kò sì sí ọ̀kankan nínú àwọn ọ̀tá wọn tí ó lè dojúkọ wọ́n. Olúwa sì fi gbogbo àwọn ọ̀tá wọn lé wọn ní ọwọ́.
44 E o SENHOR lhes deu repouso ao redor, segundo tudo que jurou aos seus pais; e diante deles não ficou de pé nenhum homem de todos os seus inimigos; o SENHOR entregou todos os seus inimigos na sua mão.
45 Kò sí ọ̀kan nínú ìlérí rere tí Olúwa ṣe fún ilé Israẹli tí ó kùnà, gbogbo rẹ̀ ni ó ṣe.
45 Nada falhou de toda coisa boa que o SENHOR havia falado à casa de Israel; tudo se cumpriu.
Atalhos do teclado
- Capítulo anterior←
- Próximo capítulo→
- Versículo anteriork
- Próximo versículoj
- Limpar seleçãoEsc
- Esta ajuda?
Estude este capítulo no WhatsApp
Peça à IA da Bíblia Fala para explicar Josué 21, comparar traduções ou montar um estudo — tudo direto pelo WhatsApp.